text,label,language "ìdílé. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "Hilahilo lori ọgọrọ ero to n wọ lu ileeṣẹ ajọ iforukọsilẹ kaadi idanimọ lorilẹede Naijiria, NIMC ti mu ki ọpọlọpọ awọn ọmọ Naijiria to wa loke okun ti ko tii gba nọmba naa o maa ko aya soke. 'Ọ̀lọ́pàá shátà mi láti Mowe dé Magboro dé Shagamu, wọ́n ní ṣé mi ò mọ̀ pé ìjọ́ba ni mo ṣiṣẹ́ fún' Amọṣa o, ajọ NIMC ti fi wọn lọkan balẹ pe ko si ewu ati pe awọn ti ṣeto awọn ibudo iforukọsilẹ kan loke okun ti wọn ti lee lọ gba nọmba idanimọ apaps ilẹẹwa , NIN tiwọn lẹyin ti wọn ba forukọsilẹ. Ọjọ kọkandinlogun oṣu kinni ọdun 2021 ni ijọba apapọ Naijiria ti sun gbedeke ṣiṣeto asopọ nọmba idanimọ apapọ ilẹ Naijiria, NIN ati nọmab ibanisọrọ awọn ọmọ orilẹede Naijiria kọọkan mọ si bayii. Amọṣa, fun awọn ti ko ba tii fi orukọ silẹ rara, gbedeke ọjọ kẹsan oṣu keji ọdun 2021 ni wọn fun wọn. Eyi ni ibi ti awọn ibudo iforukọsilẹ fun NIN wa kaakiri orilẹede agbaye. Bakan naa, ileeẹ ibaraẹnisọrọ ni ijọba apapọ pẹlu ti gbe ilana bi o ṣe lee yanju fọọmu iforukọsilẹ fun kaadi idanimọ apapọ naa lati gba nọmab idanimọ NIN rẹ. Loju opo ẹyẹnkọrin Twitter wọn ni wọn ti kọ ọ si pe ẹnikẹni to ba nilo fọọmu naa lee daa latori ikanni wọn. Loju opo twitter yii ni ẹ ti lee ri fọọmu naa gba: https://twitter.com/nimc_ng/status/1340677445435973633 Bayii ni fọọmu naa ṣe ri. Wo àwọn nǹkan to tún nílò NIN fún yàtọ̀ fún ìforúkọsílẹ̀ síìmù Laipẹ yii ni ajọ to n risi ibaraẹnisọrọ ni Naijiria, NCC fi aṣẹ sita pe, gbogbo ọmọ Naijiria to n lo siimu ẹrọ ibaraẹnisọrọ, gbọdọ fi NIN kun iforukọsilẹ siimu wọn. Gbedeke ọsẹ meji pere si ni ajọ naa fi silẹ lati sẹ bẹ ẹ. Amọ yatọ si iforukọsilẹ siimu, awọn nnkan mii wa ti o tun nilo NIN rẹ fun gẹgẹ bii ọmọ Naijiria. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Apo asunwọn banki: Awọn banki ni Naijiria ma n gba NIN gẹgẹ bi ami idanimọ, ki wọn o to le ṣi apo asunwọn pẹlu wọn, tabi bẹrẹ si ni lo asunwọn ti o ko lo fun igba pipẹ pada. Iforukọsilẹ fun iwe irinna: Ajọ to n risi iwọle-wọde ni Naijiria ti sọ ọ di dandan fun ẹnikẹni to ba fẹ ẹ gba iwe irinna pasipọọti tuntun, tabi tun ti akọkọ ṣe, gbọdọ ṣe afihan NIN rẹ ko to o di ṣisẹ. Iwe aṣẹ fun ọkọ wiwa: Ajọ ẹṣọ oju popo, FRSC, naa ti n beere fun NIN lọwọ ẹnikẹni to ba fẹ ẹ gba laisẹnsi gẹgẹ bi awakọ. Laisi NIN, o ko ni le gba iwe aṣẹ fun ọkọ wiwa. Baruwa Gas Explosion: Àwọn tó forí sọta ìjàmbá iná ń bẹ ìjọba láti dìde ìrànwọ́ Ọna to le gba lati ri nọmba idanimọ NIN rẹ gba?Ninu alaye ti ajọ to n ṣakoso eto idanimọ ni Naijiria, NIMC ṣe, wọn ni ki awọn ọmọ Naijiria ṣa ti tẹ nọmba *346# lori foonu wọn lati ri nọmba yii.Gbogbo atotonu to n waye lori nọmba yi ko sẹyin bi ajọ NCC ṣe gbe gbendeke ọlọsẹ meji kale O ti di dandan bayii ki gbogbo awọn to n lo foonu Alagbeka o pese nọmba yi bi won ko ba fẹ ki wọn wọgile opo ibaraẹnisọrọ wọn.Gbogbo ẹni to ba n lo opo MTN, Airtel, 9mobile ati Glo lo le lo nọmba yiNCC salaye pe o di dandan ki gbogbo ẹni to ba ni siimu lati je ki iroyin wọn pe perepere. Fun awọn ẹlẹrọ Alagbeka ti ko ba ti forukọsilẹ tẹlẹ ilana ti wọn le tele ree: 1) Igbesẹ akọkọ:Ko iroyin nipa re sí inú fọọmu NIMC loju opo wọn tii ṣe: https://penrol.nimc.gov.ng/loginForm.tpl.html.phpRi i pe ohun to ba yẹ lọ kọ sí gbogbo aaye ti wọn lò ṣe pataki to wa ninu fọọmu naa.Ṣe ẹda fọọmu naa ko si tẹ iwe pelebe to jẹri sí pe o kan sí ojú òpó naa. Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsèjẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọ 2) Igbesẹ Kejì: Fi iwe ti o ti fi forukọ silẹ si ṣọwọ si wọn. Kàn sí ilé iforukọsilẹ NIMC to sunmọ ọ pẹlu ojulowo iwe idanimo to ba yẹ Kollington ṣàlàyé bí orin Fuji ṣe bẹ̀rẹ̀ gan an ní Nàiìjíríà Bi o ba ti debẹ kan si kanta oṣiṣẹ wọn ti yoo ṣe ayẹwo gbogbo ìwé tó kọ lọwọ Ti gbogbo nkan rẹ bá pé daada oṣiṣẹ yi yoo gba oju ika rẹ mẹwẹwaa silẹ to fi mọ àwòrán oju rẹ. Lẹyìn naa lo wa lọ gba iwe ẹri pe o ti kọja ìpele yi. 3) Igbesẹ 3Gba nọmba NIN rẹ Bi ọjọ meji sí mẹta ni wọn yóò lo ki o to le gba iwe ẹri nọmba yi lẹyin ti wọn gba oju ika rẹ àti àwòrán oju rẹ silẹ O ṣeeṣe ki o pe ki o to ri nọmba yi gba nigba miran nitori NIMC yoo ni lati ṣe ayẹwo to peye. O ni lati fi iwe ẹri yi pamọ daada ki o ba le fi han asiko to ba fẹ gba iwe ẹri nọmba NIN rẹ Africa Eye: Wo ìtàn ìyá kan ìyá kan àtàwọn olè ajọ́mọgbé tó n ta ọmọ ní Kenya Bi o ti ṣe lè mọ ti kaadi Nimc rẹ bá ti ṣetán fún gbígba? Kan sí oju opo ajọ National Identity Management Commission [NIMC] tii ṣe www.nimc.gov.ng Sun si oju ikansiraeni ìkíni káàbọ̀ ki o si tẹ ami afihan 'e-ID Card Status Portal' lati mọ ti kaadi rẹ ba ti wa nilẹ fún gbígba. Lẹyìn náà kọ orukọ rẹ ti baba rẹ ki o si wo boya kaadi rẹ ti wa nilẹ fun gbigba.",0,yoruba "rere. Bàbá lo ni ìgbà mi owó àkokò, Ìyá lo tun se joko.",0,yoruba dídì yìí ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọba lo lọ.,0,yoruba nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọba lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jẹ́ dára jù...,0,yoruba "onà.. Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.",0,yoruba "Wáyà iná já lu ẹlẹ́wọ̀n mẹ́ta lọ́gbà ẹ̀wọ̀n l'Eko, ọ̀pọ̀ w'à níléèwòsàn Iroyin ti a gbọ sọ pe ọpọ awọn ẹlẹwọn miran ni wọn wa lẹsẹkan aye, ẹsẹ kan ọrun bayii nitori iṣẹlẹ naa. Ohun ti oṣiṣẹ ajọ ẹlẹwọn kan nibẹ ti a fi orukọ bo laṣiri ṣalaye ni pe ina ọba to ṣa dede lagbara lori awọn waya ina kan lọgba ẹwọn naa lo ṣokunfa iṣẹlẹ buruku ọhun. O fi kun un pe waya ina naa lo ja lori ibusun kan tawọn ẹlẹwọn sun si to fi di pe awọn mẹta jalaisi bo ṣe ṣẹlẹ. O ni awọn mẹta lo ku loju ẹsẹ ti awọn yooku si ti n gba iwosan nileewosan ọgba ẹwọn naa. FUTA: Àwọn mẹ́jọ ló ṣíná ìyà fún Bolu ní FUTA O ni ka ni alẹ ni iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ ni, ko ba buru ju bo ti jẹ naa lọ. O ni ọpọ awọn ẹlẹwọn lo ti dide ti wọn si ti n kọri si ile ẹjọ koowa wọn fun igbẹjọ gbogbo to kan wọn lasiko to fi waye. Minsita feto ọrọ abo abẹle Rauf Aregbesọla naa ti balẹ si ọgba ẹwọn naa. Ni kete ti o ba ti bawọn akọroyin wa to wa nibẹ sọrọ la o bun yin gbọ. World Aids Day: Wo bí kòkòrò ààrùn HIV se bẹ̀rẹ̀ lágbàyé!",0,yoruba dídì yìí ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìwà: ti o dara.,0,yoruba "Ẹgbẹ awọn dokita ti fesi si aṣẹ ti ile ẹjọ pa lọsan ọjọ Ẹti pe ki wọn pada sí ẹnu iṣẹ wọn ki wọ́n si pada lọ se ipade pẹlu ijọba lórí ẹ̀hónú wọn. Wọn ni awọn ti ṣetan lati gbe ẹjọ naa lọ si ile ẹjọ ko tẹmi lọrun, ẹgbẹ awọn dokita ni awọn ti jẹ ki agbẹjọro ẹgbẹ naa mọ pe awọn yoo pe idajọ ile ẹjọ nija lati lọ si ile ẹjọ kotémilọrun ati pe ọmọ ẹgbẹ kankan ko ni pada si ẹnu isẹ. Ikede yii waye ninu atẹjade kan ti aarẹ awọn ọmọ ẹgbẹ dokita Dokita Uyilawa Okhuaihesuyi ati akọwe ẹgbẹ naa Dokita Jerry Isogun jùmọ̀ fọwọ si lonii. O ni awọn ti bẹrẹ igbesẹ gbigbe ẹjọ naa lọ si ile ẹjọ kotẹmilọrun. '' Gẹgẹ bi a se mọ, paapa julọ awọn to wa ni ile ẹjọ lonii nibi ti ile ẹjọ to n gbọ ẹjọ osisẹ ti pasẹ lori ẹjọ ti ijọba apapọ ati ẹgbẹ awọn dokita pe, idajọ naa ko tẹ wa lọrun "" "" Lẹyin ti a fi ikuluku pẹlu agbẹjọro wa, ati ni ki o pe ẹjọ kotẹmilọrun ki o si pe fun ki idajọ naa duro titi wọn yoo fi pe ẹjọ"". Saaju ni oni yii ni ile ẹjọ ti ni ki awọn dokita ile iwosan ijọba pada si ẹnu iṣẹ ninu idajọ ti Adajọ Bashar Alkali ṣe pe ki wọn pada si ẹnu isẹ Ile- ẹjọ to n gbọ awuye-wuye Lori iyanselodi laarin ijọba apapọ (Nigeria Industrial court) ati ẹgbẹ awọn dokita lorile ede Naijiria ti paa laṣẹ pe ki wọn pada sẹnu ise wọn ni kiakia. Ki wọn si bere ise wọn leye o-sọka Bakan naa, ni ile -ejo tun paa lase pe ki egbe awon dokita ati ijoba lo fori-kori Lati yanju aawọ to wa laarin wọn ni itubi-inubi. Bakan naa,ni ile -ẹjọ tun ni ki awọn agbejọrọ ijọba ati ẹgbẹ awọn dọkita lo forikori, ki wọn si mu ojo ti wọn yoo pada wa sile ẹjọ Adajo Basha.A.Alkali lo dajo bẹẹ pe ki awon dokita pada senu ise won ni kiakia Femi Aborisade to be agbẹjọro fun ẹgbẹ awọn dokita to gun le iyanselodi ti ni awọn yoo forikori pẹlu awọn onibara wọn, iyen ẹgẹe awọn dokita boya wọn yoo tesiwaju nibi ẹjọ to wa nile ẹjọ kotẹmilọrun, tabi ki wọn fopin si iyanselodi ohun Oni ni ile ẹjọ to n ri si ọrọ awọn oṣiṣẹ ati ileeṣẹ, NIC niluu Abuja yoo ṣe idajọ lori awuyewuye owo oṣu ati owo ajẹmọnu awọn dokita ati ijọba apapọ. Adajọ Bashar A. Alkali sun igbẹjọ naa si ọjọ Ẹti oni lasiko igbẹjọ to waye ni Ọjọru. Awọn dokita ti n yanṣẹlodi lati ọsẹ meloo kan bayii lati fẹhonu han lori owo ti wọn ni ijọba n jẹ awọn. Agbẹjọro ẹgbẹ awọn dokita, Femi Falana (SAN) ti kọkọ sọ pe ile ẹjọ naa ko lagbara to lati gbọ ẹjọ naa. Ṣugbọn aggbẹjọro ijọba apapọ, Tochukwu Maduka, ni ko si ọrọ ninu ohun ti Falana n sọ. Falana tun rọ ile ẹjọ pa ko paṣẹ wi pe ki ijọba ati ẹgbẹ awọn dokita pada lọ jiroro lori ati yanju ọrọ owo to da wahala silẹ. Awon Dokita ti wa nile ẹjọ bayii niluu Abuja fun idajọ lori ọrọ naa. Awon agbẹjọro to n ṣoju fun ẹgbẹ awon dokita ile iwosan ati aṣoju ẹgbẹ awọn dokita ile iwosan orile ede Naijiria si ti n fori kori.",0,yoruba ṣe àwọn iṣẹ́ tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ẹkọ́: ti o nuni ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba "Ìjọba ààrẹ Buhari ti ní àwọn gbé ìgbésẹ̀ náà lẹ́yín ìwádìí ẹ̀sùn ìwà àjẹbánu tí wọ́n fi kàn wọ́n. Ninu atẹjade ti Aarẹ Buhari fi lede lo ti ni Ọjọgbọn Charles Uwakwe, Bamidele Olure, Shina Adetona, Tayo Odukoya ati Babatunde Aina ni wọn ti kọkọ fun ni iwe lo gbele rẹ fun igba diẹ ki wọn fi ṣe iwadii finifini ẹsun iwa ajẹbanu ti wọn fi kan wọn. Wọn ni Uwakwe jẹbi ẹsun lilo owo ajọ naa basubasu gẹgẹ bi ofin ajọ naa ti ọdun 2007 sẹ tako iwa ajẹbanu bẹẹ. Aarẹ wa kesi i lati da gbogbo ẹru ijọba to wa ni ọwọ rẹ pada fun adele dari ajọ naa to wa nibẹ lọwọlọwọ. Bakan naa ninu atẹjade ohun ni wọn ti sọ wi pe Arakunrin Bamidele Olure to jẹ adari ẹka isuna ni ajọ NECO lo jẹbi ẹsun ṣiṣẹ owo ajọ naa to wa ni ikawọ rẹ basubasu, ti ko si yẹ ni adari ẹka naa mọ. Ọmọwe Dokita, Shina Adetona ni wọn fẹsun kan ni tirẹ pe o ṣẹ jibiti, to si ṣe magomago pẹlu akọsilẹ awọn oṣiṣẹ. Tayo Odukoya ni wọn le nitori oun naa ṣẹ magomago to tako ofin ajọ naa, nigba ti wọn si le agbẹjọrọ Babatunde Aina nitori o yi akọsilẹ pade, ti o si ṣe magomago nipa tita ile igbe ajọ naa. Bakan naa ni Minisita fun eto ẹkọ, Mallam Adamu Adamu wa paṣẹ fun awọn adari ajọ naa lati bẹrẹ igbesẹ lati gba gbogbo owo ti wọn fi ọna ẹru gba pada lọwọ wọn. Ti a ko gbagbe, Ọjọ Kẹwa, Osu Karun un ọdun 2018 ni ijọba kọ iwe lo gbe ile rẹ fun igba diẹ si ọjọgbọn Uwakwe fun iwadii ẹsun jẹgudujẹra ti wọn fi kan an ati awọn meji miran.",0,yoruba "Ìjẹ̀. Nitori eyi, ara eni lo je ti ibile.",0,yoruba owo ṣẹlẹ ni Eko ti gbogbo eniyan sọ o dara. (2001),0,yoruba "Nílẹ̀ẹ Yorùbá, onírúurú nǹkan tí ẹnu ń jẹ ni a lè pè ní àkàrà, látàríi bí a ti ṣe ṣe ohun jíjẹ ọ̀hún. Àwọn oúnjẹ wo wá ni #Akara? #AlayeOro",0,yoruba "Ara meeriri, mo ri ori ologbo lori atẹ ni ọrọ isẹlẹ kan to waye nigba ti wolii kan ni ki awọn ọmọ ijọ rẹ sin laaye, ki oun si pada jinde, amọ to gba ibẹ ku fin-fin. Idile ẹlẹni marun kan lo pe wolii wa sinu ile wọn lati wa se isẹgun fun wọn to wa ni abule Mazonde, lorilẹ-ede Zambia, lati le awọn ẹ̀mí buburu jade. A gbọ pe ni ṣe ni Wolii Shamiso Kanyama sọ fun awọn ọmọ ẹyin rẹ pe ki wọn o sin oun laaye, ki oun ba le ke pe awọn agbara ìwẹ̀nùmọ́ ti yoo wo ẹbí naa ṣàn kuro lọwọ agbara ati airi to n pa wọn ni ipakupa. Lẹyin naa lo darapọ mọ àwọn ọmọ ẹ̀yìn rẹ lati gbẹ ibojì to fẹ ki wọn o sin oun si. Ṣe ẹni ba rán ni nisẹ laa bẹru, a kii bẹru ẹni ti a o jẹ ẹ fun, n se ni àwọn eniyan naa ṣe bi Ọga wọn ṣe sọ, lẹyin to gbadura, to si bẹ sinu iboji fúnra rẹ, wọn ko iyẹpẹ le e lori bi oku. Sugbọn ọrọ gba ibomiran yọ nigba ti awọn ọkunrin naa pada gbẹ iboji naa lati wo o boya wolii ti jinde bo ṣe sọ, oku rẹ ni wọn ba. Wọn ti wa fi ẹsun ipaniyan kan eeyan marun-un ninu ẹbí naa lẹyin ti wolii naa, ti wọn pe si ile wọn fun eto adura, jade laye. Awọn iwe iroyin abẹle nibẹ sọ pe, awọn afurasi marun-un naa farahan niwaju ile ẹjọ giga kan ni Harare, fun ẹsun pe wọn lọwọ si iku wolii Shamiso Kanyama, lasiko to n sisẹ iṣegun fun wọn. Ẹnikan to rojọ tako àwọn eniyan naa nile ẹjọ, Father Zvidzai sọ pe, lootọ ni wolii naa ṣe bẹẹ, sugbọn oun gbiyanju lati da awọn eniyan naa duro nigba ti wọn bu iyẹpẹ diẹ le e lori, àmọ́ wọn ko gbọ. ""Mo kilọ fun awọn ọkunrin naa pe o lewu láti sin eeyan laaye, sugbọn wọn ko gbọ. Koda, Wolii Kanyama pariwo mọ mi pe mo n di àwọn angẹli oun lọwọ, to si ni ki wọn o tẹsiwaju lati ma a rọ iyẹpẹ sinu iboji naa.""",0,yoruba oòrùn ti wọ̀ nílẹ̀ yìí báyìí ìyẹn jẹ́ àṣekágbá fún ọdúnnìí ọ̀la loòrùn ó tún là ìyẹn lọ́dún titun kọ́lọ́run ṣọ́ wa,0,yoruba "Idi ni pe ile asofin kẹfin pe owo naa ti wọ apo aladani kan. Ẹgbẹ agbabọọlu ipinlẹ Osun ọhun, ti o n jẹ Prime FC, ni Ighalo ti gba bọọlu kẹyin ko to lọ si ilẹ okeere, nibi to ti darapọ mọ ẹgbẹ agbabọọlu Norwegian kan ni Lyn Oslo lọdun 2007. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọkan lara awọn to sun mọ kọmisọna to n ri si ọrọ ere idaraya Yemi Lawal, wa lara awọn ti wọn pe si ipade ni ile igbimọ asofin fun iwadii ọrọ naa lọsẹ to kọja. Bakan naa, ni awọn miran to tun wa nibi ipade ti alaga igbimọ ile lori ọrọ ere idaraya, Abdullahi Adegbile pe ni awọn Alakoso ẹgbẹ agbabọọlu Osun United. Akọwe ẹgbẹ agbabọọlu naa, Kabiru Adekunle ati adele adari igbimọ alabojuto ere idaraya ni Osun, Rotimi Oludunmoye naa peju si bẹ pẹlu. Bakan naa ni wọn darukọ Gbenga Ololade to jẹ adari Prime FC nigba naa, gẹgẹ bi ọkan lara awọn to mọ nipa owo ti wọn fi ra Ighalo lọ nigba naa. Alaga igbimọ ile asofin fun ere idaraya, Adegbile salaye pe, igbimọ naa ko ti pari iwadii wọn lori ọrọ naa. SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike ""Lẹyin ti a gbọ iroyin, a pe gbogbo awọn ti ọrọ kan. Lẹyin iwadii lẹkunrẹrẹ, mo fi n da yin loju pe a sọ abajade nkan to ṣẹlẹ ni gbangba, a o si tun wọn pe ninu ọsẹ yii."" Ọkan lara awọn oṣiṣẹ Osun United ti ko fẹ ki orukọ oun jade, sọ fun ile iṣẹ iroyin Punch pe, ẹgbẹrun mẹwaa pọun wọle sinu akanti banki Access Osun United, ninu oṣu kaarun ọdun. O fi kun pe, aarẹ ẹgbẹ agbabọọlu naa tẹlẹ ati adari ile iṣẹ to n ri si ọrọ ere idaraya lọwọ, nikan ni wọn le buwọlu iwe owo akanti ọhun. O ni ipade pẹlu ile igbimọ asofin ko tii ni iyanju. Toyin Atoyebi mechanic: Ẹ wo Toyin, ọmọbinrin ọdún 16 tó ń tún skadà àti gẹnẹrátọ̀ ṣe ní ""Ko si aniani, owo wọle si apo owo Osun United, sugbọn wọn ko tilẹ bun awọn alaṣẹ Osun United to ni akanti naa leti rara. ""Alaga igbimọ naa ni ki a tun pada wa fun ipade miran lori ọrọ ọhun ni ọjọ Eti to kọja, sugbọn o ṣeni laanu pe, awọn ọmọ ile igbimọ asofin ko yọju. Ololade, to jẹ adari Prime FC lasiko naa salaye pe, ile igbimọ asofin wa lori ọrọ naa ati pe, wọn ti kilọ fun awọn pe ẹnikẹni ko gbọdọ ba awọn oniroyin sọrọ, titi ti iṣẹ iwadii yoo fi pari.",0,yoruba ọ̀rọ̀ yi kún fún àwọn ìkòkò tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọba lo ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "Ìlú Maiduguri ló ń forí sọta làásìgbò Boko Haram fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọdún - bákan náà ló tún ń ja ìjà abẹ́nú pẹ̀lú àsìlò òògùn Nígbà tí Mustapha Kolo, ẹni ọdún mẹ́tàdínlógún mu òògùn pupa tó dùn wò lójú náà, ó dà bíi pé ó leè hú igi. Bíí ìgbà tí ara rẹ̀ kìí se tiẹ̀. Ó sì ń mú èrò burúkú jáde. ""Tí mo bá ti múú, mo máa ń gbàgbé gbogbo nkan ni."" Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Fídíò òògùn ikọ́ Codeine: Ó dùn lóòtọ́ àmọ́ ewu ni Ojú Kolo dúdú, tó sì pọ́n bíi ẹ̀yẹ iná, ohùn rẹ̀ ń lọ́ pọ̀, tí kò sì já gaaraga bó se ń sọ̀rọ̀. Ọ̀rẹ́ rẹ̀, Modu Mustapha ni kò mọ ohun tó ń se mọ́, tí orí rl sì ń mì dirọ̀-dirọ̀ ní ààrin èjìká rẹ̀ tó jk kìkì eegun. Ó fojú hàn gbangba pé irọ̀ ni wọ́n ń pa, tí olórí wọn, tí wọn wà lọ́dọ̀ rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi fijilante tó ń sọ́ ìlú Maiduguri, sì rọ̀ wọn láti sọ tòótọ́. ""Tẹ́lẹ̀-tẹ́lẹ̀, mo máa ń mu tó mẹ́ta tàbí mẹ́rin nígbà tí mo bẹ̀rẹ̀ sí ní muú. Sùgbọ́n ní báyìí, mo ti dínkù sí ẹyọ kan tabi ààbọ̀"", tí Kolo kò sì setán láti sọ̀rọ̀ síwájú. Mustapha Kolo ní òògùn oníhóró náà máa sèrànwọ́ tóun bá wà nínú igbó láti bá Boko Haram ja Ní ìlú tí kò fararọ yìí, ẹgbẹ̀lẹ́gbẹ̀ èèyàn ni òògùn olóró Tramadol ti di bárakú fún - àwọn ẹ̀sọ́ fijilante, àwọn tí ogun le nílé àti àwọn adúnkookò gan fún ra wọn. Òògùn aporó tí kò wọ́n rara yìí wà láti wo ara ríro níwọ̀n ba. Sùgbọ́n, gẹ́gẹ́ bó se máa ń rí pẹ̀lú àwọn òògùn olóró, èèyàn leè kúndùn rẹ̀, kó sì di bárakú sí onítọ̀ún lára - sùgbọ́n àríyàn-jiyàn sì ń wáyé lórí bí èèyàn se leè kúndùn rẹ̀ sí. Àjọ elétò ìlera lágbàáyé (WHO) ní Tramadol làwọn èèyàn lérò pé ó ""èèyàn leè má tètè kúndùn rẹ̀ táa fi wé Morphine"" Àmọ́ bí ọwọ́jà òògùn náà se ń jà rànìn-rànìn káàkiri ẹkùn ìwọ̀ òòrùn Afrika tako èrò yìí. Bí àwọn ọmọ Nàíjíríà se kúndùn òògùn lílò ti di ìràwọ̀ ọ̀sán, tó ń ba àgbà lẹ́rùn báyìí - àjọ ìsọ̀kan àgbáyé sì fẹ́ se ìwádìí lópin ọdún yìí Àwọn olórí àtàwọn ológun ni wọ́n se Tramadol fún, àmọ́ bí àwọn àdúnkookò-mọ́ni se wá kúndùn rẹ̀ láti máa gbẹ̀mí ẹni, wá di àpérò àwọn ọmọ eríwo báyìí, èyi tí wọn ló ń dákún bí ọwọ́jà wọn se ń le koko síi. Ọ̀kan lára àwọn agbébọn tẹ̀lẹ̀, tíí se ẹni ọdún mọ́kànlélógún, tó wà ní àgọ́ àwọn ológun ilẹ̀ Nàíjíríà, lẹ́yìn tó ti sá ní àgọ́ Boko Haram lósù kínní 2018, sàlàyé pé ọdún mẹ́rin ni òun fi gbé inú igbó níbi tí kò sí omi tó tó tàbí oúnjẹ - sùgbọ́n Tramadol wà. ""Tá a bá ń lọ se ìkọlù wa, wọn yóò fún wa ní òògùn náà láti lò, bí bẹ́ẹ̀ kọ́, tó o bá mu ú, wọ́n leè pa ọ́. Wọ́n sọ fún wa pé tí o bá ti mu òògùn náà, ẹ̀rù kò ní bà ọ́ ma, ó ní agbára àti okun síi. Òògùn áà pọ̀ ní àpsjù."" Àwọn olórí àtàwọn ológun ni wọ́n se Tramadol fún Gẹ́gẹ́ bí Ọ̀gbẹ́ni Àyúbà ti wí, ""kò sẹ́ni tó leè pa èèyàn lójú lásán, sùgbọ́n òògùn Tramadol wà níbẹ̀ láti tìẹ́ sisẹ́ ibi."" Àwọn obìnrin kan wà tí wọn ti sá kúrò ní ibùba Boko Haram, àmọ́ tí òògùn olóró ti di bárakú fún nítorí ń se làwọn àdúnkookò-mọ́ni náà máa ń lo òògùn fáwọn ọmọdebìnrin náà tí wọn bá ti ń sunkún."" Àjọ ìsọ̀kan àgbáyé ní, àwọn ikọ̀ ọ̀daràn lágbàáyé ló ń kó Tramadol wọ ilẹ̀ Afrika láti ẹkùn gúúsù ilẹ̀ Asia. tí àwọn agbófinró sì ń gbẹ́sẹ̀ lé ìwọ́n kílò tó tó ọ̀ọ̀dúnrún ní ọdọọdún. Àjọ ìsọ̀kan àgbáyé ní, àwọn ikọ̀ ọ̀daràn lágbàáyé ló ń kó Tramadol wọ ilẹ̀ Afrika láti ẹkùn gúúsù ilẹ̀ Asia Ní báyìí tí ìlòkulò Tramadol ń wáyé ní Nàíjíríà, ó nira púpọ̀ láti mọ ìdí tí wọ́n se gbé Tramadol sí abẹ́ àwọn òògùn olóró bíi oxycontin, morphineàtàwọn òògùn olóró míì bíi Cocaine ní orílẹ̀èdè Amẹ́ríkà.",0,yoruba "Oogun apakokoro lọwọ ti oloyinbo n pe ni ""Hand Sanitizer"" ti di ja pataki lori igba bayii koda o ti di nkan pataki to gbud wa lapo rẹ nibikibi too ba n lọ nitorii arun Coronavirus. Ṣugbọn ọna ati mọ awọn eyi to jẹ ayederu too ba ri i lori igba ṣe pataki lasiko yii nitori pe ileeṣẹ awọn apoogun orilẹede Naijria to n ṣe iwadii ati idagbasoke (NIPRD) ni ida mẹtalelọgọta oogun apakokoro to wa ni ilu Abuja nikan tii ṣe oluulu orilẹede yii ni kii ṣe ojulowo. Eyi waye gẹgẹ bi orilẹede Naijiria ṣi ṣe n ba arun coronavirus finra eyi to ti mu ẹgbẹrun marunlelọgbọn o din diẹ to si ti pa eniyan to din diẹ lẹgbẹrin titii ọjọ Ẹti ọjọ ikẹtadionlogun oṣu keje ọdun 2020. Ajọ eleto ilera lagbaye, WHO lo fi ontẹ jan lilo oogun apakokoro lati le maa pa awọn kokoro to ba wa lọwọ lasiko ti ko ba si ọṣẹ ati omi larọwọto. Ṣugbọn lilo oogun apakokoro nikan ko to lati dena arakan arun gẹgẹ bi awọn onim ṣe sọ ọ. Wọn gba awọn eeyan nimọran lati maa tẹle ilana eto ilera eyi to fi mọ lilo iboju-bomu nigboro, fifi ọṣẹ ati omi fọwọ ati jijinasiraẹni. Ggẹ bi iroyin ti ileeṣẹ to n ri si eto ilera lorilẹede Naijiria fi sita nipa awọn oogun apakokoro, wọn ni beeyan ba bọ sọja lati ra a, o ni lati la oju rẹ daadaa lati wo o boya oogun apakokoro naa ni awọn nkan wọnyii:",0,yoruba "Ní ààfin ọba ní ilẹ̀ Yorùbá, akéwì ma ń wà ní ibẹ̀, tí yóò ma fi ewì dá ọba lára yá. Tí ọba bá ti fẹ́ jáde sí inú ààfin, akéwì ma fi ewì ki ọba jáde, títí tó fi ma dé orí ìtẹ́. Akéwì náà á ma ké ewì lọ, títí ọba ma fi dá a dúró.",0,yoruba "fè joko, Nitori eyi, ara eni lo ni Nitori eyi, ara eni lo ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Ore General Hospital: Ìjọba Ondo yóò wá wọ̀rọ̀kọ̀ ṣàdá lórí bí mọ́súárì ilé ìwòsan Ore ko ṣe ráyè gba òkú mọ́ Ijọba ipinlẹ Ondo ti sọ pe, oun ṣetan lati wa ojutuu sí bi ile igbokusi, mọsuari ile iwosan ijoba to wa Ore ṣe kun fọfọ, debi pe ko raye gba oku mọ bayii. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Adele Kọmiṣọnna eto ilera ipinlẹ naa, Dokita Ajibayo Adeyeye, to ba BBC Yoruba sọrọ ṣalaye pe, lootọọ ni mọsuari ile iwosan naa ti kun debi pe ita ni wọn n tẹ oku si bayii, eleyi to le fa ajakalẹ arun lagbegbe naa. Ifa Worshippers: Àwọn ẹlẹ́sìn ìbílẹ̀ ń fẹ́ kíjọba pín èrè òṣèlú alágbádá yíká gbogbo ẹ̀sìn Dokita Adeyeye ni, oku awọn eeyan to ku ninu ijamba ọkọ lopopona mọrosẹ Ore si ilu Benin, lawọn ọlọpaa maa n ṣaaba gbe lọ si mọsuari ile iwosan naa. Adele Kọmiṣọnna eto ilera ipinlẹ Ondo ni, ọrọ naa ti ju agbara awọn oṣiṣẹ ile iwosan ọhun lọ nitori wọn o ti yanju ọrọ awọn alaisan ti wọn n tọju tan, ka to wa sọ nípa àwọn to ti ku. ""Ọga ile iwosan naa sọ fun mi pe, awọn ọlọpaa ko dẹkun gbigbe oku awọn eeyan wa lẹyin ti ile igbokusi ile iwosan ọhun ti kun,"" Dokita Adeyeye lo sọ bẹẹ. Akomolede ati Aṣa lori BBC:Wo ìrúfẹ́ ìgbeyàwó méje tó wà nílẹ̀ Yorùbá àti ojúṣe Alárinà Dokita Adeyeye ni oun lọ si ile iwosan naa lati ri bi nkan ṣe ri gan an níbẹ, o ni ijọba ko ba sọ mọsuari ile iwosan naa di nla amọ ko s'aye mọ níbẹ. Kọmiṣọnna eto ilera Ondo ni, ohun ti ijọba n gbero lati ṣe bayii ni ki wọn ko mọsuari kuro nile iwosan ọhun, lati lọ kọ ọ sí ibo miran. Dokita Adeyeye ni lai deena pẹnu, ijọba ipinlẹ Ondo n ṣiṣẹ lori ọrọ naa. Ọ̀pọ̀ òkú fọ́nkálẹ̀ nílé ìwòsàn ìjọba ní Ore, ìpayà àjàkálẹ̀ àrùn gbàlú kan Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe o se e se ki ajakalẹ arun bẹ silẹ lagbegbe Ore nipinlẹ Ondo nitori iwadii ti fihan pe ọgọọrọ oku lo sun sori ara wọn nile iwosan ijọba to wa nilu naa. Gẹgẹ bi iwe iroyin Punch ti salaye, se ni wọn gbe awọn oku silẹ kaakiri awọn ilk ile iwosan naa, ti ojo si n pa wọn mọ ibẹ. Awọn aworan to ba ni lẹru ati fidio to ba ni ninujẹ nipa ayika ibudo igbokusi to wa nile iwosan naa, fihan pe awsn oku ti kun de ẹnu ọna, ti wsn si fi paanu bo awọ́n miran mọlẹ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Koda, wọn tun lo biriki lati se aala laarin oku kan si ekeji, bẹẹ si ni ninu ibi kan to dabi yara, oku ọkunrin ati obinrin lọpọlọpọ lo wa nilẹ ilẹ. Iyalẹnu tun lo jẹ pe oku meji mii ti wọn fẹyin ti lara ogiri ni wọn ti gbẹ di egungun, to si jẹ pe ẹrọ amunawa kekere meji pere ni ibudo igbokusi naa ni. Awọn ara adugbo ibi ti ile iwosan ijọba naa wa ni ọrọ naa ti ka laya, to si ti ko ipaya ati irẹwẹsi ba. Nigba to n sọrọ lori isẹlẹ yii, Kọmisana feto ilera, Ajibayo Adeyeye ni ibi ti wọn kọ ile iwosan naa si lo fa isoro nitori oju titi lo wa. ""Ọpọ awọn eeyan to lugbadi ijamba ọkọ ni wọn maa n gbe wa sile iwosan naa, ti wsn yoo si gbagbe wọn sibẹ. Nigba mii, awọn ọlọpaa yoo kan gbe oku miran wa, ti wsn yoo si gbe wọn kalẹ lai boju wẹyin mọ."" Grandma Maruwa: Ó yẹ kí obìnrin sisẹ́ láì wojú ọkọ kó tó jẹun Adeyeye fikun pe pupọ ninu awọn oku naa lo ku lati ipasẹ ijamba ọkọ lai ri ẹni beere wọn, ti ẹjọ si tun n lọ lọwọ nipa iku awọn oku miran eyi ti ko jẹ ki wọn le e sin wọn. O wa pari ọrọ rẹ pe bawọn eeyan to ni ilẹ lagbegbe naa se maa n taku lati fi ilẹ wọn silẹ pe ki wọn sin awsn oku naa si, lo mu ko nira lati sin awsn oku naa papọ. Amọ o woye pe o seese ki wọn wa ibudo kan ti wọn yoo ti dana sun awọn oku naa, ti ko ba si ọna abayọ miran, lọna ati wa ojutu si isẹlẹ yii.",0,yoruba "Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu mama agba kan, Ọlayinka Ọnabanjọ, ti wọn n pe ni ‘Grandma Maruwa’, ẹni to jẹ akinkanju obinrin to n wa Maruwa nilu Ibadan. Lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, Grandma Maruwa ni, bo se n pẹ pupọ ki ijọba to san owo osu awọn olukọ, eyi to n mu ebi pa oun, lo ta oun ni idi kan lati dara pọ mọ ẹgbẹ awọn awakọ, ẹka ti Maruwa. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: O wa gba awọn obinrin nimọran lati mase maa woju ọkọ wọn, ki wọn to jẹun tori iwuri nla ni ti ọwọ meji ba n sisẹ. Bakan naa ni Grandma Maruwa tun rọ wọn lati wa isẹ se, ki wọn lee gbiyanju ipa tiwọn naa nidi eto ẹkọ awọn ọmọ wọn.",0,yoruba "Eyi kọja bẹẹ, gbogbo ara la fi n gbá bọọlu lasiko yii Ìdije laarin orilẹ-ede Russia to ń gbàlejò àti Saudi Arabia ni wọn kọkọ fi ṣide ife ẹyẹ agbaye World Cup 2018. Lẹyin èyí ni àwọn orilẹ-ede mẹfa miran jọ ná an tán bi owó pẹlu èsì wọnyii: Awọn orilẹ-ede to gbegba oroke ri atilẹyin awọn ẹlẹse ayo bii: Èyí ni díẹ̀ lára àwọn àwòràn àwọn ẹlẹ́sẹ̀ ayò náà lẹnu iṣẹ́ wọn lọkọọkan: Idunnu ṣubu layọ lẹyin ti Russia sọ bọọlu sáwọ̀n Saudi Arabia 'A kò róhun fáyọ̀ bi ko ba ṣe ọpẹ' Ìdí iṣẹ́ ẹni la ti ń mọ ni lọ́lẹ́, ọrọ eré bọọlu ti gba ìṣirò bayii. 'Bóò lọ, o yàá mi ni ìṣesí àwọn agbabọọlu to n kopa ninu ìdíje World Cup 2018 ni Russia' Ẹni à ń bá ná ọjà là ń wò, a kìí wo ariwo ọjà ràrà ló bá dé nńú ìdíje ife ẹyẹ àgbáyé 2018 Ronaldo ti Portugal, ẹlẹ́sẹ̀ ayò ilẹ̀ Portugal lo ti gbá àmì ayò tó pọ̀jù lọ (3) nidije Ìrìrì kọjá ẹgbẹ́ abewu lọrọ eré bọọlu di bayii Ayọ̀ ti kò lẹ́gbẹ́ ni ti èèyàn sọ bọọlu sáwọ̀n ẹlomii Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Gbolahan Kabiawu: Fífi ẹ̀jẹ̀ sílẹ̀ dára fún ẹ̀yà ara Ajanaku kọja mo ri nkan firi ni idje bóólu di bayii",0,yoruba "Awọn iroyin tuntun tun jade nipa iku oloogbe Fọlakẹ Arẹmu ti ọpọ mọ si Oriṣabunmi, eekan oṣere tiata ati sinima lorilẹede Naijiria to jade laye ni ọjs diẹ sẹyin. Ọjọ meji ni aisan to ṣe Oriṣabunmi fi ṣe, gẹgẹ bi aburo rẹ, iyaafin Toyin Akinoso ṣe ṣalaye fun ileeṣẹ iroyin abẹle kan. Ni kete ti aisan naa bẹrẹ lo si lọ si ileewosan nibi to dakẹ si. Iyaafin Akinoso to jẹ aburo oloogbe naa ni awọn jumọ ṣere lati ọjọ kejila oṣu kejila ọdun 2020 titi di ọjọ kini ọdun 2021. O ni iba lasan lo ṣe Oloogbe Oriṣabunmi to fi lọ si ileewosan nibi ti o ti jade laye. O niiku to ṣe gbogbo ẹbi ni kayefi ni iku Oriṣabunmi. ""Ohun ti inu mi kan dun si ni pe bi o ṣe lo ile aye rẹ."" O ni eeyan nla ni Ọlọrun gba lọwọ ẹbi naa ati pe Ọlọrun nikan lo lee di aye to fi silẹ. O ni ọrọ to sọ fun oun ni ọjọ kini ọdun 2021 ni pe ki awọn maa gba adura. O ni o tẹẹ mọ oun leti pe ki awọn maa dupẹ ni nitori pe wọn ko duro ibanujẹ lori ẹnikẹni ninu ẹbi naa laimọ pe yoo jade laye laipẹ.",0,yoruba @user esa fe ti ina bo ile Yoruba tipa tikuku. Ari ijamba ti awon egbe Ganiyu Adams se ni ilu eko lojo aje. Eledumare yio da yin lejo,0,yoruba RT @user: #IkiniFriday mo ki @user @user @user @user eku ise igbe ede ati asa ise ile wa laruge.,0,yoruba "ni Nitori eyi, ara eni lo je gbogbo ise ibile tèmi.",0,yoruba ní nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba ilé iṣẹ́ ní ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ tí a ṣe ní fún ọmọ nàìjá yó wà fún títà lóṣù kẹ́rin ọdún,0,yoruba "Wunmi Toriola, Aisha Lawal, Sotayo àtàwọn ọmọge Yollywood mìí Gẹgẹ bi awọn to ti di agba ọjẹ ṣe wa laarin wọn ti wọn ṣi dun un wo loju bẹẹ naa lawọn to ti n yọri bọ atawọn to ṣẹṣẹ n yọri naa ni ololufẹ wọn. Diẹ lara awọn oṣerebinrin tawọn eeyan n kan sara si bi adẹdaa ṣe da wọn ree. Mercy Aigbe Mercy Aigbe kii ṣe ọmọ Yoruba. A bi oṣere ọmọ Naijiria yii ni ọjọ kinni, oṣu kinni, ọdun 1978 lati ilu Benin, olu ilu ipinlẹ Edo. Oludari ere ni Mercy o si tun jẹ oniṣowo. O ti di ilumọọka oṣere Yoruba to si n sọ ijinlẹ ede Yoruba bi awọn to ni ede gan an. Ile iwe girama Maryland Comprehensive Secondary School, Ikeja ni ipinlẹ Eko lo lọ. Bakan naa lo kẹkọọ jade ni ile iwe giga akọṣẹmọṣẹ ti ilu Ibadan nibi to ti kẹkọọ gboye OND ninu imọ eto isuna ko to lọ si fasiti ilu Eko lati lọ kẹkọọ gboye ninu imọ Tiata. Lẹyin eyi lo dara pọ awọn oṣere tiata lẹkunrẹrẹ lọdun 2006. Oun naa ti ni ile ẹkọ nipa ere ṣiṣe to pe ni ""Mercy Aigbe Gentry School of Drama"". Mercy Aigbe bu èpè jó àwọn tó ní gómìnà kan ló ra ilé fún-un Liz Da Silva Elizabeth Tekovi Da Silva ni apeja orukọ Liz to jẹ ọmọ Naijiria ṣugbọn ti awọn obi rẹ ara orilẹ-ede Togo bi i ni Lagos Island, ipinlẹ Eko to si dagba ni agbegbe Obalende l'Eko. Lati igba ti Liz ti wa nile iwe girama lo ti nifẹ si kikopa ninu awọn ere ori itage to si ti n ba wọn kopa nigba naa. Bí ilumọọka agbabọọlu Drogba ṣe dáwọ ogun dúró ní Ivory Coast Àwọn olùgbé ìlúu Abidjan ló kò àrùn Coronavirus wọ Ọ̀ṣun-Gómìnà Oyètọ́lá Coronavirus in Nigeria: Ẹ wo àǹfààní tó wà nínú àrùn Coronavirus Coronavirus: Ṣé ọtí leè dènà tàbí pa àrùn Coronavirus bi? Ọdun 2004 nigba to bẹrẹ pẹlu gbajugbaja oṣere Iyabo Ojo. Ọpọlọpọ ere ibilẹ Yoruba lo ti kopa oun naa si ti ṣe agbejade ere tirẹ gangan. Hassan, Iyabo Ojo, Ronke Ojo, and Doris Simon, atawọn mii. Mama Rainbow: Toyin Adegbola àti Razak Olayiwola ní ìyá rere àti àwòkọ́ṣe gidi ní Wumi Toriola Oṣere Naijiria to ti n gbori soke ni Wumi Toriola, Ọmọ ipinlẹ Ogun ni. Imọ ẹkọ nipa ẹda ede (Linguistics) ni Wumi kọ jade lati fasiti ilu Ilorin bẹẹ si lo gboye Diploma ninu imọ ẹkọ Tiata. Oṣere ni, oniṣẹ ọwọ si ni pẹlu to ti gbajugbaja laarin awọn oṣere Yoruba to bẹrẹ si ni kopa ninu ere lọdun 2013. Wùnmí Toríọlá: Toyin Abraham kìí se ọ̀gá mi nínú tíátà O ti kopa ninu ọpọlọpọ ere to le ni aadọta oun naa si ti ṣe agbejade ere tirẹ gangan to to bii mẹta. Wumi Toriola gbeyawo lọdun 2018 pẹlu ọkọ rẹ to n gbe nilẹ okeere wọn si ti ni ọmọ ọkunrin ninu oṣu kẹwaa, ọdun 2019. Aisha Lawal Laarin awọn ọdọ oṣere Yoruba, Aisha Lawal ti di gbajugbaja pẹlu ara ọtọ to n gba fi itumọ si ipa ti wọn ba fun un lati ko ninu ere. Yatọ si pe o jẹ oṣere, iwadii fihan pe o tun jẹ alase ati sọrọsọrọ nibi ayẹyẹ. O kawe ni Adeen International School, Ogbomosho ati ile iwe girama ti awọn akẹkọbinrin, Federal Government College, Ogbomosho. Aisha kawe gboye ninu imọ ofin ni fasiti Lead City, o si tun kawe gboye onipele kini mii ninu imọ ẹkọ Public Administration. Aisha Lawal ti kopa ninu ọpọlọpọ ere agbelewo Yoruba ati ede Gẹẹsi. Bidemi Kosoko Ile to kun fun awọn oṣere ni Bidemi Kosoko ti ṣẹ wa. Oun funrarẹ naa ni ẹbun yii gẹgẹ bi o ti jẹ ọmọ agba ọjẹ oṣere, Ọmọọba Jide Kosoko. Bakan naa, ẹni to ku fun un ni iya, oloogbe Henrietta Kosoko naa jẹ oṣere. Bidemi tun ni ẹgbọn, Sola Kosoko, ti oun naa jẹ oṣere ati ẹgbọn ọkunrin, Tunji Kosoko. Ọmọ iya kan naa ni Bidemi ati Sola Kosoko, wọn padanu iya wọn lọdun 1993. Bidemi kawe gboye ninu imọ tiatia lati fasiti ilu Eko. O ti lọkọ Bidemi Kosọkọ di ìyá ìkókó lọdun 2019. Sola Kosoko: ọlá bàbá mi ni mò n jẹ́ nínú iṣẹ́ tíátà Biola Bayo Biola Adebayo naa kii ṣe aimọ fun oloko laarin awọn oṣere Yoruba. Oju rẹ bẹrẹ si ni di gbajugbaja lọdun 2006. Bo tilẹ jẹ pe lasiko kan oju rẹ ko fi bẹẹ maa jade lori awọn ere agbelewo, bẹẹ naa lo to akoko to gberasọ pada tori naa, Biola Adebayo o ṣee fọwọ rọ sẹyin lagbo awọn awọn oṣere. Eniola Ajao Ijọba ibilẹ Epe lEko ni wọn ti bi Eniola lọjọ kọkanlelogun, oṣu kinni. Ibeji ni Eniola jẹ toun ati ikeji rẹ si jẹ abigbẹyin awọn ọmọ mẹfa ti obi wọn bi. Ile iwe alakọbẹrẹ Saint Michael ni Epe ni Eniola ti bẹrẹ iwe kika. Lẹyin naa ni Eniola lọ si ile iwe girama tawọn ologun ni Epe kan naa. Fun imọ ẹkọ giga, Eniola kawe gboye ninu imọ iṣiro owo ni ile iwe akọṣẹmọṣẹ Yaba College of Technology ko to lọ si fasiti ilu Eko lati kọ imọ iṣiro owo. Ere akọkọ ti Eniola ti fojuhan ni Igba Aimo lọdun 2004 lati igba naa lo si ti di oju taye mọ daadaa ninu awọn sinima Yoruba. 'Mí ò ya wèrè, mí ò burú, ọ̀nà àtijẹ là ń wá' Sotayo Gaga Sotayo Sobowale lorukọ rẹ ṣugbọn ti apele rẹ n jẹ Sotayo Gaga. Ọmọ orilẹ-ede Naijiria ni ti wọn bi ni ọjọ kejidinlọgbọn, ọdun 1985. Iya rẹ jẹ ẹlẹsin musulumi nigba ti baba rẹ jẹ ẹlẹsin Kristẹni. Fasiti OIlabisi Onabanjo lo ti kawe gboye ninu imọ Public Administration to si tun gboye Diploma ninu imọ ofin lati fasiti ilu Eko. Inu awọn orin lo ti kọkọ bẹrẹ si ni fojuhan ko to dara pọ mọ sinima agbelewo lede Gẹẹsi, ko to wa re si ti Yoruba to si n ṣe mejeeji sira wọn. Sotayo ni ile iṣẹ nla kan ti wọn ti n ṣagbejade ere tabi orin nilu Eko.",0,yoruba ẹ̀ká ojú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba "Ẹ kú ojúmọ́ o, ẹ̀yin olóríire gbogbo. Ẹkú ìpalẹ̀mọ́ ọdún. Á mú're wá o #ekaaro",0,yoruba à ti pé káwakọ̀ ọkọ̀ ó baa kọ́ àṣàa à ń wa ọkọ̀ láì tẹ fèrè kí a máa wa ọkọ̀ pẹ̀lú ìwà ìrẹ̀lẹ̀,0,yoruba joko. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ àti ìbi tí wọn wà.,0,yoruba owo ṣẹlẹ ni Ibadan ti gbogbo eniyan sọ o ṣe pataki. (2015),0,yoruba sí ìbàdandun láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba "Sugbọn wọn ko fun un ni anfaani nitori wọn foju ọmọkekere wo o ati pe ko si nnkan to ni laari kan ti o le se. Ko pẹ si asiko naa ni agbaọjẹ abanigbe orin jade yii ba a nibi kan ni agbegbe Ẹpẹ nibi ti o ti n fi orin da awọn eniyan laraya ti ero si pe biba sibẹ. Lọgan lo gbe e lọ lati gba orin rẹ silẹ, lati igba yii ni wọn ti bẹrẹ si ni tọ sọna gẹgẹ bi ọkan ninu awọn gbajugbaja olorin to lamilaaka ni Naijiria. Èmi àti Kolington kò fẹ́ra padà o, ọba Wákà kò fẹ́ ọba Fuji mọ́ - Salawa Abeni Inú káàdì ìránti tí mo rí he ní mó tí rí fọ́tò ìhòhò Salawa, mó kàn fẹ́ gbà owó díẹ̀ ni- Afurasí Ó pé ọdún mẹ́wàá tí Barrister kú; wo ǹkan tó yẹ láti mọ̀ nípa rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi olórin, tẹ̀wé-tẹ̀wé, akọ̀wé àti sọ́jà Èmi kò gbé pọ̀ pẹ̀lú Kollington Ayinla àmọ́ ọjà t'ọ́mọ ti wọ̀ lọ̀rọ̀ àwa méjééjì - Salawa Abẹni Lasiko kan sẹyin ni Waka Queen ṣe aisan, ọpọ lo si ti ro pe aisan ọhun ni yoo mu opin ba gbajugbaja naa, ṣugbọn, o ru u la. Pẹlu iranlọwọ awọn ọmọ Naijiria ati ijọba ipinlẹ Eko, Tinubu, Fashola ati Ambode ni Salawa ni Ọlọrun lo fun oun, o bọ lọwọ aisan rọparọsẹ to kọlu u to si ti n ṣe daada lati igba naa. Lẹyin eyi lo tun ba BBC Yoruba sọrọ lori igbesi aye rẹ ninu iṣẹ orin. Awọn nnkan mẹwaa ti o yẹ ki o mọ nipa Salawa Abeni ree, akikanju obinrin to nigbagbọ ninu ara rẹ pe oun le ṣe daada pẹlu atilẹyin awọn obi rẹ. 1. Salawa Abeni bẹrẹ orin kikọ lati ọmọ ọdun mẹsan sugbọn o sọ di iṣẹ aṣela lati wa ounjẹ oojọ ni igba to pe ọmọ ọdun mẹwaa. 2. O gbe awo orin akọkọ jade ni ọdun 1976 to pe akọle rẹ ni General Muritala Ramat Muhammed labẹ asia Leader Records. Eré orí ìtàgé kọ́ ni pé Baba Ijesha ń tẹ ọmọ lára, ẹ yé gbè sẹ́yìn mi lọ́nà àìtọ́ - Yomi Fabiyi Ṣé lóòtọ́ ni Fr Ejike Mbaka ti di àwátì? Ẹ wo ǹkan tí a mọ̀ nípa rẹ̀ 'Iṣẹ wá burẹkẹ síi tórí Covid-19, owó ńlá ló wà nínú dídáná sun òkú, ìsìnkú Zoom, Live streaming' 3. Oun ni obinrin akọkọ to gbe orin jade to si ta kasẹẹti to le ni miliọnu kan ni Naijiria, orin akọkọ to se jade ni pẹlu. 4. Nigba ti o wa ni ọdun mẹrindilogun, Salawa Abeni da ẹgbẹ orin kalẹ to pe ni The Waka Modernisers lọdun 1977. 5. Leader Records lo wa lati ọdun 1976 si ọdun 1985, o si ṣe agbekalẹ orin mẹrinla laarin asiko naa. 6. O figba kan fẹ gbajugbaja olorin, Alhaji Killington Ayinla ti gbogbo eniyan mọ si Kollington ti wọn si bi awọn ọmọ lara wọn ni Sheriff ati Okikiola. Bakan naa lo padanu ọmọ kan ri, eyi to bi fun Lati Adepoju. 7. O darapọ mọ rẹkọọdu Kollington lasiko ti wọn n fẹ ara wọn laarin ọdun 1986 titi di 1994 nigba ti wọn tuka. 8. Labẹ Kollinton Records, awo orin mẹwaa lo gbe jade. 9. Ọdun 1992 ni Alaafin Oyo, Oba Lamidi Adeyemi fun ni oye Waka Queen orin. 10. Ọkan ninu ọmọ ti Salawa bi fun Kollington Ayinla, Sheriff tọpasẹ awọn obi rẹ bi oun naa ṣe n kọ orin taka sufe pẹlu orukọ Big Sheriff. Oun ati Waka Queen ṣe atunkọ orin rẹ Gentle Lady ni mi.",0,yoruba ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o nuni ti o ní wúlò.,0,yoruba ti Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "àbá èwe. Nitori eyi, ara eni lo ni ìgbà mi owó àkokò, Ọba ri Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba fi. Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.,0,yoruba Àmọ́ wọn kò rí ìwàa wọn gẹ́gẹ́ bíi ewu fún ààbò àti àlàáfíà orílẹ̀ - èdè ; wọn kò di ẹni à ń fi ọwọ́ọ ṣìgún òfin mú tàbí mú kí a pa ayélujára nítorí ìwàa wọn .,0,yoruba Ta lẹni tó kọ ìwé Aláwíyé? A) J. F Ọdúnjọ B) D. O Fágúnwà D). Adébáyọ̀ Fálétí #ibeere #Yoruba,0,yoruba ta ló rí gẹ̀lẹ̀dẹ́ àti nǹkan mìíìn tó jẹ́ ti,0,yoruba dara. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Alàji lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba ọkunrin a yi da ti o nuni ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba "RT @user: Ẹni tó ńbẹ Ọlọ́run kì í bẹ èyàn. / Whoever pleads (his case) with God, won't need to plead with man. [God is dependabl…",0,yoruba "Ẹ̀ṣọ́ tó pa Ọ̀gágun Ethiopia tí a sọ pé ó kú, kò kú mọ́! -Ọlọ́pàá Ikede yi lo waye lati ẹnu ileeṣẹ ọlọpaa apapọ lorile-ede Ethiopia ti o kọkọ sọ pe ẹṣọ to ṣekupa olori ọmọ ọgun ilẹ naa Ọgagun, Seare Mekonnen, ti yinbọn pa ara rẹ. Ni bayi ohun ti wọn n sọ ni pe ẹṣọ naa ko ku mọ ati pe o n gba itọju lọwọ nile iwosan ni. Ile iṣẹ olootu ijọba ilẹ naa sọ pe ẹsọ naa lo ṣeku pa ọgagun naa pẹlu ọga ọmọ ogun mii, ọgagun Gezai Abera ninu igbiyanju ati fitẹgbajọba. Eyi ni igba ẹlẹẹkeji ti iroyin yoo ma yipada nipa ohun to ṣẹlẹ si ẹṣọ yi. Mo máa n forin mi kìlọ̀ ìwà ìbàjẹ́ láwùjọ ni -Hameen Ni ọjọ Ẹti, ohun ti ileeṣẹ ọlọpaa kọkọ kede ni pe ọwọ ti tẹ ẹsọ naa, lẹyin igba naa ni wọn ni o yinbọn pa ara rẹ lẹyin to ṣeku pa awọn ọgagun mejeeji. Ko ti si aridaju boya ẹsọ naa n gba itọju fun ọgbẹ ti o fi ọwọ ara rẹ da tabi eleyi ti wọn da si lara. Tomomewo Favour: olóṣèlú kìí ṣe ọ̀daràn tàbí alágbèrè",0,yoruba "O lewu lati ma lo ile iwosan awọn nọọsi abẹ ile Ileeṣẹ ijọba to n ṣamojuto awọn ile iwosan nipinlẹ Eko, HEFAMAA ti gbe agadagodo sẹnu ọna ile iwosan ogun nipinlẹ naa, lataari pe wọn ko tẹle ilana ofin. Ẹni to gbẹnusọ fun iajọ HEFAMAA, Ada Omehu sọ fun BBC pe, awọn ohun to yẹ ko wa ni awọn ile iwosan to gba ontẹ ijọba ko si ni awọn ileewosan naa, ni HEFAMAA ṣe tii pa. Ada mẹnuba awọn ohun to yẹ ki awọn eeyan maa kiyesi ki wọn to gba itọju ni ile iwosan eyikeyi ti wọn ba lọ. Ada darukọ awọn nnkan bii oṣiṣẹ to dantọ, irinṣẹ to ba igba mu, agbegbe ti irufẹ ile iwosan bẹẹ wa, ati bẹẹ bẹẹ lọ ni amuyẹ ile iwosan to dantọ. O tẹnumọ ọ pe, ki awọn to ba n ṣaarẹ dẹkun lilọ si ile iwosan awọn nọọsi abẹ ile, nitori o lewu. Nigba to n sọrọ lori awọn amuyẹ ojulowo ile iwosan, Agbẹnusọ ajọ HEFAMAA ni ""irufẹ ileewosan bẹẹ gbọdọ ni awọn oṣisẹ to kawe gboye, kiiṣe awọn nọọsi abẹ ile."" Ada ni: ""Ile iwosan bẹẹ tun gbọdọ ni, ile oogun, yara ti wọn ti n ṣe ayẹwo ẹjẹ ati ẹya ara, pẹlu awọn irinṣẹ igablode."" Bẹẹ lo tun ṣalaye pe ile iwosan to ba wa ni agbegbe ibi idalẹsi kii ṣe ojulowo ile iwosan rara nitori ẹgbin ko faaye gba ilera pipe. Bakan naa lo sọrọ lori ileewosan ogun ti wọn ti pa kaakiri ipinlẹ Eko pe HEFAMAA gbe igbesẹ yii lati daabo bo awọn olugbe ipinlẹ Eko ni. Brazil Yoruba: A n gbé àwọn ère Yorùbá káàkiri- Ọọni ti Ilé Ifẹ",0,yoruba yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ àti ìbi tí wọn wà.,0,yoruba Ọ̀jọ̀gbọ́n Wọlé Ṣóyínká pé ọgọ́rin ọdún lóríi eèpẹ̀. Àṣọdúnmọ́dún ní í ṣ'awo àṣọdúnmọ́dún.,0,yoruba Unai Emery: Àwọn olólùfẹ́ Arsenal ní Emery gbọdọ̀ fipò rẹ̀ sílẹ̀ dandan,0,yoruba "Ìyá fi. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Nitori eyi, ara eni lo ni iwa rere.",0,yoruba Ogún - 20 Ògùn - Drug Ògùn - State Ògùn - Charm Òógùn - Sweat Ògún - Iron Ó gúun - Stab Ogun - War Ogún - Property Ó gùún - Climb O gun - Long #Yoruba🇳🇬 https://t.co/7ivTjgX5Yb,0,yoruba Church of Satan: Báwo ni ìjọ́sìn ṣe n rí nínú ìjọ Sátánì?,0,yoruba "RT @user: Ekaro gbogbo tweeps mi, lo ni emi ndarapo mo awon omo odua lati tweet ni èdè wa. Mo toro gafara lowo awon ti o gbo Yor…",0,yoruba "ire àti ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìṣẹ́ ọ̀pọ́lọ̀.",0,yoruba àṣe sílẹ̀ ni àbọ̀ wá bá,0,yoruba Sadio Mane: Wọ́n ti fi orúkọ̀ agbábọ́ọ̀lù Liverpool sọ pápá ìṣeré kan ní Senegal,0,yoruba "Gẹgẹ bi akọsilẹ ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC, eeyan to din ọgọrin ni ẹgbẹrun mẹrun(3,820) lo ko arun coronavirus lapapọ ni Naijiria lọsẹ to kọja. Koda Gomina Babajide Sanwo-Olu ipinlẹ Eko naa wa lara awọn eeyan ọhun. Ajọ NCDC sọ pe igba akọkọ ree tawọn to larun naa yoo pọ to bayii ni nkan bi oṣu mẹrin sẹyin. Awọn oṣiṣẹ eleto ilera si ti sọ pe ami leyi jẹ pe ajakalẹ arun covid-19 ẹlẹẹkeji n kan ilẹkun gbọngbọn papaa nipinlẹ Eko. Ṣugbọn akiyesi wa ni pe awọn ọkọ akero to fi mọ ọkọ akero ijọba BRT ko tẹle ilana itakete sira ẹni ti ajọ NCDC la kalẹ mọ. Niṣe ni gbogbo ọkọ naa n kun fọfọ lai si aga ijoko kan to ṣofo. BBC Yoruba kan si ọga agba ileeṣẹ ọkọ akero BRT ipinlẹ Eko, Ọgbẹni Idowu Oguntona lori ọrọ yii. Ọgbẹni Oguntona gba pe lootọọ ni awọn ko tẹle ilana itakete sira ẹni mọ ninu awọn ọkọ ero BRT nitori ijọba ipinlẹ Eko ko tii paṣẹ pe ki awọn maa ṣe bẹẹ ni. Ọga ọkọ BRT ni awọn si n ri wi pe awọn ero wọ ibomu wọn, lo sanitisa sọwọ, bakan naa lawọn n yẹ ara wọn wo bo ya o gbona tabi ko gbona lati le mọ bo ya wọn ni covid-19. Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmalẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá O fikun ọrọ rẹ pe awọn ko gba kawọn ero maa duro ninu awọn ọkọ naa mọ, wọn kan n joko lasan an ni. Ọgbẹni ṣalaye pe ijọba Eko naa ti n wo ṣaakun ọwọja covid-19 lẹẹkeji lati mọ iru ilana ti wọn tun fẹ gbe kalẹ. Amọ, ọga agba ọkọ ero BRT ipinlẹ Eko ko ṣai ṣalaye pe ijọba ni lati roo daadaa ki wọn to gbe ilana mii kalẹ nitori akoba ti coronavirus ti ṣe fun ọrọ aje tẹlẹ. Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni wọ́n ti já àbálé Esra lábẹ́ àwáwí àyẹ̀wò wúndíá",0,yoruba ènìyàn a yi lo ti o nuni ti o nuni ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba "kún jú, àwọn ènìyàn ni ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa òkè: ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Lẹyin ti idibo ba ti waye tawọn oloṣelu to n du ipo gbogbo, ninu eyi ti awọn ipo ile aṣofin apapọ pẹlu wa ni wọn maa n dawati. Opọ gba pe ti polongo ibo wọn pẹlu oniruuru agbọ-pọnula ileri fun araalu ba ti pari, ọpọ igba ni awọn oloṣelu kii boju wo ẹyin mọ titi di igba ti ọdun mẹrin miran ba ti pe ti wọn tun nilo ibo araalu. Nitori idi eyi kii ṣe kayeefi pe lọpọ igba ati kaakiri ipinlẹ lorilẹ-ede Naijiria ni awọn araalu kii mọ ibi ti wọn lee wa awọn aṣoju wọn si. Bi o tilẹ jẹ wi pe ofin laa kalẹ pe awọn aṣofin yoo ni ileeṣẹ agbegbe lawọn ẹkun idibo wọn sibẹ ọpọ ni ko mọ ibi ti awọn ileeṣẹ wọnyii wa. Pabanbari rẹ tilẹ ni pe ọpọ awọn aṣofin ni ko tilẹ ni awọn ileeṣẹ wọnyii. Ki gan an ni pataki ileeṣẹ agbegbe (constituency office) fun aṣofin? Pataki ileeṣẹ agbegbe ni lati maa gbọ aroye ati ẹdun ọkan awọn eeyan agbegbe ti irufẹ aṣofin bẹẹ n ṣoju fun. Ọfiisi to yẹ ko ṣi silẹ gbaragada fun tẹrutọmọ ni. Eyi tumọ si pe kii ṣe awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu Sẹnetọ tabi aṣoju-ṣofin naa nikan lo lẹtọ lati maa wa sibẹ pẹlu ẹdun wọn. World Aids Day: Wo bí kòkòrò ààrùn HIV se bẹ̀rẹ̀ lágbàyé! Koda lati ibẹ lo yẹ ki awọn ara ilu ti maa mọ ipele to kan ninu iṣẹ akanṣe ti aṣoju wọn n gbero atiṣe fun ilu rẹ Bakan naa lo yẹ ki wọn mọ bo ṣe n na owo ilu to n gba ni Abuja fun idagbasoke agbegbe ọhun ti wọn ba ti wọ inu ọọfiisi yii. FUTA: Àwọn mẹ́jọ ló ṣíná ìyà fún Bolu ní FUTA",0,yoruba "Gomina ipinlẹ Ekiti, to tun jẹ ẹni to fẹẹ dije fun ipo aarẹ labẹ ẹgbẹ́ oselu All Progressives Congress, APC, Kayode Fayemi, ti sọ pe oun yoo mọ lé awọn ipilẹ isẹ ti Aarẹ Buhari fi lelẹ. Fayemi sọ ọrọ yii lasiko to lọ si ipinlẹ Borno ati Yobe, lati beere fun atilẹyin awọn asoju ẹgbẹ́ APC, saaju idibo abẹnu. Ninu ọrọ rẹ, o ni ""ori aṣeyọri Aarẹ Muhammadu Buhari, la o mọ lé, a o si tete mojuto àwọn ibi to kù diẹ kaato si. Fayemi sọ pe eto aabo ni yoo jẹ koko ninu iṣejọba oun, gẹgẹ bi ẹni to jẹ onimọ nipa eto aabo. "" Mo ni iwe ẹri imọ ijinlẹ ọmọwe ninu ẹ̀kọ́ nipa ogun jija, mo si sisẹ gẹgẹ bi akọṣẹmọṣẹ ninu iṣejọba Aarẹ Obasanjo."" Bakan naa lo sọ pe ipa kekere kọ ni oun ko lati da alaafia pada lasiko ogun to waye ni Sierra Leone, Liberia, Rwanda, ati Sri Lanka. O ni"" a ti ni ilana ti ao lo lati mu alaafia wa fun àwọn eeyan wa, ka le ṣe iṣẹ́ agbẹ pẹlu ifọkanbalẹ, lọ sile ẹ̀kọ́ ni ifọkanbalẹ, ka si tun ma a gbe ninu alaafia."" Fayemi sọ pe ko si nkan to burú ki òun ṣe awọn nkan ti oun ṣe nilẹ okeere, fun orile-ede to fun oun ni ohun gbogbo. Nigba to n fun Fayemi ni esi, alaga ẹgbẹ́ APC nipinlẹ Borno, Ali Bukar Dalori, sọ pe Fayemi ni awọn yan laayo nipinlẹ naa. Nitori àwọn amuyẹ rẹ, ati nitori oore to ṣe fun awọn alaga ẹgbẹ́ naa ni gbogbo ipinlẹ labẹ isakoso oun. Bukar Dalori sọ pe adari to nifẹ awọn eeyan rẹ lo le ṣe bẹẹ. Bákan naa ni ọrọ ri nipinlẹ Yobe. Igbakeji gomina to soju gomina Mai Mala Buni, sọ pe ti Fayemi ni àwọn n ṣe. Fayemi jẹjẹ fun awọn aṣojú Yobe ti yoo dibo abẹnu pe ọna abayọ kiakia ni oun yoo wa si igbesunmọmi ati awọn rògbòdìyàn mii to n waye ni Naijiria. Ọjọ kẹrin, oṣu Karun-un, ọdun 2022, ni Gomina Kayode Fayemi kede ni gbangba pe oun naa yoo dupo aarẹ lati inu ẹgbẹ́ oselu APC lọdun 2023. Saa kejì lo n lo lọwọ gẹgẹ bi gomina ipinlẹ Ekiti.",0,yoruba Ìṣẹ̀dá ọ̀rọ̀ yìí fa àwọn onírúurú ìbéèrè àti èrò — àwọn akẹ́kọ̀ọ́ kan jiyàn wí pé a lè pe ẹ̀rọ - ayàwòrán náà ní ẹ̀rọ - amóhùnmáwòrán nítorí iṣẹ́ tí wọ́n ń ṣe .,0,yoruba "Iwadi naa ni ajọ FIFA se pelu ifọwọsọwọpọ awọn ẹka miran ninu ajọ bọọlu alafẹsẹgba. Collin Udoh fi kún pé ó fi dá òun lójú pé oun yóò jà fiktafita lati wẹ orúkọ oun mọ. O ní Siasia tún fi kún fún oun pé kò tilẹ̀ sí ẹni tó pé òun láti fi ọ̀rọ̀ wá oun lẹ́nu wò lóri ǹkan to ṣẹlẹ̀ yálà láti sọ tẹ́nu oun tàbí láti ja fún ẹtọ oun, ati pé ìgbà àkọ́kọ́ rèé tí òun náà ń gbọ́ ǹkan tó ṣẹlẹ̀ Kíní àwọn olúlúfẹ́ bọ́ọ̀lù àti àwọn Nàìjírí[[a ń sọ lóri ìgbésẹ̀ FIFA si Samson Siasia Àjọ FIFA fòfinde Samson Siasia titi lailai Ajo to n se amojuto ilana ere bọọlu afẹsẹgba lagbaye ti fi ọrọ lede wipe Samson Siasia to jẹ́ akoọ́nimọ̀ọ́gbá Super Eagles tẹ́lẹ̀rí, ti jẹbi ẹsun wipe oun lee gba riba bí ààye rẹ̀ bá yọ, pàápàá jùlọ láti yí èsì ìfẹsẹwọnsẹ bọọlu pàda. Ajo to ń se amojuto iwa ibajẹ naa ti bẹẹrẹ iwadi lori ọro ọgbeni Siasia láti ọjọ kankanla osu keji ọdun yi. Eyi to waye leyin iwadi ti ajọ naa se lori bii Ọgbeni Wilson Raj se gbiyanju lati yi esi idije kan pada lati fi ta tẹtẹ. Iwadi naa ni ajọ FIFA se pelu ifọwọsọwọpọ awọn ẹka miran ninu ajọ bọọlu alafẹsẹgba. Ninu ipinu wọn, ajọ ti ń se amojuto ilana isẹ ere bọọlu afẹsẹgba naa wipe ọgbeni Siasia jẹbi lodi si ilana ti FIFA gbekale. Wọn si pasẹ fun lati san owo itanran eyi ti iye rẹ lé diẹ̀ ni miliọnu mejidinlogun naira.",0,yoruba yì í tún ṣe àwọn iṣẹ́ tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìwà: ti o ní wúlò.,0,yoruba "metacity %s Àṣẹ lórí-àrà (C) 2001-2002 Havoc Pennington, Red Hat, Inc., àti àwọn mìíràn Ọ̀fẹ́ ni ẹ̀yà-ara kọ̀ǹpútà àìfojúrí yìí; wo orísun fún àwọn ìwọfún ìṣẹ̀dà. Kò sí wáráǹtì; kó dà kò sí fún ITAJA tàbí ÌWÚLÒ FÚN ÌLÒ PÀTÀKÌ KAN.",0,yoruba "Ní ọdún - un 1950 , RDS gbé aṣọ tuntun wọ̀ — ó di Iléeṣẹ́ Ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ Orílẹ̀ - èdèe Nàìjíríà ( NBS ) — nígbà tí ó ṣe , ó di Iléeṣẹ́ Alájọṣepọ̀ Ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ Orílẹ̀ - èdèe Nàìjíríà ( NBC ) , pẹ̀lú ìkànnì ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ ní àwọn ẹ̀ka tí Nàìjíríà pín sí .",0,yoruba Yọkúrò Nínú Pánẹ́ẹ̀lì,0,yoruba "Akẹkọ naa, Success Adebor, to n lọ sile iwe alakọbẹrẹ Okotie-Ebor kinni nijọba ibilẹ Sapele, ni fidio rẹ lu awọn oju opo itakun agbaye pa, lasiko to n fapa janu pe, wọn le oun kuro nile ẹkọ tori pe oun ko ri owo ile iwe san. Success ninu fidio naa ni, o ba oun lara mu ki wọn fi ẹgba na oun tori oun ko ri owo ile iwe san, dipo ki wọn le oun lọ sile. Success ni wọn yoo na oun titi, nigba to ba rẹ ẹgba, ni wn yoo dawọ duro. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Fidio naa ti wa pe akiyesi ijọba ipinlẹ Delta si awọn isẹlẹ to n waye nile ẹkọ rẹ. Lọwọlọwọ bayii, ijọba ti pasẹ fun ọga ileẹkọ alakọbẹrẹ naa, arabinrin Vero Igbigwe lati lọ rọọkun nile na, nitori bo se le akẹkọbinrin naa nile iwe rẹ. Kloe: Èmi kìí mu òògùn olóró, àmọ́ mo fẹ́ràn láti máa wà lẹ́bà omi Kọmisana feto ẹkọ nipinlẹ Delta, Amofin Chiedu Ebie, lasiko to n bawọn akọroyin sọrọ ni, ọga ile iwe naa ko lee se alaye ohun ti owo to n beere lọwọ Success wa fun, tori ọfẹ ni ẹkọ alakọbẹrẹ nipinlẹ naa. Wayi o, ọ̀pọ awọn lookọ lookọ lawujọ lo ti n rọ ojo owo ati dukia fun success, to ti kekere jẹnu ṣamuṣamu ninu fidio ọhun, to si ti pada sile iwe.",0,yoruba olóògbé Richard Akínjídé jẹ́ ẹni ọdún Méjìdínláàdórùń kí ó tó jáde láyé .,0,yoruba "Ní ní àìlẹ̀, Olùwo ri Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Gomina Abiọdun lo sọ ọrọ yii ninu atẹjade kan ti agbẹnusọ fun ijọba, Kunle Somorin, buwọlu nilu Abẹokuta tó jẹ olu ilu ipinlẹ Ogun. O sọ ninu atẹjade naa pe ""Ipinlẹ yii ko fun alaṣẹ ileewe girama ati ileewe ikọṣẹ ọwọ kankan laṣẹ lati gba owo ileewe lọwọ ẹnikẹni, gẹgẹ bi ahesọ ti awọn kan n sọ kiri."" Dapo Abiọdun tun rọ awọn eeyan ipinlẹ Ogun pe, ki wọn maṣe kọ ibi ara si awọn ahesọ ti awọn kan n sọ kiri. O ni oun naa ti ka iroyin ofege kan to ni pe awọn ọmọ ileewe ni lati san owo ileewe nigba ti wón ba bẹrẹ saa tuntun losẹ to n bọ. Lẹyin naa lo wa fi kun un pe, ki awọn eeyan ipinlẹ Ogun ni igbagbọ ninu iṣejọba oun ki oun lee dari ọkọ ipinlẹ na si ebute ayo. Gomina na sọrọ yii leyin atẹjade kan ti ileeṣẹ to n mojuto eto ẹkọ nipinle ọhun fi kede pe, ki awọn ọmọ ileewe mura lati san ẹgbẹrun mẹrin din lọọdunrun naira fun saa kan.",0,yoruba "ìgbà mi owó àkokò, Olùwo ri Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba ti Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí.,0,yoruba onà. ti Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ài: ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba Inter-family marriage: Wo oríṣìí àrùn márùn ún tí ìgbéyàwó láàrin ìbátan máa ń fà,0,yoruba "Ọrọ yi ko ṣẹyin bi ẹgbẹ alatako ni Naijiria ọhun ti ṣe ni ẹgbẹ APC n dunkoko mọ awọn adajọ ile ẹjọ to gajulọla lati gbe idajọ to tẹwọn lọrun jade ni gbogbo igba. Akọwe ipolongo ẹgbẹ PDP Kola Ologbọndiyan lo fi ọrọ yi sita ninu atẹjade kan loju opo ẹgbẹ naa ni Twitter Ologbọndiyan ni ifarajin awọn fun idagbasoke oṣelu awarawa ni Naijiria lo mu ki awọn fi tọkantọkan gba idajọ idibo aarẹ ati tawọn ipinlẹ bi Osun,Kano ,Katsina,ati Kaduna lai fa wahala. O ni o jẹ iyalẹnu fawọn pe ẹgbẹ APC n sare lati lọ dunkoko mọ awọn adajọ ile ẹjọ giga lẹyin ti wọn gbe idajọ kalẹ lori idibo Bayelsa. ''Lẹyin ta joko jiroro, a ṣetan lati pe fun ayẹwo idajọ to gbe aarẹ Buhari wọlẹ toun ti pe ẹri wa pe o lo iwe ẹri ayederu. '' O ni bẹẹ naa ni ọrọ kan idibo ipinlẹ Katsina ti ẹri aridaju wa pe wọn lo iwe ayederu'' Supreme Court : Oyetola fẹ̀yìn Adeleke janlẹ̀ nílé ẹjọ́ tó ga jù lọ! Yatọ si idibo ti Aarẹ Buhari, PDP sọ pe awọn yoo kesi ile ẹjọ to gajulọ lati ṣe ayẹwo idajọ ipinlẹ Kano, Kaduna ati Katsina ti ẹri ti wa pe wọn ṣe jagidijagan lasiko idibo. Ipinlẹ Osun naa ko gbẹyin ninu awọn ipinlẹ ti wọn na ika aleebu si idibo to gbe Gomina wọle.",0,yoruba ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o nuni ti o jare.,0,yoruba "Ko si ẹni ti ko ni lu aluyọ lọla Eledua ni 2023 yii. Bi ọdun 2023 ṣe ti wọle de wẹrẹ yii, BBC Yoruba kan si Imam agba ninu ijọ Mosalasi Shafaudeen In Islam lati sadura ọdun fun gbogbo ololufẹ BBC Yoruba pẹlu ilana musulumi. Imam Sabiat Olagoke ni pe ayọ lo ku lọdun 2023. Ati pe Allahurabi yoo fun ijọba Naijiria lọgbọn ati agbara lati ṣe ẹtọ to yẹ fun awọn oṣiṣẹ.",0,yoruba "Mo fe gbajumo oro eto aabo lasiko yii Bẹẹ ba gbagbe, Aarẹ Buhari bẹrẹ saa keji iṣejọba rẹ ni ọjọ Kọkandinlọgbọn, oṣu Karun un, ọdun 2019, amọ ti ko ba awọn ọmọ Naijiria sọrọ lẹyin ti wọn bura fun un tan. Kókó ọ̀rọ̀ tí Buhari sọ ní àyájọ́ June 12 Gbagede Eagle Square nibi ti Naijiria ti n sami ayẹyẹ iṣejọba Awa ara wa ni Abuja, ni aarẹ Buhari ti wa ba awọn ọmọ Naijira sọrọ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ninu ọrọ rẹ fun ayajọ June 12, Buhari ṣeleri lati tubọ ri si eto aabo fun ẹ̀mí àti dukia. Aarẹ Buhari ni, oun gba pe ajọṣepọ wa laarin ìṣẹ́, eto ọrọ ajé ti ko daa pẹlu iwa jẹgudujẹra, lai yọ eto aabo ti ko fini lọkan balẹ silẹ. Aarẹ Buhari tun ni, ko si nkan to le di Naijiria lọwọ idagbasoke gẹgẹ bii ti China, India ati Indonesia. Kókó inu ọrọ Aarẹ Buhari: Aarẹ Buhari bẹrẹ nipa ṣiṣe alaye kikun lori pataki Naijiria ninu idagbasoke iṣejọba alagbada nilẹ Adulawọ. O mẹnuba awọn aṣeyọri ijọba rẹ ni saa to kọja (2015 si 2019). Aarẹ Buhari kede fifi orukọ MKO Abiola pe papa iṣere Abuja Aarẹ Buhari ni oun ti jagun Boko Haram de ibi to lapẹrẹ lati 2015. O ni nitootọ iṣẹ yii pọ lati gbogun ti awọn ajinigbe ati agbesunmọmi, ṣugbọn eyi ti di ankoo fawẹẹli gbogbo agbaye. Awọn eniyan ilẹ okeere wa ba Buhari yọ ayọ ayajọ iṣejọba alagbada O ni ijọba oun ti mojuto ọrọ atunṣe eto ẹkọ ati idagbasoke eto ọrọ aje Naijiria, yatọ si titun awọn opopona ṣe. Aṣepari awọn iṣẹ akanṣe ti ijọba rẹ ti bẹrẹ tẹlẹ. Ileri ti Buhari fẹ gbajumọ ni saa keji iṣejọba rẹ: Nitootọ Aarẹ Buhari ko soju abẹ niko ni pato lori ileri rẹ, ṣugbọn o ṣapejuwe awọn koko ti ijọba oun yoo gbajumọ lasiko yii bii: Buhari gbe ipinnu rẹ fun Naijiria jade loju ọpọ ero ni Eagle Square Awọn olori orilẹ-ede to wa nijoko nibẹ pẹlu Buhari lasiko ayajọ ijọba tiwa n tiwa naa ni aarẹ orilẹ-ede Rwanda, Chad, Niger ati Gambia. 9th Assembly: Aráàlú ní àwọn ń fẹ́ ìpèsè àwọn ohun èèlò amáyédẹrùn",0,yoruba "RT @user: """"""""""""""""@user: Kò sí ẹni tí Ọlọ́run ò ṣe fún, àfi ẹni tó bá ní tòun kò tó. #Owe #Yoruba""""""""""""""""Beeni o",0,yoruba fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Alàji lo tun se joko.,0,yoruba @user ọ̀pẹ́lẹ́ngẹ́ ṣubú l'àwo!,0,yoruba "RT @user: @user a o ni ji l'eku l'owo, a o ni ji l'arun l'owo º°˚˚°º ,,,,,, okookan l'ama ji o. █▓▒░O░D░A░R░O░▒▓█",0,yoruba fẹ. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìwà: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọba lo ni iwa rere lojiji.,0,yoruba ènìyàn a yi lo ti o nuni ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ àti ìbi tí wọn wà.,0,yoruba RT @user: @user ...ojumo re...oni a san wa oooo,0,yoruba ṣé o mọ̀ pé ògúnǹdé ṣe eré rí pẹ̀lú tó jẹ́ ìgbà kan ní gtgtgt,0,yoruba olóótọ fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Ní.,0,yoruba "lálai. Nitori eyi, ara eni lo ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.",0,yoruba owo ṣẹlẹ ni Ibadan ti gbogbo eniyan sọ o dara. (1993),0,yoruba "Onírìn àjò ìgbafẹ́ tí ó ń lo ìwé - ìrìnnà Orílẹ̀ - èdè Canada ni apànìyàn náà , ẹni tí ó gún òǹtajà ìsọ̀ náà nígbà tí òǹtajà bíi léèrè ìdí tí ó fi kó ọjà láì san owó .",0,yoruba "Gbigba iwosan niiṣe pẹlu bi eniyan ba ṣe ṣe aisan si nitori arun Coronavirus le ma lagbara lori awọn eniyan kan, amọ ko si ṣọṣẹ lara awọn eniyan miran. Awọn ohun to niiṣe pẹlu bi eniyan ba tete ri iwosan gba si ni ọjọ ori, ọkunrin tabi obinrin ati boya ẹni naa ni aisan abẹnu tẹlẹ. Ti eniyan ba tete lọ si ile iwosan, ki o bẹrẹ iwosan naa niiṣe pẹlu bi eniyan yoo ṣe gba iwosan si. Ti apẹẹrẹ arun Coronavirus ko ba buru ju nkọ? Ọpọlọpọ awọn eniyan to ba ni arun Coronavirus ko ni awọn apẹẹrẹ to koja agbara ju. Wọn le e wukọ tabi ni iba, ara riro, ọfun dundun ati ori fifọ. Ikọ wiwu naa le ma le lakọkọ, amọ to baya, wọn yoo ba wukọ ti yoo ma tu nkan jade. Ọna ati gbogun ti arun naa ni ki eniyan sun daadaa, ki eniyan mu omi daadaa ati lilo oogun ara riro tabi ori fifọ bii paracetamol. Awọn ti apẹẹrẹ wọn ko ba le ju yoo tete ri iwosan gba laarin ọsẹ meji. Ti apẹẹrẹ ami arun Coronavirus ba le ju nkọ? Arun yoo le peleke si fun awọn miran, eleyii to le jẹ bi ọjọ mẹwa lẹyin ti wọn ba ti ni arun naa lara. Ayipada naa le tete ṣẹlẹ, eemi le di iṣoro, ki ọna ọfun sibẹrẹ si ni dun eniyan. Ohun to ṣẹlẹ ni wi pe awọn eroja ara n tiraka lati gbogun ti arun Coronavirus naa, eleyii le fa ki awọn eroja ara bẹrẹ si ni ṣiṣẹ aṣeju, eleyii to ba ago ara jẹ. Awọn miran le nilo itọju ni ileewosan pajawiri ti wọn ko ba le mi dada. Iwosan fun awọn ti wọn ba ti bẹrẹ si ni lo ẹrọ ventilator lati mi le lo to osu mejila si osu mejidinlogun ni ileewosan, ki ara to bẹrẹ si ni pada si ipo notori ọpọlọpọ eroja ara lo ti sọnu lasiko ti ara n ba arun Coronavirus naa ja. Ajọ Isokan Agbaye ni ẹnikan ninu ogun eniyan to ba ni arun Coronavirus lo ma n nilo itọju pajawiri, eleyii le jẹ ki wọn kun ẹni naa loorun ni ileewosan tabi ki wọn bẹrẹ si ni lo ẹrọ ventilator lati mi fun ara wọn. Kí lo mọ̀ nípa fẹntilétọ̀, ohun èlò aṣèrànwọ́ èémí Kí làwọn ìdàmú tí Coronavirus n mú bá àgọ́ ara? Ǹjẹ́ ewé dongoyaro lè wo aàrùn coronavirus? Coronavirus Vaccine: Ṣé abẹrẹ àjẹsára ti wà fún àrùn COVID-19? Ǹjẹ́ àrùn Coronavirus leè wà lára èèyàn títí lái?",0,yoruba Ṣí líǹkì nínú fèrèsé yìí,0,yoruba "Omí tí kò gbóná, tí kò tutù, ó ṣe kíni? #ibeere",0,yoruba "Kólékólé ọ̀hún yóò tú àṣírí ara rẹ̀ síta gbangba ni, afẹ́fẹ́ á fẹ́, a óò sì rídìí ẹdìẹ. Ìgbálẹ̀ lásán ni yóò ṣiṣẹ́ yẹn. #OwoFunOle #Yoruba",0,yoruba "Ìtókun ni wọ́n ti bí Líṣàbi, tí ó sì dàgbà sí Ìgẹ́ìn. Ẹni tó ga, to sì fẹ́ láyà ni. Akọni tí ń darí àwọn èèyàn. Líṣàbi mú ètò àwọn àgbẹ̀, tí ń ṣe """"""""""""""""Ààrò"""""""""""""""" (ìrànlọ́wọ́ àgbẹ̀ kan fún àgbẹ̀ òmíràn nínú oko rẹ̀), láti kó àwọn ọmọ ogun jọ ní ìkọ̀kọ̀, bí wọ́n ti ń",0,yoruba "Sadio Mane, agbabọọlu Senegal lo gba bọọlu to sọ Senegal di ajagungbade idije ife ẹyẹ bọọlu Afrika, African Nations Cup lẹyin ti ifẹsẹwọnsẹ naa pari si ọmi, ti wọn si fi pẹnariti yanju ọrọ naa pẹlu Egypt. Agbabọọlu ikọ Liverpool naa ti kọkọ sọ pẹnariti to bọ sọwọ Senegal nu nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju keje, lẹyin ti wọn gbe agbabọọlu Egypt, Saliou Ciss ṣubu loju ile ikọ Egypt. Amọ ṣa, aṣọle ikọ Paharaoh ti Egypt naa, Gabaski di eegun ẹja si Mane atawọn atamatase Senegal lọrun pẹlu bi o ṣe n mu gbogbo awọn bọọlu ti wọn n taari si ọdọ rẹ. Igba akọkọ niyi ninu iwe itan Senegal ati ti idije naa, ti orilẹede ọhun yoo maa gba ife ẹyẹ odu awọn agbabọọlu orilẹede Afirika naa. Ilana gbe e silẹ, ko gba a si goli, iyẹn pẹnariti ni wọn fi gbẹyẹ mọ Salah atawọn agbabọọlu akẹgbẹ rẹ lati Egypt lọwọ. Lai naani pẹnariti ti Mane sọnu, n ṣe lawọn agbabọọlu Senegal n ṣigun kọlu oju ile Egypt loorekoore, sibẹ ẹṣin wọn ko le e ta ni gbogbo bi ifẹsẹwọnsẹ naa ṣe n tẹsiwaju. Lẹyin ọgọfa iṣẹju ti ikọ mejeeji yii fi woju ara wọn ni aṣekagba idije ife ẹyẹ bọọlu ilẹ Afirika naa, laisi ẹni to fi ajulọ han ara wọn ninu orilẹede mejeeji, lo mu ki alamojuto ifẹsẹwọnsẹ naa, iyẹn rẹfiri, fọn fere pe ilana gbe e silẹ, ko gba a si goli, pẹnariti ni wọn yoo fi yanju rẹ. Bona Sarr nikan lo gba tirẹ sọwọ goli lara awọn agbabọọlu Senegal, ti Abdel Meneam ati Mohana Ahmed lati ikọ Egypt pẹlu kuna lati gba tiwọn wọle. Eyi lo mu ki Senegal bori idije naa pẹlu goolu mẹrin si meji. Awọn koko manigbagbe nipa ifẹsẹwọnsẹ naa:",0,yoruba "Ní ní àìlẹ̀, Baàlè ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..",0,yoruba "Nígbà tó kún jú, àwọn ènìyàn ni ó pa Alàji lo tun se joko.",0,yoruba "RT @user: Eyin eyan wa, e jade Ni ojo Kejo Osu Erena lati rin Tori ibalopo tipa tipa. E je ka beere fun idabobo to peye #MarchAg…",0,yoruba "dara. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Bàbá lo ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba óóga o alákòwé à fi sùúrù o nkan ńbẹ ẹ̀yin èèyàn mi òjóró ojúkorojú yìí pọ̀ lápọ̀jù o,0,yoruba nípa ara eni lo ni ìgbà mi owó àkokò eyti o gbe lori ọ̀run dídì.,0,yoruba "RT @user: Onígbèsè èyàn ti kú, a kò tíì sìnkú rẹ̀ ni /A chronic debtor has died, he simply hasn't been buried.[Be cautious with…",0,yoruba tí wọ́n bá ní èèyàn lóògùn ìkà dé góńgó orúkọ wo ni wọ́n máa ń fi ṣe àfiwé a ògbùró b ẹ̀gbẹ̀jí d àrọ̀nì,0,yoruba "Aisha Raheem àtí Victor Boyle-Komolafe ti pegedé nínú àwọ́n orúkọ tí wọ́n fi sílẹ̀ fún àmì ẹ̀yẹ 2020 Africa Prize. Eka Ami Ẹyẹ onimọ ẹrọ ni wọn fi orukọ wọn si. Aisha Raheem gbe imọ ẹrọ kalẹ ti yoo ma a ran awọn agbẹ lọwọ ati ẹbi wọn lati ri wi pe wọn ko ko ounjẹ danu lọna aitọ. Bakan naa ni Victor Boyle naa gbe imọ ẹrọ jade ti yoo ma se atunlo awọn nkan ti awọn eniyan ko lo mọ lati gbe ohun ara ọtọ jade. Tani Victor Boyle-Komolafe to fẹ gba Ami Ẹyẹ 2020 Africa Price? World Diabetes Day: Ọdún kọkandinlogun ti mo ti wà lẹ́nu itọ ṣúgà nìyí Ọlọpàá gba owó ilé ìwé #150,000 lọ́wọ́ akẹ́kọ̀ọ́ DELSU kan Ẹ̀rù kò bà mí láti padà sí Bolivia- Evo Morales Ikú ni fífi oògùn 'Paracetamol' bọ ẹran tàbí se ẹ̀wà- Iléeṣẹ́ ìlera Messi gọ̀ láti sọ fun akọ́nimọ̀ọ́gbá Brazil pé kó gbẹ́nu dákẹ́- Thiago Silva Tani Aisha Raheem to fẹ gba ami ẹyẹ 2020 Africa Price? Divorcee: Ó sàn kí wọ́n yàgò fúnra wọn ju ki wọ́n ṣe ara wọn léṣe- Fisayo Èèyàn 2,040 làwọn agbésùnmọ̀mí ti pa ní Nàìjíríà lọ́dún yìí- Ìwádìí Àbá ìsúná N1.3 trillion ni CBN gbé jáde fún ọdun 2020 Ǹjẹ o yẹ kí èèyàn máa sùn lẹ́nu iṣẹ́? Goodluck Jonathan jẹ́ olùfọkànsìn àti ìwúrí fún ìrandíran ní Nàìjíríà - Buhari Ẹ wo fídíò Kìnìhún ní ibùgbé rẹ̀ tuntun ní Bogije, Lekki",0,yoruba "Ẹjọ, níbo ni aare ọna Kakanfo wa? #Yoruba",0,yoruba wúlò. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìṣẹ̀: ti o nuni ti o nuni ti o dun.,0,yoruba owo ṣẹlẹ ni Lagos ti gbogbo eniyan sọ o dara. (2001),0,yoruba mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o nuni ti o wulo.,0,yoruba "Reposted from @user Hello fam, let's have some fun and to all my Saki people, gather here, """"""""""""""""ẹ wá fi etí gbé ìyàwó ọ̀rọ̀."""""""""""""""" saki.finest mufutau_natalia . . #asa #yoruba_pikin #yoruba_pikin👑 #ede #yoruba #saki… https://t.co/jcoA6GqSDT",0,yoruba "'A sọ fún ọlọ́kadà pé omi kún, omi kún, ṣùgbọ́n ó kọ etí ikún' Olugbe adugbo naa kan fi inu iho ti wọn ni Adediwura ko si han akọroyin BBC Yoruba. Ọpọ eeyan lo ti n bere pe Kí ló ṣe ikú pa Adewura Latifat Bello lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ méjì tí wọ́n ń wá a? O ṣalaye pe igbakuugba ti ojo ba ti rọ, adugbo naa kii ṣe ohun tẹnu le sọ rara nitori fọfọ ni gbogbo ilẹ yoo kun fun omi, ẹrọfọ ohun idọti to bẹẹ ti eeyan ko ni mọ ibi aa tẹsẹ bọ. Daju daju kii ṣe oni ni iho yii ṣẹṣẹ ṣi silẹ ni agbegbe naa eyi lo mu ki wọn ""pariwo fun ọlọkada naa pe ojo n rọ, ojo n rọ ṣugbọn to kọ ti ko gbọ"". Àgbà ni Obasanjo, oun tó ń sọ yé e, ìjọba ni kó tají - Wale oke O ni bi ọlọkada naa ṣe ""lọ lari mọ ibi iho naa ti arabinrin to gbe si ko sinu rẹ niyẹn, wọn si kilọ fun un ṣugbọn boya o ti mọ bo ṣe n gba na yii tẹlẹ"". Wọn mu BBC Yoruba rin agbegbe naa ka ti a si rii wi pe yatọ fun iho to ṣi silẹ yii, gọta ti agbara ojo ti maa n ṣan wọọ wọọ wa nibẹ bẹẹ si ni koto ti omi maa n rọ jọ si wa nibẹ. Lai ni imọ eyi, Adediwura mori gba ọna agbegbe Abesan lọjọ naa ninu ojo, lori ọkada, to si ba ọlọjọ lọ nipasẹ agbara ojo to n ṣan.",0,yoruba "RT @user: @user month ki eyin na o, se laafia ni? E ji re bi?",0,yoruba "nìkan. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba Ìyá lọ. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó wáyé..,0,yoruba "Ile ẹjọ Crown Court to wa ni Birmingham sọ pe tọkọ-taya naa sọ ọmọ wọn ni Adolf lati fi bu ọlá fun olori ikọ̀ NAzi to ti papoda. Wọn fi ẹsun kan Adam Thomas, ẹni ọdun mejilelogun, ati Claudia Patatas, ẹni ọdun mejidinlogoji, to fi mọ Daniel Bogunovic, ẹni ọdun mẹtadinlọgbọn, pe wọn jẹ ọmọ ẹgbẹ́ ọlọtẹ National Action. Tọkọ-taya Patatas ati Adam Thomas sọ ọmọ wọn ni Adolf nitori ifẹ ti wọn ni si Hitler Ṣaaju asiko yii ni wọn ti fi ofin de ẹgbẹ National Action nilẹ Gẹẹsi, lẹyin ọdun mẹta ti wọn bẹrẹ rẹ l'ọdun 2013, ti wọn si ṣe ajọyọ lẹyin ṣiṣekupa aṣofin Jo Cox.. Ile ẹjọ sọ pe ẹjọ́ naa da lori i idunkooko mọni to n jẹyọ lati ara igbagbọ pe awọn alawọ funfun ni laari ju awọn ẹya to ku lọ. Ìwẹ̀ wíwẹ́ má n dín agbára ìrẹ̀wẹ̀sì ọkàn kù Ileeṣẹ ọlọpa sọ pe awọn ba àdá meji, ọfà, to fi mọ ọpọlọpọ àsìá ati awọn nkan mi i to jẹ ami idanimọ asiko ti ikọ Nazi n dari, ati ti National Action ti wọn fi ofin de, ni yaara ibusun Thomas ati Patatas. Sugbọn ninu ọrọ rẹ, Thomas sọ pe aṣọ ẹgbẹ́ okunkun ti oun fi ya aworan jẹ eré lasan, ṣugbọn o gba pe lootọ ni oun n dẹ́yẹ si awọn ẹ̀yà to ku. Ọjọ kẹrinla, oṣu Kejila ni wn yoo ṣe idajọ wọn.",0,yoruba Eni a fe la mo..... https://t.co/dMrk6xoO2Z,0,yoruba "'Ọmọogun Nàìjíríà Onimọ nipa eto abo lagbaye, Temitope Olodo lo salaye pe ile isẹ ologun nilo lati gba awọn onimọ nipa kikoju ikọ adunkokomọni lọna igbalode. Temitọpe ninu ọrọ rẹ sọ wi pe Naijiria ko ni awọn onimọ to le sọ gbogbo bi awọn Boko Haram se n rin, ati ibi ti wọn ba n rin si, ki wọn ba le maa fi iroyin to yẹ lede fun awọn ọmogun to n koju Boko Haram. Beautiful Nubia: Kò sí wàhálà tó ń ṣẹlẹ̀ láàgbáyé tí kò ní ọwọ́ ẹ̀sìn lábẹ́nú Lori ọrọ ti adari awọn osisẹ ologun Naijiria sọ pe Boko Haram ti n lo ohun ija drone, onimọ nipa eto abo naa fi kun un wi pe ile isẹ ologun ofurufu Naijria nilo lati gba awọn eniyan si isẹ ti yoo ran wọn lọwọ lati lo awọn ohun ija igbalode ati imọ ẹrọ fun ibanisọrọ. Tẹmitọpe Olodo ni ""awọn ọmọ ikọ Boko Haram ko koju awọn ọmọogun Naijiria pẹlu ohun ija igbalode, sugbọn wọn lo ""armour tank"" pẹlu ibọn lati wọ inu baraaki wọn lati koju ija si wọn"". ""Wọn nilo agbada satalite ti yoo ma sọ igba ati akoko bi awọn Boko Haram se n gbero lati koju wọn"". ""Ati wi pe wọn nilo ‘anti-drone’ lati jagun naa lai si iru isẹlẹ to pa ọgọọrọ awọn ologun Naijiria mọ"". Ti a ko ba gbagbe, ọdun to koja ni ijọba apapọ lorilẹede Naijiria, sọ wi pe awọn yọ biliọnu Dọla kan kuro ninu apo ijọba apapọ lati lẹ ra ohun ija igbalode fun awọn ọmọogun. 'Ọmọọgun 23 ló kú ní Metele, 31 farapa ní ìkọ̀lù Borno' Ile isẹ ologun lorilẹede Naijria ti sọ wi pe eniyan mẹtalelogun lo ku ninu ikọlu ti awọn ikọ Boko Haram ṣe si ibudo ọmọ ogun kan lagbeegbe Metele ni ipinlẹ Borno, ti mọkanlelọgbọn si farapa. Ikọlu to waye ni Ọjọ Kejidinlogun, Osu Kọkanla, ọdun 2018 ni ọpọlọpọ iroyin sọ wi pe o mu ẹmi ọmọọgun to to ọgọrun lọ, ti ọpọlọpọ si di awati, ṣugbọn ile iṣẹ ologun sọ wi pe ko si otitọ ninu iroyin naa. Abdulfatah Ahmed: PDP kò fi tíkẹ́ẹ̀tì mi fa ojú ẹnìkejì mọ́ra Ninu atẹjade ti ọga awọn ọmọọgun ilẹ Naijiria, Ọgagun Tukur Buratai fi lede gba ọwọ Ọgagun Sani Usman ni lootọ ni ikọ Boko Haram se ikọlu si awọn ọmoọgun ni Ọjọ Keji ati Ọjọ Kẹtadinlogun, Osu Kọkanla, ọdun 2018 ni agbeegbe Kukawa, Ngoshe, Kareto ati Gajiram. Beautiful Nubia: Kò sí wàhálà tó ń ṣẹlẹ̀ láàgbáyé tí kò ní ọwọ́ ẹ̀sìn lábẹ́nú Usman ni awọn ọmọogun Naijiria bori ikọ Boko Haram,sugbọn ọmọogun mẹrinlelogun ni ẹmi wọn lọ si ikọlu naa, ti mejila si farapa ninu ikọlu naa. Wo ìdí tí Boko Haram fi ń pa ọmọogun Nàìjíríà Iku ọwọọwọ awọn ologun Naijiria ti o n koju ikọ agbebọn Boko Haram ti n kọ ọpọ lominu. Oniruuru ikọlu ti Boko Haram ti gbe kọlu awọn ọmọogun Naijiria ni o jasi iku ọpọ ọmọogun lọpọ igba. Iroyin awọn ọmọogun ti wọn ku laipẹ yii lẹyin ti awọn agbebọn Boko Haram ya bo ibudo wọn ni ilu Metele ni ipinlẹ Borno, ti fa ọpọ ẹhonu lorilẹede Naijiria ati agbaye. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Adedoyin: Tí mo bá rí Buhari, màá sọ fun kó rántí pé Ọlọ́run wà Amọṣa, ẹni to ti fi igba kan ri jẹ ọgagun agba ileeṣẹ ologun lorilẹede Naijiria, Ajagunfẹyinti Marthin Luther Agwai ni, bi awọn ologun ṣe n ku iku ọwọọwọ naa ko le ṣai ri bẹẹ nitori irufẹ ogun ti wọn gba ikọni fun yatọ si eyi ti wọn n koju lọwọ. Ajagunfẹyinti Marthin Luther Agwai ṣalaye pe, ogun kọju simi ki n kọju si ọ ni awọn ọmọogun Naijiria kọ nipa rẹ, kii ṣe eyi ti wọn n ba awọn Boko Haram ja lọwọ. Iku ọwọọwọ awọn ologun Naijiria ti o n koju ikọ agbebọn Boko Haram ti n kọ ọpọ lominu ""Ṣe ki n maa parọ fun yin, ọfọ nla ni pe a padanu iye awọn ọmọogun to pọ to bayii"" Amọ o ni ko yẹ kawọn ọmọ orilẹede Naijiria sọ ireti nu ninu ijafafa awọn ologun orilẹede yii, pẹlu afikun pe bi yoo ṣe ri niyi nitori irufẹ ogun ti wọn n ja lọwọ. ""Bi aja ba bu eniyan jẹ, kii ṣe iroyin ṣugbọn ni ọjọ ti eniyan ba yi oju pada lati bu aja jẹ ni ariwo yoo ta. Iroyin kii pọ lori iye awọn agbebọn Boko Haram ti awọn ologun ti pa tabi mu si ahamọ?"" ""Idi ni pe aja lo n bu eniyan jẹ nigba yẹn. Ojuṣe ti a n reti lọwọ awọn ologun niyi."" Agwai ni ko si ologun ṣe lee ja iru ija yii ti wọn ko ni fara gba ọta. O ni ko si bi awọn ọmọogun yoo ṣe maa ja ogun bayii lai ni fara kaaṣa ikọlu awọn agbebọn yii. Ibeere lori biliọnu kan dọla owo ilẹ Amẹrika ti Buhari beere lati na lori ọmọogun Ni ibẹẹrẹ ọdun 2018 ni aarẹ Buhari buwọlu biliọnu kan dọla owo ilẹ Amẹrika fun rira awọn nnkan ija ogun fun awọn ologun lati koju Boko Haram. Ni gba naa, kii ṣe ede aiyede kekere lo waye laarin ẹka aṣofin, ẹka iṣakoso ati awọn alatako, paapaa julọ ẹgbẹ oṣelu PDP, to fi mọ igun kan laarin awọn ọmọ orilẹede yii. Nibayii ti ọrọ ikọlu ati pipa awọn ọmọogun ti wa n di lemọlemọ bayii, ọpọ lo ti n ṣe ibeere pe nibo ni owo naa wọlẹ si ati pe kini wọn n fi awsn ohun ija ogun ti wọn ra ṣe ti o fi di pe awọn agbebọn yii n gbẹyẹ mọ awọn ọmọogun lọwọ lẹnu ọjọ mẹta yii. Nibo lo kan? Oniruuru iroyin lo ti jade ni pa iye awọn ọmọogun ti wọn ku ni pato ninu ikọlu naa Lẹnu oṣu diẹ bayii lemọlemọ ni ikọlu awọn ologun lorilẹede Naijiria lati ọdọ awọn agbebọn Boko Haram yii. Awọn ibudo ologun lawọn ilu bii, Metele (November 18), Kekeno (September 23), Mainok, Gajiram, Gashigar (September 25), Damsak (September 12), Zari (August 30), Garunda (August 8) ni awọn agbebọn yii ti kọlu. Bi awọn onwoye kan si ti n sọ, ikọlu wọnyii ni batani bi o ti n lọ eleyii ti o mu ki wọn maa beere pe nibo lo tun kan bayii? Akọroyin kan, Ahmad Salkida ṣalaye lori ikanni twitter rẹ pe ọwọ ti awọn ikọ agbebọn yii fi n gba awọn eeyan tuntun si agbo wọn n fẹ amojuto. O ni lọwọ yii ipo akọkọ ni ikọ agbebọn Boko Haram ti wọn n pe orukọ rẹ ni ISWAP laarin awọn ẹgbẹ agbesunmọmi ati agbebọn lagbaye. SERAP ní kí Buhari gbé Dasuki, Jonathan lọ síwaju kóòtù àgbáyé Buhari ni ijọba yoo pese oun ija to peye fun awọn ọmọ ogun Naijiria Iṣẹlẹ bi awọn Boko Haram ṣe kọlu ikọ ọmọogun Naijiria laipẹ yii ti wọn si pa pupọ ninu wọn ti di eyi ti eeyan lee sọ pe gbogbo agbaye ti gbọ. Oniruuru gbọyisọyi lo si ti ti ara rẹ jade lagbo oṣelu, awujọ orilẹede agbaye ati laarin awọn sms orilẹede Naijiria funrawọn. Ni ọjọ abamẹta ni aarẹ Buhari funrarẹ pẹlu bu ẹnu atẹ lu iṣẹlẹ naa ti o si tẹnumọ ipinnu ijọba rẹ lati rii pe aabo wa fun tẹrutọmọ lorilẹede Naijiria. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Èmi kì í ṣe olórí tí kò bìkítà nípa ọmọlẹ́yìn rè-Ààrẹ Buhari Pín fídíò 'ayédèrú' kó o ríjà ológun Nàìjíríà Amọṣa, ẹgbẹ ajafẹtọ ọmọniyan kan ti o fi orilẹede Naijiria ṣe ibugbe ti ke gbajare sita pe ko yẹ ki ọrọ naa ms bẹẹ, ayaafi ki aarẹ tete gbe iwadi kalẹ lati tan ina wadi bi wọn ṣe n na gbogbo owo ti wọn n ya sọtọ fun nina lẹka abo ati ileeṣẹ ologun ninu eto iṣuna orilẹede Naijiria bẹrẹ lati ọdun 1999 si 2018. Ikẹdun Ààrẹ Buhari yí n wáyé lẹyìn bí ọjọ máàrún tí ìròyìn ìṣẹlẹ ikọlù àwọn ọmọ ogún pẹlú ìkọ Boko Haram wà ye SERAP ni ni ibi ti ọrs de duro bayii ti awọn ọmọ ogun orilẹede Naijiria wa n ku iku ọwọọwọ loju ija, o to ki aarẹ dari gbogbo ẹsun iwa ijẹkukjẹ to niiṣe pẹlu nina owo to yẹ fun rira nnkan ijagun fun awọn ologun lorilẹede Naijiria si iwaju kootu agbaye, ICC. Ninu lẹta kan ti o kọ ṣọwọ si aarẹ Buhari, ajọ naa ni, ""ẹgbẹlẹgbẹ biliọnu naira ni a ti ya sọtọ fun ileeṣẹ ologun lati daabo bo orilẹede yii ṣugbsn ko jọ bi ẹni pe eyi ti ni ipa kankan ninu ipa awọn ọmọogun Naijiria lati dojukọ awọn agbebọn BokoHaram atawọn iks agbebọn miran lorilẹede Naijiria."" SERAP ní kí Ààrẹ Buhari darí gbogbo àwọn ìwé ẹ̀sùn ìkówójẹ tí ó bá rọ̀ mọ̀ ríra ohun èlò ológun ránṣẹ́ sí kóòtù àgbáyé Ajọ naa woye pe bi ọrs ṣe ri bayii, ti awọn ologun ko lee wawọ kilanko awọn agbebọn naa bọlẹ, o fihan pe ejo lọwọ ninu pẹlu bi wọn ṣe n ṣe awọn owo ti wọn ya sọtọ labẹ iṣuna orilẹede Naijiria fun ẹka aabo. Ààrẹ Buhari kẹ́dùn lórí ikú àwọn ológun ní Metele Eyi kii ṣe igba akọkọ ti Buhari yoo ma kẹdun pẹlu awọn ọmọ Naijiria lori ipaniyan Lẹyin nnkan bi ọjọ maarun ti iroyin pe ikọ Boko Haram ṣe iku pa awọn ọmọ ogun Naijiria,Aarẹ Muahmmadu Buihari ti ba awọn ọmọ Naijiria kẹdun lori iṣẹlẹ naa. Ikẹdun rẹ ti o wa ninu atejade kan ti agbẹnusọ ileeṣẹ Aarẹ Garba Sheu fi sita lọjọ Aiku so pe ''inu Aarẹ Buhari bajẹ pupọ lori iṣẹlẹ iku awọn ọmọ ogun ni abule Metele lọwọ Boko Haram'' Aarẹ Buhari so ninu atejade naa pe ''ko si olori kankan ti yoo kawo pọnyin ti yoo si ma wo bi awọn agbesunmọmi yoo ṣe ma ṣeku pa awọn ọmọogun rẹ'' O ni ohun n ṣe ipade pẹlu awọn olori ọmọogun lati ri wi pe awọn koju Boko Haram. Buhari ni ijọba yoo pese oun ija to peye fun awọn ọmọ ogun Naijiria. Ija laarin awọn ologun Naijiria ati ikọ Boko Haram ti n lọ ti pẹ O tẹsiwaju wi pe oun 'ṣetan lati fun awọn ọmọ ogun wa ni gbogbo iranwọ ti yoo mu wọn ṣe iṣẹ wọn bo ti ṣe yẹ' Lai pe yi ni iroyin gbode nipa iku awọn ọmọogun Naijiria lọwọ ikọ Boko Haram ni abule Metele ni ipinlẹ Borno. Iṣẹlẹ naa mu ki ara ilu bẹnu atẹ lu ijọba Buhari ti o ni oun ti dẹkun agbara ikọ Boko Haram. Ile ise ologun ko sọ pato iye ọmọogunto ku ninu ikọlu naa sugbọn awọn iroyin kan ni wọn le ni ọgọrun. Fidio orisirisi ni o si ti gba ori ayelujara nibi ti awọn ọmọ ogun ti n ke gbajare si Aarẹ Buhari lati wa wọrọkọ fi sada lori bi awọn olori wn ko ti ṣe ra nnkan ija fun wọn lati koju Boko Haram. Ilé iṣẹ́ ológun orílẹ̀èdè Nàìjíríà ti ní lóòtọ́ ni ikọ̀ Boko Haram kọ lu àwọn ológun tí wọ́n sì pa lára wọn ní Metele, ìjọba ìbílẹ̀ Abadam, ìpínlẹ̀ Borno. Ọ̀rọ̀ tó jáde láti olú ilé iṣẹ́ ológun Nàìjíríà sọ pé ìkọlù tí àwọn ẹsin ò kọ'kú Boko Haram ṣe sí ọ̀wọ́ ogun 157 Task Force Battalion wáyé ní ọjọ́ kejìdínlogún oṣù kọ́kànlá ṣùgbọ́n kò sọ iyé ọmọ ogun tó kú. Àwọn oníròyìn sì ti bábá gbé e síta wí péó lé ni ààdọ́rin ọmọ ogun tí wọ́n ti pa tó fi mọ́ olórí ọ̀wọ́ ogun náà, fídíò rẹ̀ sì ti gba gbogbo orí ẹ̀rọ ayélujára. Ibi ìpamọ̀ ohun ìjagun púpọ̀, ta ìbọn àti ohun èlò àwọn ológun ni ikọ̀ Boko Haram kó lọ lákokò ìkọlù yìí tó wáyé ni Metele, ìjọba ìbílẹ̀ Abadam ní ìpínlẹ̀ Borno. Iléeṣẹ́ ológun Nàìjíríà kò tíi fo hùn lórí ìròyìn náà Ìbò tó ń bọ̀ ló fa ìkọlù Boko Haram àti ọmọ ogun Ọga ileeṣe ọtẹlẹmuyẹ DSS tẹlẹ lorilẹede Naijira Mike Ejiofor ti sọ pe ibo to n bọ lọna lo jẹ ki ikọlu Boko Haram pẹlu awọn ọmọ ogun Naijiria pọ si lẹnu lọọlọ yii. Ejofor to ba BBC sọrọ yii lẹyin ti ara awọn ẹgbẹ agbesumọmi Boko Haram, Islamic State West Africa Province(ISWAP) pa ọpọ ọmọ ologun ti wọn si tun ko nnkan ija wọn lọ. O fikun ọrọ rẹ pe Boko Haram ko ni gbagbọ ninu eto ijọba awa-ara-wa, eleyi lo jẹ ki wọn maa da rukerudo silẹ ki ẹru le maa ba awọn eeyan ṣaaju idibo ọdun 2019. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ejiofor tilẹ tun sọ pe o ṣeeṣe ki awọn ọmọ ologun ti Boko Haram pa ju iye ti ile iṣẹ ọmọ ogun Naijiria fi lede lọ, nitori wọn o ni fẹ ki awọn ọmọ ologun ti wọn si n ja kaya soke. Awọn ile iṣẹ ologun Naijiria kọ lati sọrọ nigba ti BBC kan si wọn lori ọrọ yii. Boko Haram ti fi ẹmi ọpọ ọmọ ogun orilẹede Naijiria ṣofo lati bi ọdun meji wa sẹyin, bo tilẹ jẹ pe ijọba ni ohun ṣẹgun agbesumọmi Boko Haram Iléeṣẹ́ ológun Nàìjíríà kò tíi fo hùn lórí ìròyìn náà Boko Haram pa ọmọ ogun Nàìjíríà mẹ́tàléláàádọ́ta Ìròyin tó tẹ̀ wá lọ́wọ́ láti ìpínlẹ̀ Borno tó wà ní àríwá Nàìjíríà ń sọ wí pé Boko Haram ti pa ọmọ ogun Nàìjíríà àti àwọn àgbẹ̀ mẹ́tàléláàádọ́ta' láàrin ọjọ́ mẹ́ta. Súgbọ́n iléeṣẹ́ ologun orílẹ̀-èdè Nàìjíríà kò tíì sọ ǹkankan nípa ìròyìn náà. Ilé iṣẹ́ ìròyìn AFP fidi ẹ mulẹ lati ọdọ àwọn ológun kan tí wọ́n sọ wí pé ìkọ̀ Boko Haram pa, ó kéréjù, sọ́jà mẹ́tàlélógójì ( 43) ní oko Metele tí kò jìnǹa sí ẹnu aàlà orílẹ̀-èdè náà àti orílẹ̀-èdè Nìjẹ́r ní ọjọ́ Àìkú. Ológun náà sọ pé: ""Wọn pa àwọn ọmọ ogun wa, lẹ́yìn náà ni wọn gba bárékè wa nígba tí a dáná fún rawa yá. Sọ́jà náà ṣe àfikún pé àwọn ológun ti wo inú igbó láti wá àwọn sọ́jà tí wọn sọnú lẹ́yìn ìkọlù náà. Àwọn ọmọogun aráìlú fi tó iléeṣe AFP létí pé ikọ̀ Boko Haram náà wa ọkọ̀ bíi ogún (20), wọn kò sì rí ìrànlọ́wọ́ àwọn ọmọ ogun míràn títí tí àwọn ikọ̀ Bko Haram náà fi dòyì ká bárékè náà tí wọn sì kó nǹkan ìjagun lọ́ ."" Ní ọjọ́ náà ni Boko Haram kọlu oko Gajiram láàárọ̀ kùtù-kùtù. Oko náà tó máìlì mọ́kàndínláàádọ́ta (49 miles) sí Maiduguri, olú ìlú ìpínlẹ̀ náà. Ará oko náà sọ fún iléese AFP pé àwọn Boko Haram àti ológun náà jà fún wákàtí díẹ̀. Boko Haram n gbẹbo laarin awọn orilẹ ede ilẹ Adulawọ",0,yoruba "fè mú, Nitori eyi, ara eni lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde sí ara ilẹ̀.",0,yoruba @user @user Àwa nìyẹn jàre. Àwa ò lè wá kú :),0,yoruba "Yoruba ni to ba buru tan, iwọ nikan ni yoo ku. Bẹẹ lọrọ ri fun afurasi ajinigbe kan ti ẹnu ko sin lara rẹ lẹnu ọjọ mẹta yii, Hamisu Bala, ti gbogbo eeyan mọ si Wadume, ẹni to kede pe ẹgbẹ oselu APC fun oun ni miliọnu mẹtala naira lasiko eto idibo apapọ to kọja. Bẹẹ ba gbagbe, afurasi yii ni awọn ọlọpa fẹ gbe nipinlẹ Taraba, amọ ti awọn ologun gbaa silẹ, ti wọn si gbẹmi ọlọpa mẹta ati araalu kan lasiko isẹlẹ naa. Nigba ti ọwọ wa tẹ Wadume, lo ba figbe ta pe oun kii se apaayan abi ajinigbe rara, oloselu ni oun, ti ẹgbẹ oselu APC si mọ oun bii ẹni mọ owo, koda wọn fun oun ni miliọnu mẹtala naira lasiko ibo to kọja fun ipolongo ibo, amọ ti oun na miliọnu meje naira nibẹ. Sugbọn niwọn igba to jẹ pe oku ni eeyan pa irọ mọ ti kii lee fọhun, ẹgbẹ oselu APC ti wa kigbe sita fun Wadume pe, yoo dara ko tete sọ awọn to ran nisẹ ibi nitori APC kii fun awọn apaayan ati ajinigbe ni owo. Lanre Issa Onilu, tii se akọwe ipolongo apapọ fun ẹgbẹ APC salaye pe, ọrọ Wadume dabi afomọ to n wa gbongbo ti yoo so mọ ni lasiko to fẹ subu sinu odo, o si di dandan ki Wadume to n koju idajọ fẹ wa awọn ti yoo fẹyin ti ni. ""Ẹgbẹ tiwa kii ya owo sọtọ fun awọn janduku. Asiko yii yatọ si igba ti ẹgbẹ to n sejọba maa n tọwọ bọ apo ilu lati fi owo gbọ bukata ipolongo ibo ati idibo pẹlu, bi ọwọ eku ẹgbẹ oselu wa se mọ, lo fi n họri lasiko yii."" Onilu ni, taa ba gbọ ohun ti Wadume sọ yii daada, a jẹ pe ọmọ ẹgbẹ APC ni yoo jẹ pẹlu awọn alaye to se.",0,yoruba "RT @user: @user Iroyin Pajawiri: Aare egbe ASUU nigba kan ri, Festus Iyayi ku ninu ijamba oko.",0,yoruba "ìwájú. Bàbá lo ni ìgbà mi owó àkokò, Alàji lo lọ.",0,yoruba "Madrid lu Juventus lati gba ife ẹ̀yẹ̀ Champions League ni ọ̀dun 2017 Ṣe ikọ̀ Juventus ṣetan lati gbẹsan nini ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ yii? Pẹ̀lu awọn iriri Giorgio Chiellini ti o sọ pe. ""Emi ko ronu nipa ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ yi bi ẹsan. Nigbati o ba lọ jina ninu idije yii, o pẹ, o ya, o ni lati koju Real Madrid tabi Barcelona. ""Awọn ti o jẹ ẹgbẹ ti o dara julọ ni agbaye ni bayi. Bi o tilẹ jẹ̀ pe, awa naa ni iranti ti o dara ninu awọ̀n ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ wa pẹ̀lu wọn."" Juventus yoo gbiyanju lati bori Real Madrid ni Turin lalẹ ọ̀jọ̀ iṣẹ̀gun Ninu ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ mejilelogun ti o ti waye laaarin awọ̀n mejeeji, ikọ̀ Real Madrid fagba han Juventus lẹ̀ẹ̀mẹ̀jọ̀ ti Juventus si bori lẹ̀ẹ̀meje. Akọ̀nimọ̀ọ̀gba fun Juventus, Massimiliano Allegri wipe ""Real Madrid gba ife eye mejila ni Yuroopu. Wọn jẹ ẹgbẹ agbabọ̀ọ̀lu to dangajia pẹ̀lu, ṣugbọn mo ro pe Juventus yoo fakọ̀yọ̀ ninu idije yii paapa julọ̀ ni abala akọ̀kọ̀"". Ẹ̀wẹ̀, Akọ̀nimọ̀ọ̀gba fun Real Madrid, Zinedine Zidane wipe, ""awọn ẹ̀gbẹ̀ Juventus ko tii ni ayipada pupọ ni akawe si eyi ti a dije pẹlu ni aṣekagba idije ti saa to kọ̀ja ni Cardiff ṣugbọn ere eyi yoo yatọ patapata nitoripe oṣu mẹwa ti kọja bayi lẹ̀yin ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀. Real Madrid lu Jventus pelu ami ayo mẹ̀rin si ẹ̀yọ̀ kan ""Saa yi ko lọ̀ gẹ̀gẹ̀bi mo ṣe ro wipe yoo lọ̀ ṣugbọ̀n inu mi dun nitori pe Real Madrid wa ni ipo ti o dara bayi"". Bakanna, ẹ̀gbẹ̀ agbabọ̀ọ̀lu Sevilla yoo maa gbalejo ẹ̀gbẹ̀ agbabọ̀ọ̀lu Bayern Munich ninu ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ keji lalẹ̀ ọ̀jọ̀ iṣẹ̀gun. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:",0,yoruba "Ọlọ́pá YouTube naa ní ègé olóótọ fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbfi yóò ni Nitori eyi, ara eni lo je gbogbo ise ibile tèmi.",0,yoruba "Nígbà tó kún jú, àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó wáyé.",0,yoruba ìgbàgbọ́ kan wà láàárín àwọn yorùbá wípé bí èèyàn bá kú ẹ̀mí ẹni náà ma lọ fi ara han àwọn èèyàn rẹ̀ ní ilé tàbí ní ibikíbi tó bá ti bá wọn òkú ẹni bẹ́ẹ̀ lè fi ara hàn nípa kí èèyàn tó jọ ẹni tó kú yẹn pẹ̀lú ìrísí àti ara kọjá lára èèyàn nínú ẹbí láì,0,yoruba "E ku irole o! Mi o ni nkankan lati so, sugbon won ni eni ni ojo ti a ma tweeti ni ede Yooba. Oda emi na ti da si ooo... 😁 #TweetinYoruba",0,yoruba "Lọ́jọ́ 30 , oṣù Kìn - ín - ín ní Bubanza , a rán to àwọn akọ̀ròyìn mẹ́rẹ̀ẹ̀rin náà lọ sí ẹ̀wọ̀n ọdún méjì àti àbọ̀ pẹ̀lú kí ẹnìkọ̀ọ̀kan ó sanwó ìtanràn ẹgbẹẹgbẹ̀rún owó francs ( $ 521 owó orílẹ̀ èdè Amẹ́ríkà ) lábẹ́ òfin 16 ti Òfin Ọ̀daràn , tí awakọ̀ sì gba ilé - e rẹ̀ láì sanwó ìtanràn .",0,yoruba 3. Kí nìdí tí a fi máa ń fi aró pa òrò-mọdìẹ lára? #Ibeere #Yoruba #learnyoruba #speakyoruba #InternationalMotherTongueDay #MotherLanguage #MotherTongueDay https://t.co/9SqkKL4izX,0,yoruba "àlùfáà. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "Ọkan tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..",0,yoruba agba ri pe lẹ ìkòkò wey ti o nuni ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ẹkọ́: ti o ní wúlò fún gbogbo.,0,yoruba o wo fun ipilẹ̀ ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba alámọ̀ ni à ń pe amọ̀kòkò alápẹ̀rẹ̀ ní ń hun apẹ̀rẹ̀ ní ń lọ́ ìlẹ̀kẹ̀,0,yoruba ibile. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba ojú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó ṣe pàtàkì.,0,yoruba "@user: @user irun ori #tweetYoruba #AloApamo -- Ó gbàá o, irun orí ni a à lè dá padà síbi tí a ti fà á tu o.",0,yoruba RT @user: @user @user @user Adupe lowo Olodumare fun abo Ategun oru eni ni ilu oba po sugbon Oluwa ko je ki a…,0,yoruba ewoo emii fe fi asiko yii upload omu breast nii oo torii mii o mon asiwerey okunrin kan too maa prefer idi oshii wey awon omu yii ooo asin tii o ba feran omu orun apadi nii straight shoni oyaa werey nii abii kilowi mo so,0,yoruba "tí yóò rò papa re yóò ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Nitori eyi, ara eni ni nfàn ojú kakaaki.",0,yoruba "Adamu lo sọ ọrọ yii nibi ijiroro kan to waye pẹlu awọn gomina ilkẹ Yoruba nilu Eko lori agbekalẹ ọlọpaa agbegbe. O sọ fun awọn akọroyin pe ""Ipade keji niyi ti a maa ṣe pẹlu awọn gomina naa lori agbekalẹ ikọ Amotekun."" Adamu ṣalaye pe ""Gbogbo ipinlẹ lo ni eto abo ti wọn lati koju iwa ọdaran, ikọ Amotekun ko si yatọ si iru agbekalẹ bẹẹ. O ni ajọ ọlọpaa ati awọn gomina naa ti fẹnuko lati sọ ọlọpaa agbegeb ati Amotekun di ọkan ṣoṣo ki eto abo ilu lee jẹ lati ọwọ awọn ara ilu. Adamu sọ pe ajọ ọlọpaa yoo ṣatilẹyin fun awọn eeyan lati ri pe agbegbe wọn wa ni alafia Ọga agba ajọ ọlọpaa naa tẹsiwaju pe ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria yoo lọwọ si igbanisiṣẹ ati idanilẹkọ awọn eeyan ti yoo ṣeṣẹ gẹgẹ bi ikọ Amotekun. Adamu sọ pe eto abo gbọdọ bẹre lati ọdọ awọn ara ilu, lẹyin naa lo rọ awọn eeyan lati fọwọsowọpọ gbogun ti iwa ibajẹ. Adamu pari ọrọ rẹ pe ajọ ọlọpaa yoo ṣatilẹyin fun awọn eeyan lati ri pe agbegbe wọn wa ni alafia.",0,yoruba ọ̀jọ̀jọ̀ a yorùbá food that is made of grated water yam and fried it can be eaten as a snack or food and its best eaten hot oúnjẹ àwọn yorùbá tí wọ́n fi iṣu ewùrà obí iṣu rínrin ṣe a lè jẹ́ bíi ìpapánu tàbí ní oúnjẹ ó dùn jẹ ní gbígbóná,0,yoruba "Oshiomole: Nínú ká máa rin ìrìnàjò ilẹ òkèèrè, ọgá ṣí ní Ọbasanjọ jẹ́ Opọ awọn ọmọ Naijiria ti n sọrọ pe ko si koko pe Aarẹ Buhari n rin irin ajo kaakiriBuhari kàn ń kọwọ́ bọ̀wé nílẹ̀ òkèèrè kiri ni, a ò rí ipa ní Nàijíríà- Onímọ̀ ọrọ̀-ajé Oshiomole fesi yi ni idahun si ibeere awọn oniroyin l'Abuja lori bi aarẹ Buhari ti ṣe fẹran lati ma rinrinajo lọ silẹ okeere lasiko yii. Alaga ẹgbẹ APC naa sọ pe ko si ootọ ninu ọrọ yi. Lati le kin ọrọ rẹ lẹyin, o ni Gani Fawehinmi kọ iwe kan nibi to ti ṣatupalẹ iye igba ti aarẹ Obasanjo fi ririn ajo nigba to wa ni ijọba. Oshiomole ni ''Ki a ma sọ pe aarẹ Buhari fẹran ko maa rinrin ajo lọ si ilẹ ki i ṣe ootọ. Mo ranti daadaa pe ko si aarẹ kankan lati ọdun 1999 titi di isinyi to rinrin ajo to aarẹ ana Olusegun Obasanjo'' Loju Oshiomole, irinajo Buhari ko tii pọ ''Bi ẹ ba wo akọsilẹ daadaa, ẹ o ri ibi ti oloogbe Gani Fawehinmi ti ka iye igba ti aarẹ Obasanjo ti lọ irinajo silẹ okeere. Koda o ka iye wakati to n lo lori ofurufu pẹlu iye igba to fi wa nile'' Lẹnu ọjọ mẹta yii, aarẹ Muhammadu Buhari ti n ṣe awọn irinajo lọ si ilẹ okeere eleyi to mu ki awọn ma sọrọ pe kii joko sile ṣejọba. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:",0,yoruba "Ó di aago kan, a óò tú kókóo ipa tí ẹ̀rọ ayélujára ayárabíàṣá àti alágbèéká ńkó ní ti ètò ẹ̀kọ̀ọ́. »» @user",0,yoruba "RT @user: Ko fi ile wa se ibugbe lose tuntun yi RT""""""""""""""""@user: Ajé o!""""""""""""""""",0,yoruba "Báyìí, Mo ti ṣetán láti ṣe ìponlogo ìbò fún Tinubu àti àwọn Olùdíje APC- Buhari",0,yoruba "ko si si olukọ kankan ninu awọn yara ikẹkọ lati sisẹ ni ọgba fasiti Ibadan SSANU ni awọn n gun le iyansẹlodi naa nitori ijọba kọ lati bu ọla fun idajọ ile ẹjọ lori ọrọ awọn ile iwe alakọbẹrẹ ti fasiti ati bi ijọba se kuna lati san owo ajẹmọnu awọn osisẹ, lẹyin adehun ti wọn jọ buwọlu. Ajọ naa ni ijọba apapọ ko lati da awọn olukọ ile iwe alakọbẹrẹ ti fasiti ti wọn da duro lẹnu ise pada si ipo. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọrọ pọ ninu iwe kọbọ lori opo Twitter. Ẹnikan woye, o sọ pe ajọ ASUU lo kọkọ bẹrẹ iyanṣẹlodi ki ajọ NASS to bẹrẹ ti wọn. O ni awọn SSANU naa ti wa bẹrẹ ti wọn. O ni afaimọ ki iyanṣẹlodi ọhun ko maa di inu oṣu kọkanla to mbọ ko to pari. SSANU Alao Abiodun tiẹ ni ajọ ASUU ati ASUP n yanṣẹlodi, bakan naa ajọ SSANU ti bẹrẹ ti wọn. O ni to ba ya, NASU naa yoo bẹrẹ tiẹ. Abiodun ni laisi aniani iṣoro nla wa pẹlu eto ẹkọ lorilẹ-ede Naijiria. Gbogbo ènìyàn ló wọ agbádá ikú, ẹni tó kàn lẹnìkan kò mọ̀ Ẹlomiran ni ijọba apapọ ko ni ṣe ohun tile ẹjọ paṣẹ rẹ. O ṣalaye pe Wọn ti gba beeli Sambo Dasuki ati olori ẹsin musulumi Shiite ṣugbọn wọn tun wa lẹwọn ni Kuje. O ni to ba jẹ pe lorilẹ-ede miran ni, ko yẹ ki Aarẹ Muhammadu Buhari ṣe ijọba orilẹ-ede Naijiria rara lẹyin to ditẹ gbajọba lọdun 1983 eyi to mu ifasẹyin ba eto oṣelu Naijiria. Alápinni: Kò sí ẹni to fẹ́ kọ́kọ́ kọ́ iṣẹ́ òṣèré bíi ti àtẹ̀yìnwá Mohammed Ahmed Gorko ni ASUU ati ASUP wa lori iyanṣẹlodi, COESU sẹṣẹ fagile iyanṣẹlodi ti wọn. Ni bayii SSANU ti bẹrẹ ti wọn. O ni o ṣeni laanu pe ẹka eto ẹkọ ti doju keji lorilẹ-ede Naijiria. Ero awọn eeyan sọtọọtọ lori iyanṣẹlodi ti SSANU gunle lọjọ Aje lori opo facebook. Bi awọn kan ti n sọ pe awọn olosẹlu kan lo n lo ajọ awọn oṣiṣẹ ti wọn n daṣẹ silẹ lati ba ijọba to wa lode jẹ, bẹẹ ni awọn miran n sọ pe ijọba Buhari gan an ni ko ṣe ojuṣe rẹ. Ọrọ lori iyansẹlodi SSANU Bayii ti gbogbo olukọ fasiti yari, kini ṣiṣe? Yahaya Yakubu Muhammad ni asiko yii gan an ni ọpọlọpọ oṣiṣẹ fẹran lati maa gun le iyanṣẹlodi nitori idibo to mbọ. Ọrọ lori iyansẹlodi SSANU",0,yoruba "Baàlè joko. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Nitori eyi, ara eni ni nfàn ojú kakaaki.",0,yoruba "RT @user: Aseyi s'amodun """"""""""""""""""""""""""""""""@user: Ẹ kú ọdún tuntun oooo!!!! #2013""""""""""""""""""""""""""""""""",0,yoruba "Idi ni pe Ọlamijuwọnlọ, tii se ọmọ bibi Ọtunba Adebayọ Akala, ti kin baba rẹ lẹyin pe ijọba ipinlẹ Ọyọ ko ni atilẹyin ofin lati yọ oun nipo. Ọlamiju salaye pe ara lo n ta ẹgbẹ APC, nitori pe oun pada sẹgbẹ baba oun, tii se PDP, ti kanselọ mẹrin ninu mẹjọ si wa lẹyin oun. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: O fikun pe awọn eeyan ilu Ogbomosọ nikan lo lee yọ oun nipo, kii se Kọmisana, bẹẹ si ni ko sẹlẹ ri, ki Kọmisana maa bura fun alaga ijọba ibilẹ. O wa fọwọ gbaya pe pe ile ẹjọ ni yoo ba oun ati ijọba ipinlẹ Ọyọ da si ọrọ naa.",0,yoruba @user @user @user Ẹ wá gba fọ́ọ̀mù kẹ́ ẹ forúkọ sílẹ̀ 🙄,0,yoruba yi lo ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa òkè: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba @user Abala ke̟rin. A kò gbo̟dò̟ mú e̟niké̟ni ní e̟rú tàbí kí a mú un sìn; e̟rú níní àti ò wò e̟rú ni a gbo̟dò̟ fi òfin dè ní gbogbo ò̟nà.,0,yoruba Ìlẹ̀ Ọ̀yọ́ jẹ́ ìlú tí ó ga ju lọ nínú Nàìjíríà.,0,yoruba "Ile ise olopaa fẹsun kan Senato Dino Melaye niwaju ile ẹjo giga kan ni Lokoja Eyi waye lẹyin ti ileesẹ ọlọpa Naijiria gbe lọ si ile ẹjọ pe awọn ọdaran meji jẹwọ pe oun ni Baba isalẹ awọn. Melaye kede ọrọ naa loju opo twita re. O ni ''Pabo ni irọ ti ijọba ipinlẹ Kogi ati ile isẹ ọlọpa n pa mo mi yoo ja si. Ase lasan ni. Ọgbon ati dun mọhuru mọhuru mọ mi ni.'' Lọjọ aje ni agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpa, Moshood Jimoh, se afihan awọn afurasi meji kan nilu Lokoja to ni wọn jẹwọ pe Senato Dino Melaye lo ran awọn nisẹ lati wu iwa janduku nipinlẹ Kogi. Saaju igba naa, Dino Melaye ti fesi sọrọ ọga ọlọpa lori aṣẹ to pa pe ki gbogbo awọn ọlọpa to n ṣiṣẹ ẹṣọ lọdọ awọn eeyan pataki lawujọ, to fi mọ awọn oloṣelu ati awọn to di ipo iṣakoso mu jakejado orilẹẹde Naijiria kuro lẹyin wọn ni kiakia. O ti to ọjọ mẹta ti Dino Melaye ati gomina ipinlẹ Kogi, Yahaya Bello ti n sọko ọrọ si ara wọn.",0,yoruba olùparapọ̀ ri pe ṣe iyalẹnu wey ti o tẹ.,0,yoruba "àkerekere, Olùwo ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìṣẹ̀: ti o ní wúlò fún gbogbo.",0,yoruba "Ǹjẹ́ òbìnrín tún le lóyún lásìkò tó wà nínú oyún, kíní sáyẹ́nsì sọ?",0,yoruba "♫ Ewúro làgbà igi oo, ewúro làgbà igi. Gbogbo igi ẹ bọ̀wọ̀ f'ewúro, ewúro làgbà. ♫",0,yoruba Omo Oduduwa tokàn tokàn ...Yoruba ni mi 💯 #yoruba #backtoschool #Arewa #yorubadboi,0,yoruba "Àlááfíà àìnípẹ̀kún á jẹ́ tiwa, òfò, àìní, àìrójú-ráyè, ikú òjijì ti dágbére láyée wa . A kú àyájọ́ ọjọ́ àlááfíà #PeaceDay",0,yoruba ojú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Bàbá lo tun se lọ.,0,yoruba "Patience Jonathan Eyi waye lẹyin abajade idajọ adajọ agba, Mojisola Olatoregun ni ile ẹjọ giga to wa ni ipinlẹ Eko to si paṣẹ pe ki iyawo aarẹ Patience Jonathan lati gbagbe $8.4m àti N9.2b rẹ tori o ti bọ sọwọ ijọba. Ijinigbe: BBC ṣe ìwádìí bí ikọ̀ IRT ṣe ń gbéjà ko awọn ajinigbe lójú Adajọ agba, Mojisola Olatoregun tẹ pẹlẹ mọ ọ pe wọn funra pe owo naa jade latari iwa magomago. Nitori naa, o gba ẹjọ ti ajọ EFCC pe wi pe ki Patience padanu owo naa pata pata. Awọn Iroyin ti ẹ le nifẹ si Idajọ naa sọ ajọ EFCC di ajawe olubori gẹgẹ bi adajọ ṣe ni arabinrin Jonathan ko ni aridaju lati fi han pe ọna to tọ ni oun fi ri owo naa ati idi ti wọn ko fi ni gba owo naa lọwọ rẹ. Ile ẹjọ ni gẹgẹ bi ajọ EFCC ṣe sọ ọ, ọns ti Patience gba ri owo naa lodi si abala ofin ikẹtadinlogun to ni ṣe pẹlu jiji owo atawọn ẹsun mii to fara pẹ ẹ. Ajọ EFCC ti fi aridaju eyi han nipa fifi si oju opo Twitter wọn.",0,yoruba "RT @user: @user @user @user @user @user @user Aku iyedun, Oluwa a fi ire kin ire o. Ase",0,yoruba iṣẹ́ ayin. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "Bí Boko Haram ṣe pa àwọn àgbẹ̀ ní Borno fihàn pé ọ̀rọ̀ ààbò Naijiria n fẹ́ akitiyan si - Bola Tinubu Oloye ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC, Bola Tinubu ti sọ pe bi Boko Haram ṣe pa awọn agbẹ onirẹsi nipinlẹ Borno lọjọ Satide fihan pe igbogun ti awọn agbesunmọmi ṣi nilo akitiyan si ko to o le wa sopin. Ninu lẹta kan ti Tinubu kọ si gomina ipinlẹ Borno, Zulum, lati ba kẹdun iṣẹlẹ naa to waye ni Zabarmani, lo ti sọ eyi. Ko din ni agbẹ onirẹsi mẹtalelogoji ti Boko Haram bẹ lori nibẹ. Ọpọlọpọ eeyan lo si ti bu ẹnu ẹtẹ lu ipaniyan naa. Tinubu sọ pe pipa ti wọn pa awọn agbẹ naa, to n tiraka lati pese fun ẹbí wọn ati oúnjẹ fun orile-ede Naijiria, ko yatọ si iwa ika ati ti Satani. O gboriyin fun Gomina Zulum, fun gbogbo akitiyan rẹ lati ri pe awọn ti ogun sọ di alainilelori, pada si ilu abinibi ati isẹ oojọ wọn. Eyi to ni o ti mu idagbasoke ba ipese oúnjẹ ni Naijiria, ati idunnu ba awọn eeyan naa. Ìdí tí ààrẹ Buhari ṣe padà gbà láti yọjú si ilé ìgbìmọ̀ aṣójú-ṣòfin tórí ọ̀sẹ́ Boko Haram Adari ile igbimọ aṣojuṣofin ilẹ Naijiria, Femi gbajabiamila ti fi lede pe aarẹ Muhammadu Buhari ti gba lati wa siwaju ile aṣojuṣofin bayii. Eyi ko sẹyin ọrọ ikọlu to waye ni ilu Kushebe Zabarmani nibi ti ikọ Boko Haram ti dumbu ọpọlọpọ awọn agbẹ onirẹsi to bẹẹ ti ko tii ni pato onka iye awọn to fori fa iku naa. Ọjọbọ ọsẹ ni Gbajabiamila n sọ fun awọn oniroyin lẹyin to ṣepade kan pẹlu aarẹ ni ile rẹ. Lọjọ Aje ọsẹ ni ile igbimọ aṣojuṣofin Naijiria kọwe pe aarẹ Buhari lati wa wi tẹnu rẹ nipa iṣoro aabo to n koju orilẹede yii. Bakan naa, o tun ṣalaye awọn igbesẹ ti ijọba rẹ n gbe lati fopin si iwa iṣoro yii. Bi ẹ ko ba gbagbe, ikọ Boko Haram latẹnu adari wọn tun ṣẹṣẹ ṣe fidio kan jade ni ninu eyi to ti ṣalaye bi awọn ṣe pa awọn agbẹ naa. 'Ọkọ mi wa ọkọ̀ tẹ ""Poly Bag"" lásán, àfi gbùùàà! Àdó okoró búrẹ́kẹ' 'Boko Haram ti gbilẹ̀ kan nílẹ̀ Hausa, wọ́n ti ń ní ""Check Point"" láti gba owó lọ́wọ́ àwọn àgbẹ̀' Gẹgẹ bi ile igbimọ aṣofin mejeeji ṣe n ke si aarẹ buhari lati da wa wi tẹnu rẹ ati pe ko gba iṣẹ lọwọ awọn ọga awọn ologun tori wọn ni wọn ti kuna ninu iṣẹ wọn. Ile igbimọ aṣofin agba ni tiwọn to tẹnu mọ ọ́ pe ọrọ̀ aje orilẹede Naijiria ti wa di akurẹtẹ gbaa to bẹẹ to fi jẹ wipe awọn Boko Haram ti n gbe nkan di ọna lawọn apa ibi kọọkan ni Borno. Awọn ibudo yii ni wọn ti n da awọn agbẹ to n lọ si oko duro lati maa gba owo lọwọ wọn"". Tori eyi wọn ni dandan ni ki aarẹ ṣe atunto ẹka abo ni Naijiria. Igba kẹta ree ti ile aṣofin n funpe si aarẹ Buhari lati yọ awọn ọga awọn ologun. Titọ yii n jẹ jade latari awọn agbẹ onirẹsi tawọn Boko Haram dumbu bi ẹran ni Borno ti ko si tii si ojutuu. Wo bí ìlànà tuntun lórí gbígba físà UK lẹyìn Brexit ṣe kàn ọ́ Abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 ti Pfizer ṣe yóò di lílò láti ọ̀sẹ̀ tó ń bọ̀ Àwọn afurasí ṣá ìgbákejì kọmísọ́nà ọ̀gá ọlọ́pàá láàké dójú ikú 'Ọkọ mi wa ọkọ̀ tẹ ""Poly Bag"" lásán, àfi gbùùàà! Àdó okoró búrẹ́kẹ' Niṣe lawọn ọmọ ile igbimọ aṣoju-ṣofin l'Abuja ti ke si Aarẹ Muhammadu Buhari lati wa ṣalaye ibi ọrọ de duro nipa eto abo orilẹ-ede Naijiria. Wọn gbe igbesẹ naa lẹyin ti awọn aṣoju lati ipinlẹ Bornu da aba pe o yẹ ki Aarẹ Buhari yọju si ile ọhun. Bi ẹ ko ba gbagbe, opin ọsẹ to kọja yii ni awọn ọmọ ẹgbẹ Boko Haram dumbu eeyan mẹtalelogoji bi ẹni dumbu ẹran ninu oko irẹsi kan ni ipinlẹ naa. Ṣaaju ni ariyanjiyan ti kọkọ waye laarin awọn ọmọ ile igbimọ aṣoju lori boya ki wọn ke si Aarẹ tabi ki wọn ma ṣe bẹẹ. Eyii to mu ki agbẹnusọ ile naa, Femi Gbajabiamila parọwa si awọn eeyan ọhun pe ko bojumu lati ke si Aarẹ lati wa tu aṣiri igbesẹ ti ijọba n gbe lori eto abo, nitori ko le so eso rere. Ṣugbọn awọn kan ninu ile naa faake kọri pe ko si ohun to buru ninu ki Aarẹ wa ṣo fun awọn ọmọ Naijiria awọn ohun to n ṣe lori eto abo ẹmi ati dukia wọn. Lẹ́yìn ọ̀pọ̀lọ́pọ̀ oṣù tí òjò kò rọ̀ ní orílẹ̀èdè Cuba, Ọba ilẹ̀ Yorùbá ló Ṣugbọn lẹyinorẹyin, ọkan lara awọn to daba pe ki wọn pe Aarẹ, Ahmed Jaha ni o ti di ọranyan ki Aarẹ yọju sile naa, ti awọn aṣoju miran si ṣegbe lẹyin rẹ ki gbogbo ile to gba aba ọhun wọle. Bo tilẹ jẹ pe ile igbimọ aṣoju naa fọwọ si pe ki Aarẹ wa wi tẹnu rẹ lori eto abo Naijiria, wọn ko tii sọ ọjọ ti Aarẹ yoo wa. Ọjọ Satide, ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu Kọkanla, ọdun 2020 ni awọn ọmọ ẹgbẹ Boko Haram ṣekupa awọn eeyan mẹtalelogoji lagbegbe Marrabati ati Hammayya, lẹba ijọba ibilẹ Jere, ni ipi9nlẹ Bornu. Wo ohun tí wọ́n sọ nípa Owa Ale ìlú Ikare, Ọba Samule Kolapo Adegbite Adedoyin tó wàjà",0,yoruba "Olùwo fi. Nitori eyi, ara eni lo ni àṣà ìdílé lo je ti ibile.",0,yoruba Ààmì ìdánimọ̀ orílẹ̀ èdèe Jamaica tí Kanye West lò di awuyewuye tí ó dá fìrìgbagbòó lórí ‘ìsààmì’,0,yoruba o lẹ. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọba lo ni ìgbà àkerekere ni nfàn ojú kakaaki.,0,yoruba "lálai. Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "owó àkokò, Alàji lo ni ìgbà mi owó àkokò, Ọmọ lo ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba "kakaaki. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbfi yóò ni Nitori eyi, ara eni lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò.",0,yoruba ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí gbogbo ènìyàn gbọ́dọ̀ kọ̀ láti rí ìdìsẹ̀ àti àlàáfíà.,0,yoruba Bojúbojú ni èmi kà á sí wípé Abọ́bakú rọ́ gbẹ́. Àwọn kan ló wà nídìí ìròhìn irọ́. #AbobakuOoni #Yoruba,0,yoruba ọ̀rẹ́ẹ̀ mi nathan lugo kú iṣẹ́ mo rí ọ o àwọn alálẹ̀ yóò gbè ọ́ o,0,yoruba ta ló sọ wí pé a kò ní ọ̀rọ̀ìperí fún rubber lédè a kúkú ní àwọn ènìyàn kò mọ̀ ọ́n ni yálà kí a pè é ní irẹ́,0,yoruba Ọkan tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà.. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba ìbàdandun ìlú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba "ỌDÚN IFÁ ma ń wáyé ní ọ̀sẹ̀ àkọ́kọ́ nínú oṣù Òkúdù, èyí tí ó jẹ́ ìbẹ̀rẹ̀ Ọdún Tuntun fún àwọn Yorùbá. Ọdún Ifá ọdọọdún ma ń ní odù tí ó jáde rẹ̀.",0,yoruba "Omoluabi wa ni ọrọ̀ àìmọ́ lo je ti ibile. Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.. Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba "Odídẹrẹ́ tí kìí kú s'óko ìwánkanjẹ, yó kó èrè oko délé.",0,yoruba Ọ̀gọ̀rọ̀ ló wá láti àwọn Ìlú Gúúsù Aṣálẹ̀ Sahara .,0,yoruba Àwọn ẹ̀kọ́ dídì yìí ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìwà: ti o nuni ti o pataki.,0,yoruba kí ni èròo tì rẹ nípa ìjókòó àpérò gbogboògbò nàìjíríà tó ń bọ̀ lọ́nà,0,yoruba "Ní nígbà àkerekere, Olùwo ri Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba àdán da orí kodò ó ń wo ìṣe ẹyẹ,0,yoruba "Àmọ́ bí kò bá sí igi nínú igbó mọ́, ẹ̀dá ọmọ ènìyàn yóò há ṣe máa gbé ilé ayé? Èyí ni ó fi yẹ kí gbogbo wa ó gbáríjọ pọ̀ lọ́wọ́ sí ìràpadà igi orí ilẹ̀, kí oníkálukú ó gbin igi sí àdúgbò rẹ. Ó lè jẹ́ igi ọsàn, àgbọn tàbí igikígi tí ó ń ṣíjì bo'ni. #OyiEedu",0,yoruba Ẹ̀ka-èdè Yorùbá Oǹdó àti apá kan ní Ọ̀yọ́. #idahun #Ibeere #Yoruba https://t.co/buSqnXvIpl,0,yoruba Ẹ̀yìn ìgbà tí a dá ihò lu sí kọ́ìnsì penny ni a tó gbà á. Okùn ni à ń sín in sí bí owó-ẹyọ. #OwoEyo #Yoruba,0,yoruba Àhesọ nípa egbògi àjẹsára agbógunti àrùn rọmọlápárọmọlẹ́sẹ̀ fọ́n ká sí ìgboro .,0,yoruba Àwọn ìsàmúlò-ètò tí kò bá àwọn ọ̀wọ́ mìíràn mu,0,yoruba "Ó sọ ìdí tí ó fi rọrùn fún erin láti máa gbé pẹ̀lú àwọn ènìyàn àmọ́ , lẹ́yìn ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìran , wọ́n gbàgbé ìpìlẹ̀ wọn , wọ́n lọ ń gbé nínú igbó .",0,yoruba 'Owó ara ęni l'àá fí ń túnwà ęni se' One's hand is the best tool for fixing ones life. #Yoruba proverb #Orisha #Ori #healing #spirit,0,yoruba "RT @user: """"""""""""""""@user: Óyá mó ti dá'mi sí wájú, kí ng wá máa tẹ'lẹ̀ tútù."""""""""""""""" Atepe lese te ona, ki ajinde ara ma je o",0,yoruba Ó tẹ̀síwájú pé wọ́n tún leè lo àwọn irinsẹ́ àti ohun èlò ọ̀hún fún gbígbé àwọn aláìsàn ààrùn COVID - 19 tó bá nílò ìtọ́jú ní kíákíá .,0,yoruba Ń sọ ní pàtó oye ìdádúró ọ̀kẹ́-ìṣísẹ̀ lẹ́yìn tí atọ́ka náà ti jáde lágbègbè náà kí pánẹ́ẹ̀lì tó di pípamọ́. Ìgbà tí bọ́tìnì ìpamọ́_aládàáṣe bá jẹ́ òótọ́ nìkan ni bọ́tìnì yìí wúlò.,0,yoruba iba ò ní pa wá o gt,0,yoruba Ohùn kan lójú oorun ló ní kí n gbàdúrà fún Tinubu ní ìhòhò- Olaiya Igwe,0,yoruba ènìyàn yì í tún ṣe àwọn iṣẹ́ tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Bàbá lo ni ẹ̀ká àwẹ eyti o gbe lori àìmọ́ kọ.,0,yoruba Mo wọ ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò kan tí @user ṣe fún ọ̀kan lára àwọn #Bokoharam ní #Abuja. #BringBackOurGirls http://t.co/JxmdS89tUu,0,yoruba "nípa àìmọ́. Nitori eyi, ara eni lo ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.",0,yoruba "Zamfara INEC ti kéde pé àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ló jáwé olúbori nínú ìdìbò 2019 Ǹkan ti àjọ eleto ìdìbò ṣe ni pé wọn tẹ̀lé ìdájọ ilé ẹjọ to ga julọ tó jẹjọ náà ni ọjọ jimọ, èyí to sọ pe ìbò ẹgbẹ́ òṣèlú APC ni ]ipínlẹ̀ náà ko fẹsẹ múlẹ̀ ni ìpínlẹ̀ náa. Bode George: òòtọ́ ni ìkìlọ̀ Obasanjọ ati Soyinka Ọ̀gá àgbà àjọ INEC ọjọgbọ́n Mahmood Yakubu to kede ìjáwe olubori ọhun sàlàye pe ìjẹjọ ilé ẹjọ to ga jùlọ to wáye ni àná ọjọ Jimọ ló mu ki àwọn yí ìkédé ẹni to jáwe olúbolri páda kuro ni APC ti àwọn ti kede tẹlẹ si PDP. Ọ̀gá Yakubu sọ pé àjọ INEC yóò fún gbogbo wọn ni ìwé èrí ní ọjọ ajé ti ṣe ọjọ kẹtàdinlọgbọ̀n oṣù kàrún ọdun 2019. Lásìkò ìkéde yìí alága INEC kéde Bello Muhammad Mutawalle to jẹ olùdíje PDP fun gomina gẹ́gẹ́ bi ẹni to jáwe olúbori ní Zamfara. Ní ti ilé ìgbìmọ aṣòfin àti ilé ìgbìmọ aṣofin ìpínlẹ̀ ti ko mu wahala dani, bio se ti gomina, A ni láti wo àwọn ti o pọ jùlọ tó si jẹ Bello Mutawalle lo jáwe olubori. Alaga INEC sàlàye pé lẹ́yin ti àwọn ti fi gbèdèke fún ìdìbò abẹlé APC ti wọn o si mu èsì ìdìbò abẹle ti won wa ni àwọn o fi ka wọn kún ti wọn si gbe ẹjọ lọ si ilé ẹjọ.",0,yoruba "èwe. Nitori eyi, ara eni lo ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba nìlẹ̀̀ní sáàrí ti nípa ìtànká àti ire ènìyàn.,0,yoruba Hebrew (IS_O-8859-8-I),0,yoruba "... Ọ̀nà Ìsokùn (Baba oyè Aláàfin), Àrẹ̀mọ̀ àti Alápìn-ín-ni òòṣà. #Yungba #EwiAlohun #Yoruba #Oyo",0,yoruba "Ní ìlú kan, Ọmọ ni olùkó. ìrìn ìròyìn. Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba "ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "Ileeṣẹ ọlọpaa ni ko wa sọ tẹnu rẹ idi to ṣe fi kamẹra CCTV sinu yara tawọn alejo n gba. Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun, Abimbola Oyeyemi ṣalaye pe ilu Eko ni ẹni to ni ile itura naa to wa ni Odogbolu n gbe. Amọ, Ọgbẹni Oyeyemi sọ pe ọga DPO ilu Odogbolu ti sọ fun un pe ko wa sọ idi to ṣe fi kamẹra sinu yara tawọn eeyan n gba. O ni iwadii si n lọ lọwọ lori ẹsun pe ile itura ọhun n ṣe ayọjuran si ohun tawọn alejo ba n ṣe ninu yara ti wọn ba gba. Ọrọ naa bẹrẹ nigba ti alejo kan nile itura naa fi fidio to ya nibẹ lede lori ayelujara ninu eyi to ti ṣalaye pe wọn fi CCTV sinu awọn yara to wa nibẹ eleyi to lodim sofin. Big breast: Oluwatosin Adegboro, Oluwaseun Amoo, Remi Fatolu: Ẹlòmíì ń fi irú ọyàn wa tọrọ Ọkunrin naa sọ ninu fido ọhun pe ninu yara marun un lawọn ti ri iru kamẹra bẹẹ. O ni awọn kamẹra yii ti maa ka ihoho burọda ati mama oun. Ọrọ yii ti di iṣu ata yan-an yan-an lori ayelujara debi pe awọn ilumọọka naa da si ọrọ naa pe ileeṣẹ ọlọpaa ni lati ṣe iwadii iṣẹlẹ naa. Ó lódì sí òfin kí ilé ìtura fí 'camera' sí inú yàrá tí àwọn ènìyàn wà- Irukera FCCPC Ijọba orilẹ-ede Naijiria ti ni o lodi si ofin ti awọn eniyan ma tẹlẹ aṣẹ to de asiri awọn eniyan. Ọga Agba ileeṣẹ Federal Competition and Consumer Protection Commission (FCCPC), Babatunde Irukera lo sọ bẹẹ lasiko to n fesi si iṣẹlẹ bi ile itura kan ṣe fi ẹrọ amohunmaworan si inu awọn yara to wa ninu ile itura naa. Irukera ni awọn ọmọ Naijiria ni aṣẹ si aṣiri wọn (Privacy) ti ko si tọna ki ẹnikẹni tu aṣiri wọn sita. Amọ, o fikun wi pe o ṣeeṣẹ ki o ni awọn igba kọọkan ti ijọba le tẹ oju ofin yii mọlẹ, amọ ijọba nikan lo laṣẹ lati ṣẹ bẹẹ. Ọga Agba ileeṣẹ Federal Competition and Consumer Protection Commission (FCCPC), Babatunde Irukẹra fikun wi pe iwadii ti bẹrẹ ni pẹrẹwu lori iṣẹlẹ naa. Saaju nigba ti a fi iroyin naa lede ni awọn eniyan ti ṣe lodi sii loju opo BBC Yoruba. Koda, awọn ero ti sọ riṣiriṣi nipa eyi ni awọn oju opo ayelujara Ṣé o tọ̀nà kí ilé ìtura máa fi 'Camera' sí iyàrá ìbùsùn àwọn àlejò? Njẹ o tọ ki ile itura fi ''camera'' si iyara ibusun awọn alejo? Awọn alejo ile itura faraya nitori camera ti wọn ri ni iyara ibusun wọn Ile itura kan ni ipinlẹ Ogun ti ko ibinu awọn alejo to wa sun nibẹ nitori bi wọn ti sefi ẹrọ ayaworan si inu iyara ibusun awọn alejo naa. Ninu fọnran fidio kan ti a ri loju opo ayelujara ni akara ọrọ yi ti tu sepo. A ko le fidi ọrọ naa mulẹ lori asiko ti wọn ya fọnran naa tabi ibi ti wọn ti ya fidio yi sugbọn pẹlu ohun ti awọn to wa ninu rẹ n sọ. Nise ni awọn eeyan kan n faraya pẹlu bi ile itura yi ti se fi 'camera' pamọ sinu iyara wọn. Mckinley Erves di ẹni tọ ń ríran rí aàwọ̀ nípasẹ̀ ìrànlọ́wọ́ ọ̀rẹ́ rẹ̀ Awọn kan n sọ pe ile itura ti wọn ti ya fidio yi wa ni Ayepe ni ijọba ibilẹ Odogbolu., ni ipinlẹ Ogun ni Guusu Iwọ oorun Naijiria. Wọn ko kọ asiko ti wọn ya fidio naa tabi orukọ ẹni to ya a ki wọn to bẹrẹ si ni se alabapin rẹ kaakiri. Kini kan to daju ninu fọnran naa ni pe awọn kan ti wọn jọ ẹni to ni ile itura yi n fidi rẹ mulẹ pe awọn lẹtọ lati fi fidio sinu iyara awọn alejo to wa sibẹ. Koda, a gbọ ninu fidio naa nibi ti arakunrin kan (ẹni to seese ko ni ile itura naa) ti n sọ pe awọn lẹtọ lati fi ẹrọ kamẹra sinu iyara awọn alejo. Ohun to fa ki awọn eeyan maa gba ọrọ inu fọnran yi bi ẹni gba igba ọti ni pe ọkan lara awọn alejo n faraya pe erọ kamẹra to wa ni ibusun awọn ko bikita asiri bibo fun awọn. Tolulope Adeleke Aire: Mo wòye pé àwọn ọkùnrin Nàìjíríà kò fi bẹ́ẹ̀ mọ̀ nípa ìtọ́jú ọmọ tu Bi ọrọ yi ba fi le de iwaju adajọ, o seese ki wọn fi iya jẹ awọn ti ko bikita lati maa ya awọn eeyan laigba iyọnda lọdọ wọn. Titi di bi ase n ko iroyin yi jọ, a ko ri akọsilẹ pe awọn to fi fidio yi sita ti fẹjọ sun awọn ọlọpaa.",0,yoruba _Tún orúkọ sọ...,0,yoruba "Adajọ Okon Abang da ẹjọ naa lọjọ iṣẹgun ọsẹ lori ẹsun siṣe owo maku-maku ati yiyi owo da si tir ti gbogbo rẹ to irinwo miliọnu naira. Bakan naa, adajọ paṣ pe ki ileeṣ Olisa Metuh, Dextra investment san faani miliọnu mẹẹdọgbn naira ni ibamu pẹlu ẹsun ikarun ati ikẹfa ti wọn si paṣẹ pe ki Olisa Metuh funra rẹ san faani ọọdunrun le marunlelaadọrin miliọnu naira. Ile ẹjọ giga niluu Abuja ri aridaju pe Ọgbẹni Olisa Metuh jẹbi gbogbo ẹsun ti wọn fi kan an lori owo irinwo miliọnu naira pe o gba lọwọ Sambo Dasuki laye ijoba Jonathan. Ninu ẹjọ naa ti adajọ Okon Abang ti ile ẹjọ giga ni ilu Abuja da, wọn ni Ọgbẹni Olisa Metuh jẹbi ẹsun ti ajọ EFCC fi kan an. Ajọ EFCC fi ẹsun meje tan yanyan kan Metuh ti o jẹjọ papọ pẹlu ile iṣẹ rẹ, Destra Investment. Ṣe ni Olisa Metuh rin wọ inu ile ẹjọ bi ẹni ti ko ni iṣoro kankan, ẹwẹ ko tii mọ iru idajọ ti yoo gba lonii. Awọn igba ti Olisa Metuh ti foju ba ile ẹjọ ri Wọn fi ẹsun kan agbẹnusọ ẹgbẹ oṣelu PDP tẹlẹri yii lórí iye owo to to irinwo miliọnu naira (N400,000,000). Atoun ati ile iṣẹ rẹ, Destra Investment ni ẹjọ yii kan eyi to nii ṣe pẹlu ẹsun meje ọtọtọ lori yiyi owo ti o gba lọwọ olugbaninimọran lori ọrọ abo tẹlẹ ri, Ogagun Sambo Dasuki si tirẹ. Ninu aworan isalẹ yii, iyalnu lo jẹ lọjọ yii to yẹ ki Olisa Metuh fara han nile ẹjọ ti gbogbo eeyan si dede ri i lori ibusun alaarẹ ati ike iwosan lọrun rẹ. Bakan naa, wọn fi ẹsun kan Metuh lori iye owo miliọnu meji dollar kan ti ko gba banki kankan kọja rara eyi si ni ajọ EFCC ni o lodi si ofin. Ninu oṣu karun ọdun 2018, lasiko ti igbẹjọ n lọ lọwọ, ṣaa dede ni agbẹnusọ fun ẹgbẹ oṣelu PDP tẹlẹ ri, Olisa Metuh ṣubu yakata silẹ nigba ti wọn pe e to fẹ maa rin lọ sinu koto ijẹjọ to si fa ariwo hee nile ẹjọ. A gbọ pè aisan to n ba a finra ni ṣe pẹlu ifarapa egungun ẹyin to si ti mu u farahan nile ẹjọ lọpọ igba lori ibusun alaisan. Gbogbo igbiyanju lati jẹ ki wọn sun igbẹjọ rẹ siwaju ko baa le lọ fun itọju loke okun ni ile ẹjọ ko gba rara. Ninu oṣu kinni ọdun 2016, Metuh ni oun ko jẹbi awọn ẹsun ti wọn fi kan an.",0,yoruba RT @user: Oníṣẹ́-ìròyìn ní Nàìjíríà: 1.Agbébọnrìn pa Lawrence Okojie ń Benin ń'nú oṣù Agẹmọ 2017. 2.Ọmọẹgbẹ́ ọkùnrin 7 dìgbòlu oníròyìn…,0,yoruba "Gbajugbaja oṣere, Ganiu Nafiu ti gbogbo eeyan mọ si Alapinni Ooṣa sọrọ nipa idojukọ ti ẹgbẹ oṣere n koju lori ayederu ẹda fiimu ti wọn n pe ni 'Piracy'. O ba BBC Yoruba sọrọ lori ọna ti àwọn àsáwọ̀ oṣere ṣe n wọ agbo wọn nigba ti BBC Yorùbá n fọrọ waa lẹnu wo ni Port Novo lorilé-ede Bẹnin Republic. O ni ijọba Naijiria kò ba àwọn oṣere ja ija naa bi o ti yẹ pe ohun lo faa ti onikaluku fi n dọmu iya rẹ gbe. Alapinni Ooṣa ṣalaye ipa pataki ti àwọn baba nla tiata bii Hubert Ogunde ko nigba aye wọn ni eyi ti o fi jẹ pe kikọ ni mímọ̀ ni wọn n fi ọrọ iṣẹ ere ori itage ṣe ni akoko naa. O kilọ wiwa òkìkí ti àwọn àsáwò inu ere tiata kọọkan n wa lasiko yii fun wọn. Alapinni rọ awọn eniyan ki wọn farabalẹ kọ iṣẹ ti wọn ba yan laayo ki wọn le di agba ọ̀jẹ̀ nibẹ koda ko ṣe iṣẹ tiata. Bakan naa lo parọwa pe ki gbogbo eeyan sọ ogun ayederu ẹda nkan ti a mọ si 'Piracy' di ogun àjùmọ̀jà.",0,yoruba Ó kùnà láti ka fáìlì sáà tí a fi pamọ́ %s: %s,0,yoruba "agbègbè tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "yorubá lo ni ìgbà mi owó àkokò, Ọba lo mú.",0,yoruba yóò ní è̟tó̟ sí ìbò kan s̟os̟o tí a dì ní ìkò̟kò̟ tàbí nípasè̟ irú o̟ nà ìdìbò mìíràn tí ó bá irú ìdìbò bé̟è̟ mu,0,yoruba "Ọpọlọpọ awọn onigbagbọ ninu oriṣa iṣẹmbaye ni wọn ri awọn orisa yii gẹgẹ bi ọlọrun wọn. Wọn gbagbọ wi pe awọn orisa yii ṣiṣ̣ẹ pọ fun ara wọn ni, amọ wọn ki n ṣe nkankan naa lati ọdọ Olodumare to ran wọn wa si ile aye. Ohun tí ìyàwó Adeboye ṣe ní ìgbà akọkọ tó fojú hàn lẹ́yìn ikú ọmọ wọn Dare Pasítọ̀ Dare, ọmọ́ Pásítọ̀ Adeboye ti dágbére fáyé Ìyá àláwo tó di àjíhìnrere òjijì fi àwọn òrìṣà rẹ̀ ṣe ẹlẹ́yà 'Ẹ kálọ sí ìlú mi'... Ètò ńlá tó bẹ̀ sílẹ̀ kìjà lórí BBC Yorùbá Paapaa wọn ni igbagbọ wi pe awọn orisa yii dabi angẹli tabi iranṣẹ olodumare ti awọn eniyan ma n pe ni igba iṣoro. Lara awọn orisa naa ni Esu, Ogun, Ọbatala, Yemọja, Osun, Sango ati Ọya, ti wọn pe ni Ọrumila. Esu In ilẹ Yoruba, awọn ̣elẹsin ibilẹ gbagbọ wi pe esu jẹ oriṣa to lagbara pupọ, to si jẹ iranṣẹ laarin aye ati ọrun, to fi mọ agbede meji. Oun si ni ọkan lara awọn orisa ti o ma n tọ awọn oku sọna lẹyin ti wọn papoda. Wọn gbagbọ wipe esu ni a n ke pe ti ohun ba daru, ti eniyan si n wa ọna abayọ tabi ojutu si nkan to wọ. 'Èṣù kìí ṣe sàtànì bí ẹ ṣe máa ń pè é' Bakan naa ni wọn ri ẹmi esu gẹgẹ bi orisa alarekereke, to ṣeeṣe ko tan eniyan jẹ. Awọn aṣọ pupa ati dudu ni o jọ mọ orisa yii, ti wọn si n lo ata wẹwẹ, taba mimu ati ounjẹ gbigbona lati fi bọ oriṣa yii. Ogun Ogun jẹ orisa akunlẹbọ ti wọn gbagbọ wi pe oun ni ẹni keji to lagbara julọ ninu awọn orisa meje to ku. Ogun ti gbogbo eniyan mọ pẹlu irin, ni o ma n ṣiṣẹ iwosan to si jọba lori gbogbo ohun ti a fi irin da. Awọn ẹlẹsin ibilẹ gbagbọ wipe abiyamọ tootọ ni Ogun, ti o ma n ṣe atilẹyin fun ọmọde ati idile. Oun si ni wọn n pe lati bura tabi rin irinajo. Wọn gbagbọ wi pe oriṣa kan ti kii sinmi ni Ogun jẹ, to si ma n fi ẹjẹ wẹ bi omi. Amọ, ẹnikẹnị ti ẹjẹ ba n yọ ni ara rẹ ko gbọdọ sunmo idi oriṣa Ogun. Lati bọ Ogun, wọn ma n lo ewe ni ẹba titi, irin, ẹjẹ, awọn ohun ija, ẹran, ogogoro ati bẹẹ bẹẹ lọ. Ọbatala Ọbatala jẹ ọkan lara awọn orisa meje ti o tutu pẹlu ẹbun itusilẹ ati alaafia. Amọ, oun ni awọn oloriṣa gbagbọ wi pe o ma n da awọn eniyan ti ko pe, paapaa awọn akanda eniyan. Ọbatala ni o ni suuru julọ laarin awọn ẹmi meje yii, to si ma n ṣe idajọ ododo. Oriṣa yii fẹran awọn eniyan ti kii ṣe alara gbigbona, ti wọn si le e ko ara wọn ni ijanu. Aṣọ funfun ni a mọ pẹlu Ọbatala, ti o si ma n ṣiṣẹ iwosan fun awọn to ba ni ailera, paapaa awọn akanda ẹda. Bẹẹ si ni Ọbatala kii gba oṭi kikan rara, yatọ si omi, miliki, ṣuga, ọgẹdẹ ati bẹẹ bẹẹ lọ. Yemọja Yemọja jẹ obinrin lara awọn orisa meje to di ile aye mu, to n gbe ninu omi, to si n jọba lori gbogbo omi nla nla. Yemọja to jẹ ẹja nla ninu odo ni ibatan Osun to jọba lori awọn omi kekeke. Awọn ẹlẹsin ibilẹ gbagbọ wi pe olupese ni Yemọja, to n pese ọmọ to si n fun awọn eniyan ni ohun meremere ninu omi, amọ o si le e fa ibinu yọ bi ẹkun omi tabi iji lile. Lailai, Ọya ati Yemọja kii ṣe ọrẹ nitori naa wọn kii gbe wọn si ibi kan naa. Awọn arinrinajo lori omi ma n bọ lẹba odo, ki wọn to bẹrẹ irinajo wọn, ki o le lo ni irọwọ-rọsẹ. Ọsun Oriṣa akunlẹbọ yii ni awọn ẹlẹsin ibilẹ gbagbọ wi pe o jọba lori awọn omi kekeke, to si jẹ ibatan Yemọja. Ọsun ni wọn ma n bọ ti wọn ba n wa nkan ayọ, paapaa ọmọ tuntun jojolo. Ọsun kii tete binu, amọ ibinu rẹ ko sunwọn rara. Awọn eroja ti wọn fi n sin Osun ni omi, miliki, oyin ati bẹẹ bẹẹ lọ. Ṣango Ṣango jẹ ọkan lara awọn oriṣa to gbona jainjain, ti si n rọjo ina ti irin ba koju irin. Ṣango ni awọn ẹlẹsin ibilẹ gbagbọ wi pe o jẹ Ọya ati Ọsun. Ṣango ati Ogun kii ri ara wọn soju nitori wọn kii ṣe ọrẹ nitori ọta ara wọn ni wọn n ṣe. Ṣango ni o ma n ṣe idajọ nipa lilo mọnamọna, ti kii si jẹ ki ibi ṣẹlẹ si awọn ọlọlufẹ rẹ, to si fẹran obinrin, orin ati igbadun. Ọya Ọya lo kẹyin ninu awọn oriṣa meje to lagbara julọ lagbaye, ti wọn si ma fi n rọpọ orunmila nigba miran. Awọn ẹlẹsin ibilẹ gbagbọ wi pe obinrin to rẹwa ni ti o si wa ninu omi pẹlu agbara lati ṣiṣẹ iwosan ati ọmọ bibi. Eewọ ni lati pe oriṣa Ọya, Yemọja ati Ọsun papọ lẹẹkan naa, nitori ọta ni wọn, wọn kii ri Ọya soju, afi ti ẹ ba n pe awọn oriṣa mejeeje papọ ni igba kan naa.",0,yoruba "Èyí ni apá kejì ìròyìn nínú àkọsílẹ̀ ẹlẹ́ka méjì lórí ọ̀rọ̀ ìkórìíra ẹ̀yà lórí ayélujára , ìròyìn ayédèrú àti ìsọkiri lásìkò ìdìbò ọdún - un 2019 lórílẹ̀ - èdèe Nàìjíríà .",0,yoruba "Ajọ eleto idibo nilẹ wa ti kede esi idibo gomina nipinlẹ Osun to waye lọjọ Satide, ọjọ Kẹrindinlogun osu Keje ọdun 2022. Ẹni to bori eto idibo naa ni Sẹnatọ Ademola Adeleke tii se oludije fun ipo gomina labẹ asia ẹgbẹ oselu PDP. Adeleke lo ni apapọ ibo 403,371 eyi to mu ko fi ẹyin gomina to wa lori aleefa janlẹ, eyiun Adegboyega Oyetola. Oyetola lo ni apapọ ibo 345,027 ninu esi ibo naa. Oludije fun ẹgb oselu Labour, Lasun Yusuff lo se ipo keẹta ninu esi ibo naa pẹlu apapọ ibo 2,709. Oludije fun ipo gomina labẹ asia ẹgbẹ oselu SDP, Goke Omigbodun lo se ipo Kẹrin ninu eto idibo naa. Alakoso eto idibo naa, Oluwatoyin Temitayo Ogundipe lo kede esi ibo naa fawọn akọroyin. PDP bori ninu esi idibo Guusu ilu Ede PDP bori ninu esi idibo Guusu ilu Ede A 38 APC 5704 LP 16 PDP 19438 SDP11 Accredited voters 12007 A 37 APC 5649 LP 09 PDP 5860 SDP 03 Valid votes 11795 Rejected votes 212 Total votes cast 12007 Ilesha East Reg voters Accredited voters 26179 A 91 APC 13452 LP 33 PDP 10969 SDP 32 Valid votes 25342 Rejected votes 804 Total votes cast 2614 Osogbo LG Reg voters 142459 Accredited voters 56020 A 395 APC 22952 LP 79 PDP 30401 SDP 62 Valid votes 54997 Rejected votes 945 Total votes cast 55942 Atakunmosa west Reg voters 36470 Accredited voters 15171 A 75 APC 6601 LP 13 PDP 7750 SDP 11 Valid votes 14794 Rejected votes 353 Total votes cast 15147 Ifelodun Reg voters 80021 Accredited voters 34860 A 65 APC 16068 LP 18 PDP 17107 SDP 12 Valid votes 34036 Rejected votes 792 Total votes cast 34828 Ilesa west Reg voters 71001 Accredited voters 26364 A 106 APC 10777 LP 40 PDP 13769 SDP 21 Valid votes 25403 Rejected votes 881 Total votes cast 26284 Ilesa west Reg voters 71001 Accredited voters 26364 A 106 APC 10777 LP 40 PDP 13769 SDP 21 Valid votes 25403 Rejected votes 881 Total votes cast 26284 Ayedire Reg voters 37092 Accredited voters 17284 A 1510 APC 7868 LP 7 PDP 7402 SDP 4 Valid votes 17094 Rejected votes 253 Total votes cast 17267 Odoọtin Reg voters 66866 Accredited voters 28864 A 170 APC 13482 LP 19 PDP 14003 SDP 12 Valid votes 28105 Rejected votes Total votes cast Boripe Reg voters 66866 Accredited voters A 91 APC 21205 LP 4 PDP 7595 SDP 9 Valid votes 29510 Rejected votes 598 Total votes cast 30108 Obokun Reg voters 53267 Accredited voters 24447 A 26 APC 9727 LP 11 PDP 13575 SDP 4 Valid votes 23813 Rejected votes 586 Total votes cast 24399 Orolu Reg voters Accredited voters 21182 A 69 APC 9928 LP 32 PDP 10282 SDP 9 Valid votes 20765 Rejected votes 413 Total votes cast 211 Olorunda LG Reg voters 104700 Accredited voters 42009 A 208 APC 18709 LP 63 PDP 21350 SDP 46 Valid votes 41187 Rejected votes 737 Total votes cast 41924 Ife North LG Reg voters 58672 Accredited voters 21774 A 74 APC 9964 LP 34 PDP 10359 SDP 9 Valid votes 21050 Rejected votes 650 Total votes cast Ifedayo LG Reg voters 19598 Accredited voters 10300 A 55 APC 5016 LP 1 PDP 4730 SDP 0 Valid votes 9912 Rejected votes Total votes cast 10036 Ife Central LG Reg voters 113232 Accredited voters 33453 A 202 APC 17880 LP 134 PDP 13532 SDP 50 Valid votes 32544 Rejected votes 865 Total votes cast 33409 Irẹpodun LG Reg voters 57712 Accredited voters 29913 A 63 APC 12122 LP 1886 PDP 14369 SDP 6 Valid votes 29032 Rejected votes 544 Total votes cast 29576 Oriade LG Reg voters 69651 Accredited voters A 60 APC 14189 LP 24 PDP 15947 SDP 21 Valid votes Rejected votes 806 Total votes cast 31747 Olaoluwa LG Reg voters 37149 Accredited voters 18217 A 35 APC 9123 LP 12 PDP 7205 SDP 14 Valid votes 16737 Rejected votes 455 Total votes cast 1719 Ayedade LG Reg voters 37149 Accredited voters 1821 A 229 APC 14527 LP 20 PDP 13380 SDP 10 Valid votes Rejected votes 692 Total votes cast 29680 Iwo LG Reg voters Accredited voters A 214 APC 17421 LP 32 PDP 16914 SDP 20 Valid votes 35634 Rejected votes 897 Total votes cast Ede South LG Reg voters 54872 Accredited voters 26306 A 38 APC 5704 LP 16 PDP 19438 SDP 11 Valid votes 25691 Rejected votes 546 Total votes cast 26237 Isokan LG Reg voters 53288 Accredited voters 23051 A 23 APC 10833 LP 17 PDP 10777 SDP 8 Valid votes Rejected votes 634 Total votes cast 2298 Ejigbo LG Reg voters 73750 Accredited voters 34387 A 67 APC 14355 LP 30 PDP 18065 SDP 17 Valid votes Rejected votes Total votes cast Ede North LG Reg voters 71748 Accredited voters 34735 A 61 APC 9603 LP 15 PDP 23931 SDP 14 Valid votes Rejected votes Total votes cast Egbesore LG Reg voters Accredited voters A 105 APC 9228 LP 41 PDP 13230 SDP 22 Valid votes Rejected votes Total votes cast Irewole LG Reg voters Accredited voters A 31 APC 18198 LP 17 PDP 14216 SDP 11 Valid votes Rejected votes Total votes castiAtakunmosa east LG Reg voters 41027 Accredited voters 15497 A 40 APC 7449 LP 23 PDP 6992 SDP 14 Valid votes Rejected votes Total votes cast Ìfẹ South LG Reg voters Accredited voters A 36 APC 12481 LP 28 PDP 9116 SDP 14 Valid votes Rejected votes Total votes cast Ìfẹ east LG Reg voters 114403 Accredited voters 41006 A 305 APC 19353 LP 65 PDP 18071 SDP 40 Valid votes Rejected votes Total votes cast",0,yoruba "àkokò, Olùwo ri Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.",0,yoruba "Paraga, kainkain, fona gau ati omiran wo lẹyin tun mọ? Gbogbo awọn ọti inu ọra ati inu igo wọnyii ni ijọba apapọ ti n gbe igbesẹ lati fi ofin de e laipẹ, iyẹn bi ọrọ oludari agba ajọ to n gbogun ti ilokulo ohun jijẹ ati ogun, lorilẹede Naijiria, NAFDAC, Ọjọgbọn Mojisọla Adeyẹye ṣe sọ. Ajọ NAFDAC ni ijọba apapọ fẹ gbe igbesẹ yii nitori ipa ti mimu ọti lọna ti ko tọ n mu ba ilera ilu pẹlu igbayegbadun araalu. O ni bi awọn eeyan ṣe n lanfani lati mu ọti wọnyii nigbakugba to ba wu wọn ninu ọra pelebe pelebe ati igo kekeke n ṣe ọpọ akoba fun awujọ paapaa julọ bi iwadii ti ṣe fihan pe awọn eroja yii lo fihan pe ohun lo n ṣokunfa bi awọn eeyan ṣe n mu ọti bi ẹni n mu omi lawujọ. O ni ijọba ti kọkọ fofin silẹ fun awọn to n pọn ọti inu ọra pelebe ati igo kekeke ni ibẹrẹ ọdun 2020 pe ki wọn din iwọn ti wọn n ṣe jade ku pẹlu ida aadọta ninu ọgọrun, (50%) gẹgẹ bi igbesẹ akọkọ lati dẹkun awọn ọti inu ọra naa. Ajọ ilera agbaye, WHO ti gbe e sita ninu iwadii kan pe eeyan miliọnu mẹta lo n ku lọdun nitori ọti mimu. Ọkọ mi kò fẹ́ràn oúnjẹ òyìnbó àfi ti ìbílẹ̀ - Lizzy Anjorin Mercy Aigbe ṣá ọmọ rẹ̀ sínúu fíìmù tuntun, wo itú tí ọmọ ọdún mẹ́wàá náà pa",0,yoruba "yìí ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn ẹ̀kọ́ ọmọ aláwọ̀ wà níṣẹ̀.",0,yoruba "Obasanjo àti Adebanjo lọ sí Enugu, wọ́n ní kò sí gìrì lórí olùdíje táwọn ń tẹ̀lé",0,yoruba "Ẹ bá wa ké músò! Ohùn Àgbáyé ní Èdèe Yorùbá pé ọdún kan lórí gbàgede Iké-ẹyẹ. @user @user Ẹ bá wa ṣe nínú iṣẹ́ ìlú, ẹ darapọ̀ mọ́ wa!!! #MyTwitterAnniversary https://t.co/1KYvqAfRDj",0,yoruba ni a ní láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó wáyé.,0,yoruba "Asaaju ẹsin One Love Family, Sat Guru Maharaji ti ransẹ ikilọ si Oluwo tilu Iwo, Ọba Abdulrasheed Adewale Akanbi, Telu Kinni. Guru Maharaji, lasiko to n bawọn akọroyin sọrọ nibudo rẹ to wa nilu Ibadan, fi oju abuku wo awọn igbesẹ ti Oluwo n gbe eyi to ni o fi n tapa si ilẹ Yoruba. Lara awọn igbesẹ bẹẹ, gẹgẹ bi Guru Maharaji ti wi ni fifi ara rẹ pe Emir, sisọ awọn ede alufansa si iran Yoruba, bo se fẹ iyawo lapa oke ọya ati titabuku asa Yorua lapapọ. Ṣé lóòtọ́ ni pé mo leè jẹ́ ''virgin"" kí ẹ̀jẹ̀ má sì yọ lálẹ́ ọjọ́ ìgbéyàwó? - Ìwádìí fìhàn Wo bí o ṣe lè so fóònù rẹ pọ̀ mọ́ àwọn ǹkan tí ọmọ rẹ ń wò lórí fóònù rẹ̀ Asaaju ijọ One Love Family naa ni ko sẹni to le tapa si ilẹ Yoruba to le mu jẹ, nitori ọjọ ẹsan n bọ. A fẹ ki Oluwo ranti pe baba kan lo bi awọn, ẹni ti ko de ipo tawọn de loni yii. Nitori naa, a fẹ ki wọn ye fi orisirisi abuku lọ wa, mo gbọ nigba kan ti wọn ni awọn fẹ joye Emir nitori ifẹ ti n bẹ laarin awọn ati Arewa. Irọ ni, jibiti ni wọn fi n rin, wọn ko sọ otitọ ri, baba wa naa ni wọn amọ wọn fẹ fi eru gba ibukun ni wọn tun se gba ibi ẹsin wọle. O wa yẹ ki Oluwo maa ranti pe ewe n bẹ o, ẹ sọ fun wọn ki wọn tete yipada nitori asa ati ise Yoruba lo wa nipo kinni jake jado agbaye. Ẹni to ba ni ko rii bẹẹ, ko wa sọ jade, ko wa koju mi."" Bakan naa ni Guru Maharaji fikun pe ohun to n ba ni ninujẹ, ti ko si bojumu ni awọn iwa Oluwo naa. O wa fikun pe ẹnikan kii tapa si ẹya Yoruba, ẹni to ba tapa si Yoruba, Iya yoo jẹ. Nigba to n sọrọ lori bi Oluwo se lọ mu iyawo wa nilẹ Hausa, Guru Maraji ni ti eeyan ba pẹ lori imi, esinkesin yoo bo. O ni Naijiria ti goke agba, ọlaju si ti de amọ ohun to se pataki fun Oluwo ni pe ko ma gbagbe asa. ""O seese ki Oluwo mọ ohun to ri lara obinrin yẹ, emi o gbọ iru rẹ ri, kii si se Kabiyesi wa lo yẹ ko se bẹẹ́.""",0,yoruba "yìí ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba nípa aráyé: ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba ọsẹ àsa. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó ga.,0,yoruba "Gẹgẹ bi awọn oniroyin ṣe sọ ọ, awọn to ba iṣẹlẹ naa rin n ririnajo bọ lati ipagọ adura awọn Kristẹni kan eyi ti wọn n pe ni Oke Maria Pilgrimage ni agbegbe Otan Ayegbaju ninu ọkọ ijọ Paul Catholic Church, Lagere Ile Ife. Awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn ni ṣe ni ọkọ to n gbe awọn ero ọhun bọ lati ipagọ adura ti wọn ṣe lọjọ ẹti yiwọ to si lọ rọ lu odi kan lẹba opopona Ire/Eripa/Otan Ayegbaju/Ila eyi to si jẹ ki ọkọ naa da sinu koto. Iroyin sọ pe awọn oṣiṣẹ ajọ ẹṣọ aṣọbode ti de ibi iṣẹlẹ naa ti wọn si ti n gbe awọn to fara pa jade kuro ninu ọkọ naa pẹlu iranlọwọ awọn to n gbe ni agbegbe naa. Lasiko ti iroyin naa wọle, o ti le ni eeyan mẹwaa ni o ti gbẹmi mi gẹgẹ bi awọn to n kọja lọ ṣe n ke bosi o. Ọjọ ẹti ọjọ kẹjọ oṣu keji ni ipagọ adura naa waye eyi ti ọgọrọ awọn olujọsin korajọ fun adura ni Oke Maria to wa ni Otan Ayegbaju.",0,yoruba "kún jú, àwọn ènìyàn ni ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún gbogbo.",0,yoruba "13. Ààbà loògùn tí ń mú èèyàn má le è ṣe nǹkan kan, ____ni oògùn tí máa ń fi ọ̀nà han ọdẹ nínú igbó. A. Agbe B. Ọ̀rẹ́kẹ́ṣẹ́ #ibeere #Yoruba",0,yoruba "Leke Adeboye to jẹ aburo oloogbe Dare Adeboye ti sọrọ lori ohun ti oun yoo bẹrẹ si ni ṣe fun ẹbi ẹgbọn oun ni asiko yii to ti fi aye silẹ. Ọjọ Kọkanla, Oṣu Karun un ni Dare Adeboye wọ ilẹ sun, lẹyin ti o doloogbe ni ẹni ọdun mejilelogoji ni Ọjọ Kẹrin, Oṣu Karun un, ọdun 2021. Leke Adeboye lasiko to n sọrọ ni oun yoo sa gbogbo ipa oun lati ri i wi pe awọn ọmọ oloogbe naa ri itọju to peye. Leke ni: ''Nibayii, mo mọ pe mo ni ọmọ mẹfa nitori mo bi mẹta, ẹgbọn mi si bi mẹta, ma a si ṣe itọju wọn.'' ''Gbogbo nkan ti wọn ba n ṣe ni ma a ri wi pe mo peju-pesẹ sibẹ to fi mọ igba ti wọn ba n lọ ṣe ayẹwo ara wọn'' 'Mo ti sọ fun iyawo mi pe: Awọn ọmọ rẹ ti da ti temi, ma a si sa gbogbo ipa mi lati wa nibẹ fun wọn.'' Leke tun ni pe: ''Amọ mi o ni ṣe iṣe ajihinrere to gbe kalẹ nitori ọgbọn lati ṣe iṣẹ ihinrere rẹ yatọ si ti temi, ti ọpọlọpọ eniyan si fẹran rẹ ti o ba n waasu.'' '' Ti ẹgbọn mi ba n waasu, awọn eniyan ma n ho fun ayọ ni, amọ ti emi ba n waasu ko si ẹni ti yoo ho fun ayọ nitori mo ma n sọ otitọ ọrọ bii abata ti a na ni pọ̀pá ni, ẹnikẹni ni ọrọ mi le ta ba ni, kii ṣe bi ajihinrere.'' ''Ohun gbogbo ni emi ati ẹgbọn mi ṣe papọ, to fi mọ ọjọ igbeyawo...'' Bakan naa ni Leke Adeboye sọ oriṣiriṣi ohun ti oun ati ẹgbọn oun jọ ṣe papọ lasiko ti wọn n dagba, titi awọn fi di ọdọ langba. Leke ni ileẹkọ kan naa ni wọn jọ lọ lati ileẹkọ alakọbẹrẹ, girama, to fi mọ kikawe ni oke okun. ''Nigba ti mo gbọ wi pe ẹgbọn mi n lọ ka iwe ni oke okun ti ko si fẹ mu mi lọ, mo sọ fun pe ọkọ baalu rẹ yoo gbina ti ko ba mu mi dani. Leke tun ni: ''Ẹgbọn mi lo fi ẹjọ mi sun Baba Adeboye, ki o to di wi pe ẹmi naa tẹle e, ti a si jọ lọ ka iwe ni ileewe kan naa ni oke okun'' ''Dare Adeboye jẹ ẹni to kun fun ọgbọn, ti kii ṣi ṣe imẹlẹ ni gbogbo nkan to ba n ṣe'' Ọpọlọpọ igba ni awọn eniyan maa n sọ fun mi pe ṣe mi o le dabi ẹgbọn mi ni? amọ a yatọ si ara wa'' Leke Adeboye wa gbadura wi pe ọrun lo ja ju fun gbogbo onigbagbọ, ati wi pe oun gbadura wi pe bi Dare Adeboye ṣe pari daradara naa ni awọn yoo pari daradara ni ile aye.",0,yoruba Ìbàdandun ni ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn. (Item 95),0,yoruba "ní ègé olóótọ fún àwọn ìkòkò tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba … Mo lálàá wí pé mo lọ sí inú oòrùn .,0,yoruba "ní nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn ẹ̀kọ́ ọmọ aláwọ̀ wà níṣẹ̀.",0,yoruba "Nikita Pearl Waligwa kopa Gloria, ọrẹ Phiona, to kọ ọ bi wọn ṣe n ta ayo 'chess' Gẹgẹ bi awọn akọroyin ni Uganda ṣe sọ, wọn ni jẹjẹrẹ inu ọpọlọ ni ọmọ naa, Nikita Pearl Waligwa ni. Fiimu to ṣe lọdun 2016 jẹ itan igbe-aye Phiona Mutesi, to bẹrẹ si ni ta ayo Chess lọmọ ọdun mẹsan, bo tilẹ jẹ pe ko lọ sileewe rara, ṣugbọn o gbe ayo naa de ipele to lagbara, to si bẹrẹ si ni kopa ninu idije agbaye. Awọn oṣere bii Lupita Nyong'o to ṣe iya rẹ, ati David Oyelowo, to ṣe olukọ to kọ bi wọn ṣe n ta ayo 'Chess, lo kopa ninu fiimu naa. Waligwa kopa bi i Gloria, ọrẹ Phiona to ṣalaye bi wọn ṣe n ta ayo naa fun. Ọdun 2016 ni wọn ti kọkọ sọ nileewosan pe o ni jẹjẹrẹ inu ọpọlọ. Iroyin si sọ pe oludari fiimu 'Queen of Katwe, Mira Nair, ko awọn eniyan jọ lati da owo ti wọn yoo fi ṣe iṣẹ abẹ fun ni India, 'nitori pe awọn dokita Uganda sọ pe awọn ko ni irinṣẹ lati tọju rẹ'. Botilẹjẹ pe wọn sọ l'ọdun 2017 pe ara rẹ ti n ya, wọn pada ri jẹjẹrẹ miran l'ọdun to kọja.",0,yoruba ẹkọ́ ṣẹlẹ ni Ibadan ti gbogbo eniyan sọ o dara. (2006),0,yoruba "Buhari ni alafi awọn ara ilu lo yẹ ko jẹ awọn aarẹ ilẹ Afirika logun Buhari lo sọ ọrọ yii l'Abuja nibi ipade ti awọn aarẹ ati minisita to wa ni iwọ orun Afirika ṣe, lati wa ojutu si idojukọ awọn alakatakiti ẹsin. Nibi ipade ọhun ni Buhari tun ti sọ pe iṣẹ ibi awọn alakatakiti ẹsin ni isọro gboogi to n koju iwọ orun Africa. O ni akoko ti to ni Afirika lati fọwọsowọpọ lọna ati wa ojutu si wahala awọn alakatakiti ẹsin naa. Buhari mẹnu ba bi awọn onija ẹsin ọhun ṣe pa awọn ọmọ ogun mẹtalelọgbọn ni ipakupa lorilẹede Niger laipẹ yii. Trump impeachment: Trump kò fìdí janlẹ̀ tán, àmọ́ níbo ni yóò jásì? Lẹyin naa lo ni orilẹede Naijiria ti ṣe tan lati ṣafẹhinti fun awọn orilẹ-ede mii nilẹ Afririka lati gbogun ti awọn alakatakitii ẹsin ọhun. Buhari ni alafia awọn ara ilu lo yẹ ko jẹ awọn aarẹ ilẹ Afirika logun.",0,yoruba wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba Ẹkọ́ ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba "láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Ìyẹn bẹ́ẹ̀ , àwọn ọmọ ẹgbẹ́ẹ ajótà Ìran Ọ̀kín Thangya márùn - ún di èrò ẹ̀wọ̀n tí ó wà ní Insein títí di ìgbà tí wọn yóò lọ sí ilé ẹjọ́ fún ẹ̀fẹ̀ tí wọ́n fi ológun ṣe .",0,yoruba òní. ti Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "February 2020 memories, 2021 music. 🔥✊🏾👾 Àkókò kò dúró de ẹnìkan. Time waits for no one. #Yoruba #NicoleKali #progression #glitchart https://t.co/fbG6nrMu8C We are Afrogoth, @user alongside @user , @user and many more. 👾👻😈 https://t.co/CBcIVIyXng",0,yoruba iyalẹnu wey ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa aráyé: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Alàji lo fi.,0,yoruba Eḳọ tí a ní nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o nuni ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba "Wọn maa n wọ ọkọ oju omi, gbafẹ, gba bọọlu tabi ṣe ayẹyẹ. Ṣugbọn, awọn to laya le san owo lati gun ẹṣin - pẹlu iranlọwọ awọn ẹlẹṣin to wa leti okun. Quadri Raji, ẹni ọdun mọkandinlogun n ṣiṣẹ atun foonu ṣe larin ọṣẹ, ṣugbọn o maa n fi ẹṣin siṣẹ leti òkun Atlantic l'opin ọsẹ. O pa ẹ̀kọ́ rẹ ti nileewe girama nigba ti wọn ge ẹsẹ iya rẹ lẹyin ijamba kan. Nibayi, oun n tọju ara rẹ, o si ni ireti pe ẹṣin yii yoo pa owo ti yoo to, lati ṣe idanwo aṣejade ileewe girama. ''O wumi lati tẹsiwaju ninu ẹ̀kọ́ mi, àmọ́ bayii iṣẹ kan yii ni mo n ṣe lati pawo wọle. Leti okun, Quadri maa n pa to ẹgbẹrun mẹwa Naira lójúmọ́. Ẹṣin rẹ, Jack, maa n jo lasiko awọn ọdun ibilẹ, ṣugbọn Quadri ti n kọ ọ lati ṣiṣẹ leti òkun. O si maa n ṣe daada. Tunde Sanni (to wa lapa òsì), jẹ ẹni ọdun mejidinlọgbọn. O si ti n gun ẹṣin leti òkun ju ọdun mẹtala lọ, oun si ni alaga ẹgbẹ awọn to n gun ẹṣin ni eti okun Atican. Ọdun 2008 ni awọn obi rẹ ku, o si tun n ṣiṣẹ ajorin-mọrin. ""Ẹṣin gigun si ti gba ole jija lọwọ mi."" Àpá kan wa niwaju ori Tunde, eyi to waye lasiko to jabọ lori ẹṣin nigba ti ọkọ ayọkẹlẹ kan gba a lasiko to n gun ẹṣin lọdun 2010. 'Stone' jẹ ọkan lara ẹṣin mẹta to ni, Oun naa lo ni 'Prince ati 'Pale.' Ẹni ọgbọn ọdun ni Lanre, o si ti n ṣiṣẹ ẹṣin gigun leti okun fun ọdun mẹta. Bakan naa lo maa n ta ewurẹ ati tolotolo ni ọja ẹran ọsin. Opin ọsẹ lo maa n mu ẹṣin rẹ, 'Spaghetti', lọ si eti okun lati pawo si i. ""Mo niyawo ati ọmọ meji ti mo n bọ ọ, nitori naa ni mo ṣe n gba ọna mi i lati pawo wọle.'' Ẹṣin Adebọwale Dada, Jerry, maa n ṣiṣẹ tẹlẹ fun ere sisa. O ra a ni igba ẹgbẹrun ati mẹtalelaadọta Naira, niluu Kano lọdun to kọja. ""Iṣẹ kan ti mo n ṣe niyii, mo si niyawo ti mo n tọju. Bakan naa ni mo n fi owo pamọ fun owo ileewe awọn ọmọ mi."" Bi ẹẹdẹgbẹta Naira si ẹgbẹrun kan Naira ni awọn eniyan maa n san lati gun ẹṣin, awọn ẹlẹṣin a si maa rin pẹlu wọn. Igba akọkọ niyii ti Favour Eric yoo gun ẹṣin. ''Ẹru ba mi o, ṣugbọn mo gbadun ara mi.'' Awọn ẹlẹṣin yii jẹ diẹ lara awọn ẹgbẹ wọn o n wa awọn ọna ti ko wọpọ lati wa owo, nigba ti iṣẹ oṣu ko si nigboro. Awọn aworan yii wa lati ọwọ oṣiṣẹ BBC, Grace Ekpu.",0,yoruba Ancestors in trouble. Nigerian Army need some slap for all the abuse. . . 👉 Yorùbátv ẸGBẸ ỌMỌ OLÚWA BÍ GBOGBO ÀGBÁYÉ Ojú òpó ìkànsíraẹni 🇳🇬🇹🇬🇧🇯🇧🇷🇨🇴🇨🇺🇬🇭🇨🇮______________________________□ Yoruba TV 🥰😘🔥 #yoruba #yorubatv… https://t.co/7FXtX8TKCu,0,yoruba "Iná sọ lẹ́yìn táwọn ajépo gbé bẹ́ àgbá epo l'Abule Egba Ajọ LASEMA ti wọn n mojuto iṣẹlẹ pajawiri ni ipinlẹ Eko ni àwọn ti gbe gbogbo awọn to fi ara pa ninu iṣẹlẹ naa lọ fun itọju nile iwosan. Ogbẹni Tiamiyu Adeṣina to jẹ ọga agba ajọ LASEMA ni awọn oniṣẹ ibi ti wọn n ji epo rọbi lati inu ọpa epo lo ṣokunfa ina to ṣẹ naa. O ni ko sẹni kankan to sọ ẹmi rẹ nu ninu iṣẹlẹ ọhun ṣugbọn ọpọlọpọ ile lo jona ni Awori ni Abule Ẹgba ti ọpọlọpo si n ṣofọ awọn nkan ti wọn padanu. Buruji Kashamu: Èmi ṣì ni olùdíje PDP ní Ìpínlẹ̀ Ogun Republic of Benin: ìtàn tó bí abẹ́sàn án kọjá bẹ́ẹ̀! Ọga agba LASEMA gba awọn ara ilu niyanju lati maa tete sọrọ jade ni kete ti wọn ba ti kẹfin ohunkohun ladugbo wọn. O ni awọn ti ri oriṣii itọni ati awọn igbese to yẹ ki ajọ awọn agbofinro gbe ni eyi ti o fi ṣeeṣe lati fopin siru iṣẹlẹ yii nibi ifọrọwanilẹnuwo ti awọn ti ṣe pelu awọn ara Abule Ẹgba. ọpọlọpọ mọto, ọjà ati nkan amuludun lo jona ni Abule Egba nidaji Seun Kuti: Fela ló n pọ́n gbogbo òǹkọrin Afrobeat lagbaye",0,yoruba "Omoluabi wa ni ìya ìlú lo je ti ibile. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé.. Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "Kò ju oṣù mẹ́rin ti Real Madrid gba akọ́nimọ̀ọ́gbá Julen Lopetegui ti wọ́n ti ní kó lọ rọọ́ kún nílé. Ninu atẹjade ti Real Madrid fi sita, Solari yoo wa ni ipo akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu naa titi wọn yoo fi ri ẹni to koju osuwọn lati tukọ wọn. Iroyin fikun wi pe akọnimọọgba tuntun naa kii se gbajugbaja ti awọn eniyan mọ l'agbo ere bọọlu ilẹ Spain. Ni bayii solari yoo tukọ ẹgbẹ Real Madrid lati kopa ninu ifẹsẹwọnsẹ mẹrin pẹlu Malilla, ninu idije Copa Del Rey, Real Valladolid ati Celta Vigo ninu idije League. Nigba ti wọn yoo ma koju Viktoria Plzen ti ilẹ Czech ninu idije Champions League. Real Madrid: Ta ló tóo gbé wọn dé èbúté ògo nínú Premiere League? Àmì ayò márùn ún sí ọ̀kan ni Barcelona fi gbewúro sójú Real Madrid ni El Classico. Won ko fun Julen Lopetegui laaye ju osù merin lọ lati tukọ Real Madrid Eyi jẹ ọkan lara idi ti wọn fi ni ki akọnimọogba wọn, Julen Lopetegui maa lọ sile rẹ pada ni eyi to sọ wọn di ẹni to n wa akọnimọọgba tuntun bayii. Oriṣiiriṣi àwọn akọnimọogba lo ti n fifẹ han lati tukọ ẹgbẹ agbabọọlu yii siwaju ninu idije premiere league. Idije mii ti wọn ni niwaju ni pẹlu Melilla ninu idije Copa del Rey lalẹ ọjọ'Ru. Ta ni adé yìí yóò wọ orí rẹ́? Ọ̀kan pataki lara awọn ti wọn n foju si lara lati wọ bata akọnimọọgba tuntun fun Real Madrid ni Santiago Solari. Santiago Solari ni ẹgbẹ agbabọọlu na yan lati dile mu fun wọn gẹgẹ bii akọnimọọgba titi wọn yoo fi gba ẹlomii rọpo Julen. Santiago ni ẹnu n kùn julọ pe o ṣeeṣe ki ade yii ṣimọ lori Santiago jẹ ọkan lara agbabọọlu Real Madrid tẹlẹ ko to lọ maa kọni mọọgba ni Madrid 'B' ki wọn to pèé kó wa ba wọn di real Madrid mu fun igba diẹ yii. Ọdun 2013 ni Solari darapọ mọ ẹgbẹ yii to si mọ tifun-tẹdọ rẹ̀. Antonio Conte: Antonio jẹ ọkan pataki lara awọn agba akọnimọọgba ninu ere bọọlu alafẹsẹgba. Ọpọlọpọ gbà pé o ni iriri to le gbé ẹgbẹ Real Madrid soke ninu idije yii. Lati igba ti ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea ti daa duro ni ko tii niṣẹ mii to n ṣe. Iroyin to n kàn lọwọ ni pe Antonio ọmọ Italy yii ti ṣetan lati ṣiṣẹ pẹlu wọn. Conte ko i niṣẹ mii lati igba ti Chelsea ti daa duro Conte ti gba ife ẹyẹ League lẹẹmeji ri pẹlu Chelsea ati Juventus ni eyi to fi iriri rẹ han pe o to iṣẹ naa ṣe. Jose Mourinho: O jẹ agba ọjẹ akọnimọọgba to ti ṣiṣe pẹlu Real Madrid ri. Ọmọ Pọtugi yii ni ko wu oun lati pada si Real Madrid ṣugbọn iroyin ti a n gbọ ni pe, wọn ti n wo apa ọdọ rẹ naa wo boya o le gbe Real Madrid de ebute ogo lasiko yii. Manchester United ni Mourinho ti n ṣiṣẹ bayii. Ọdun 2010 si 2013 lo fi jẹ akọnimọọgba fun Real Madrid. Oju Real Madrid tun ti wa lara Jose Mourinho lasiko yii Arsene Wenger: Arsene Wenger fipo rẹ silẹ kuro ni Arsenal lẹyin ogun ọdun o le meji to ti n ba wọn ṣiṣẹ. Lati igba to ti kuro ni oun naa ko tii niṣẹ miran di asiko yii. O jẹ ọkan lara awọn agba ọjẹ akọnimọọgba ni Yuroopu ni eyi ti ọkan awọn Real Madridi lè balẹ pẹlu fun ilọsiwaju. Wenger naa koi tii niṣẹ miran latigba to ti kuro ni Arsenal Ki ló ti ṣẹlẹ̀ sẹ́yìn ní Real Madrid? Omi ti tẹyin wọ igbin lẹnu fun Lopetegui Ẹgbẹ agbabọọlu Real Madrid ti gbà iṣẹ́ lọ́wọ́ akọnimoogba wọn Julen Lopetegui. Ikede yi waye lẹyin osu mẹrin ati abọ to gba iṣẹ akọnimoogba ẹgbẹ La Liga ohun. Eyi ni igba ẹlẹkeeji ti iṣẹ yoo bọ lọwọ Lopetegui. Real Madrid to ti gba liigi fun igba mẹsan ko ṣe daada lẹnu ọjọ mẹta yi labẹ akoso Lopetegui. Eyi ni igba ekeji ti iṣẹ yoo bọ lọwọ Lopetegui Ikede iyọniniṣẹ rẹ́ ti wọn fi si oju opo Twitter wọn salaye pe Santiago Solari to jẹ agbabọọlu ẹgbẹ naa tẹlẹ ri ati akonimoogba ikọ keji Real Madrid ni yoo gba ipo rẹ titi ti wọn yoo fi kede eni ti yoo rọpo rẹ. Ẹgbẹ agbabọọlu na salaye pe aisedeede wa ''laarin awọn osiṣẹ ẹgbẹ naa ti esi ti awọn n ri'' Ipo kẹsan ni wọn wa lori afara liigi. Ọrọ ro naa doju rẹ pẹlu ifidirẹmi El Classico Luis Suarez jẹ goolu mẹta lati da kun iṣoro akọnimọgba ikọ Real Madrid , Julen Lopetegui, ninu ifẹsẹwọnsẹ El Classico to lamilaka lọjọ aiku. Julen Lopetegui ati awọn agbabọọlu rẹ ko ri ju esi goolu kan dapada ninu maarun ti Barcelona gba sinu awọn wọn. Ni bayi, a ti ma padanu iṣẹ Julen Lopetegui yoo ku si ọwọ Ọlọrun pẹlu bi awọn alatako ẹgbẹ wọn ti ṣe doju ti wọn. Aisinile Messi ko tiẹ yọlẹ pẹ́lu bi Suarez ṣe jẹ goolu mẹta Phillipe Coutinho lo kọkọ gba goolu wọle ni abala ikini ifẹsẹwọnsẹ naa lẹyin ti Luis Suarez jẹ gbesilẹgbasile wole fun goolu elekeji. Real Madrid ja fita fita ni abala keji ti wọn si ri goolu kan jẹ lati ọwọ Marcello to faya sọ bọọlu kale ki o to gba wole pẹlu ẹsẹ ọtun rẹ. Ẹpa ko boro mọ Kaka ki ewe agbọn Barcelona dẹ, niṣe ni o le koko si ti wọn si fi goolu mẹta ọtọọto dakun wahala Real Madrid. Ninu goolu mẹta ohun,Luis Suarez jẹ meji ti Arturo Vidal si kasẹ eto n lẹ pẹlu goolu ẹlẹkaarun. Pẹlu esi yi, Real Madrid ti bọsi ipo kẹsan lori afara liigi ti Barcelona si le tente lori afara. #Adetutu Alabi OJ: Mo ti gba kámú lórí ilà ojú mi",0,yoruba "Ìwádìí fihàn pé ọkọ̀ òfuurufú #MH370 ya ìbòmíràn, pé #China lọ́ yẹ kó gbà. @user",0,yoruba "Bi ọpọ pasitọ ati aafa ṣe n sọ asọtẹlẹ lori ohun ti yoo ṣẹlẹ lọdun tuntun ọdun 2021 yii, ajafẹtọ Sunday Adeyemo ti ọpọ mọ si Sunday Ighoho ti sọrọ akin lori ohun to kan fun ilẹ Yoruba. Sunday Ighoho sọrọ yii lori ẹrọ amohunmaworan pẹlu awọn ọdọ kan ti wọn kan si nile rẹ. Ọgbẹni Adeyemo sọrọ o fa komookun rẹ yọ pe ọdun ominira ni ọdun 2021 yii jẹ fun ilẹ Yoruba. Sunday Igboho ni awọn ọdọ lo n jiya ju ni Naijiria, nitori diẹ ni tawọn agbalagba nibẹ. ''Abọwaaba lọrọ awọn agbaagba ilẹ Yoruba, awọn ọdọ lo yẹ ki a ṣe ara wa lọkan,'' ọgbẹni Adeyemo lo sọ bẹẹ. Sunday Ighoho ni o ti wa ninu akọọlẹ pe ọdun ayọ ati ọdun ominira ni ọdun 2021 jẹ fun ilẹ kaarọ o jiire. O ṣalaye oun atawọn mii to fẹ ki Yoruba gbaye gbadun ko ni ohun kan ṣe pẹlu awọn ọlọpaa ati sọja. Sunday Igboho ni ọpọ ọdọ lo ti ka iwe gboye ni ile ẹgọ giga fasiti tan lai ri iṣẹ ṣe. O gbadura pe gbogbo awọn to ba ṣe abosi tabi da ilẹ Yoruba, ilẹ Yoruba yoo da fun wọn. Sunday ṣalaye pe ọpọ lo ro pe oun kan ṣadedee dakẹ lori ọrọ ilẹ Yoruba. Amọ, o sọ pe agbo oun to fẹyin rin, agbara lo lọ mu wa. Ọgbẹni Adeyemo rọ awọn ọdọ pe ki wọn maa ṣojo, ki wọn si mura lati ja fun ẹtọ wọn. O ni awọn ọdọ ti wọn maa n ran lati tako awọn ọdọ ilẹ Yoruba to n beere fun ẹtọ wọn ni ori wọn ko pe.",0,yoruba "Kọmiṣọna feto ilera nipinlẹ Eko, Ọjọgbọn Akin Abayọmi lo ṣalaye eyi ninu atẹjade kan lọjọru. Ọjọgbọn Abayọmi ni ẹni naa ti wa labẹ itọju nileewosan nla fasiti ilu Eko, LUTH. Amọṣa kọmiṣọna feto ilera nipinlẹ Eko ko ṣai fi awọn olugbe ipinlẹ naa lọkan balẹ pe ko si idi fun wọn lati foya nitoripe eto gbogbo ti to lati kapa iba naa to ba fẹ gbera sọ nibẹ. O ni ileeṣẹ eto ilera ti n ṣe iwadii lori awọn eeyan ti ẹni to ko aarun naa ba da nnkan pọ lati mọ awọn to ṣeeṣe ko ti ko aarun ọhun lọwọ yii nipasẹ rẹ. Bakan naa ni kọmiṣọna fun eto ilera ni ipinlẹ Eko tun ke sawọn eeyan ipinlẹ Eko lati karamasiki ilera wọn ki wọn si yago fun ekute. O ni awọn agbegbe ayẹwo iyasọtọ ti wa kaakiri lati tọju awọn eeyan to ba lugbadi aisan naa; ti oogun ati itọju to bagbamu pẹlu ilana agbaye si ti wa nikalẹ fun wọn. Gẹgẹ bii iwadii ajọ to n ṣewadi ati igbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, eeyan eedẹgbẹta ati mọkanlelọgbọn ni wọn ti funra aisan iba Lassa si bayii lorilẹede Naijiria; mẹrinlelọgọrun ninu wọn ni wọn si ti fi idi rẹ mulẹ pe wọn ni aisan naa ti eeyan mẹfa si ti jade laye nipasẹ rẹ.",0,yoruba "àsà tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba "Ni agogo mẹsan aarọ ọjọ Ẹti ni eto naa yoo bẹrẹ ni gbangan Ọjọgbọn Theophilus Ogunlesi nidojukọ ọgba UCH. Ṣugbọn ẹ jẹ ki a sọrọ nipa gbangan Mapo to kalẹ si ilu Ibadan nibi ti ole ti n jare olohun. Ipade itagbangba BBC Yoruba Gbọngan Mapo re e to kalẹ sori oke Mapo ti wọn fi sọ orukọ rẹ nilu Ibadan. Nibi ni awọn ọmọbibi ilu ti maa n ṣepade ọrọ oṣelu, ọrọ idagbasoke ati ilọsiwaju ilu Ibadan. Ipade itagbangba BBC Yoruba Ẹni to ba duro lori oke Mapo, kedere ni yoo maa ri gbogbo ilu Ibadan ninu ogo rẹ. Ipade itagbangba BBC Yoruba Awọn opo to di gbọngan Mapo mu lo n ṣe apejuwe oke meje to yi ilu Ibadan ka. Gbogbo oke yii ni wọn si mọ opo si. Ipade ita gbangba BBC Yoruba Tabili yii ni wọn maa n tẹ awọn oku Olubadan to ba ti waja si ki gbogbo ara ilu le rii. Ipade Itagbangba BBC Yoruba Gbọngan Mapo tobi gan, bẹẹ lo laye daadaa lati gba ọpọlọpọ eeyan. Nibayii gbogbo eto lo ti wa ni ṣẹpẹ bayi ṣaaju ipade itagbangba BBC Yoruba lọjọ Ẹti, ẹ jẹki a jọ pade nibẹ lọla.",0,yoruba Ebi kan fẹ́ máa pa mí fẹ́ẹ́rẹ́fẹ́. Kíni n ó wa jẹ?,0,yoruba "Ẹni tó ńgun ẹṣin kó sọ ìpàkọ́ mọ ní'wọ̀n; ìbẹ́kẹ́ṣẹ́ ẹṣin á máa la’ni mọ́’lẹ̀ / When on a horse, fling your head backward in moderation; horses do throw their riders [Exercise self-control; never abuse privileges; safeguards against abuse do exist] #Yoruba#proverb",0,yoruba "Ọjọ́ kan, ọ̀rọ̀ kan | One word per day • Òpin - The end • Follow us @user for more quality Yorùbá contents! • • #yorubanimi #yorubaindiaspora #yorubahood #edeyoruba #edeyorubarewa #yoruba https://t.co/cSaXk7gT8t",0,yoruba Ọ̀nà mẹ́sàn án láti yọ ààrẹ Naijiria nìyìí...,0,yoruba Ìlẹ̀ Ọ̀yọ́ jẹ́ ìlú tí ó ṣe pàtàkì.,0,yoruba ife alailegbe bi eyi ti edumare fi fe wa e ku ojumo oh,0,yoruba "Ẹgbẹ́ agbábọ́ọ́lù Manchester City ló ń se ipò kíní lórí tábìlì Premier League pẹ̀lú àmì ayò 65 lórí àtẹ. Sergio Aguero lo pegede julọ ninu ifẹsẹwọnsẹ to waye ni alẹ Ọjọ Àìkú. Ẹgbẹ agbabọọlu Manchester City ọhun lo n leke tabili pẹlu ami ayo marunlelọgọta (65) lori atẹ tabili Premier League. Ọkọ àti ìyàwó sọ àsọtẹ́lẹ̀ tani yóò wọlé nínú PDP tàbí APC Liverpool naa pẹlu na Bournemouth, eleyii to ti mu ki ẹgbẹ agbabọọlu naa si wa ni ipo keji ni ori tabili.",0,yoruba "Kódà ni Hong Kong , àyè láti sọ ọ̀rọ̀ ẹnu ẹni jáde àti láti bá èèyàn ṣe pọ̀ ti jákulẹ̀ .",0,yoruba "Awọn to gbe iroyin tiẹ sọ pe ọmọ orilẹ-ede Cameroon kan to n gbe ni China ri iwosan nitori pe o jẹ alawọ dudu. Irọ nla leyi, nitori pe ko ti i si ẹri ijinlẹ pe awọn alawọ dudu ni anfaani lati bori coronavirus ju awọn ẹya miran lọ. Bakan naa lo ṣe pataki lati mọ pe aarun naa yara pa awọn to ba ti dagba diẹ tabi ni aarun kan ti wọn n tọju lara tẹlẹ. O si tun ṣe pataki fun ọ lati maa nu foonu rẹ pẹlu lati dena aarun naa.",0,yoruba "ìwájú. Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.",0,yoruba "Wọ́n yọ àwọn ohun ìjà ti akọ̀ròyìn Marco Ruiz , Luz Mely Rehes àti Federico Black [ pẹ̀lú àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ ìròyìn .",0,yoruba ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba "@user @user #Atunse A à rí i ooo - ó yẹ kí a máa kọ ọ́ ní ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ni, a kò gbọdọ̀ kọ ọ́ papọ̀, àfi bí a bá ṣe ìsúnkì. Aàrí kò tọ̀nà, 'a à rí i' ni ó yẹ. A à rí i náà ni a ò rí i. #Ami #Yoruba ❤️",0,yoruba "the offender must make restitution from the best of their own field or vineyard. #Yoruba ẸKISODU 22:5 “Bí ẹnìkan bá jẹ́ kí ẹran ọ̀sìn rẹ̀ jẹ oko olóko, tabi ọgbà àjàrà ẹlòmíràn, tabi tí ó bá da ẹran wọ inú oko olóko tí wọ́n sì jẹ nǹkan ọ̀gbìn inú rẹ̀,",0,yoruba "Ní ní àìlẹ̀, Ìyá ri Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "Ninu awọn ibudo idibo ti akọrọyin BBC foju ri ibo kika, wọn jabọ pe awọn ẹgbẹ oṣelu APC ati PDP ni wọn jijọ n fagba han ara wọn. Saaju ki a to fi awọn esi ohun sọwọ, a fẹ ki ẹ mọ wi pe eyi ke ṣe akojọpọ esi ibo lapapọ, bi kii ṣe awọn esi to waye lawọn ibudo idibo awọn eekan oloṣelu ti a ṣe akojọpọ wọn paapa julọ ninu ibo Aarẹ. Igbakeji Aarẹ Osinbajo fidirẹmi Igbakeji Yemi Osinbajo Awọn oludibo to wa ni wọọdu idibo kẹrin, agọ idibo kẹtalelọgbọn ni agbegbe VGC, Lekki ikate ti igbakeji Aarẹ Yemi Osinbajo ti dibo,wọn ti fi ibo wọn da sẹria, ti ẹgbẹ PDP si bori APC nibẹ. Ninu esi eleyi ti akọroyin wa jabọ lati ẹnu oṣiṣẹ Inec nibẹ, bayi ni nnkan ti ṣe lọ ninu idibo Aarẹ: PYO Ward 4 unit 033 Esi ibo Aarẹ: ANN : 39, APC: 197, PDP: 384 Unit 033 A Esi ibo Aarẹ: ANN: 2, APC: 32, PDP: 41 Buhari na Atiku pẹlu ibo 19 lagọ idibo rẹ ni Yola Oludije ipo Aarẹ fun ẹgbẹ APC, Muhammadu Buhari na fẹyin akẹgbẹ rẹ, Atiku Abubakar, to n soju ẹgbẹ PDP janlẹ ni agọ idibo Atiku pẹlu ibo mọkandinlogun. Aworan esi ibo aaye idibo Atiku Buhari ri ibo 186 gba ni agọ idibo Ajiya unit 02 ni Yola, Adamawa nibit Atiku ti ri ibo 167 gba . Atiku fẹyin Buhari gbolẹ ni Aso Rock villa Lẹyin ti wọn tun ibo ka ni agọ idibo to wa nile ijọba Presidential villa l'Abuja, apapọ esi ibo ni agọ idibo 021 ati 022 Aso Rock Villa lọ bayi: Buhari ati Atiku nibi ti wọn ti n dibo Esi ibo Aarẹ APC - Buhari: 1017, PDP - Atiku: 1027, Ile Asofin agba: APC 1009, PDP 1082 Donald Duke fidirẹmi lọwọ PDP lagọ idibo rẹ Ibo mẹfa pere ni oludije ipo Aarẹ labẹ asia SDP, Donald Duke ri gba nibudo idibo rẹ Atiku Abubakar, ti ẹgbẹ PDP lo jawe olubori mọ lọwọ. Egbe SDP niDonald Duke to ti jẹ Gomina ri n soju Bi esi ṣe lọ ree ni agọ idibo rẹ tii ṣe AME Zion School unit 005 ni Calabar, ipinlẹ Cross River : APC - Buhari: 98, PDP - Atiku: 291, SDP - Duke: 6 Saraki di aye idibo rẹ mu fun PDP Bi nnkan ti ṣe lọ re agọ idibo Saraki Ajikobi ward, opobiyi PU 06 : Esi Ibo Aarẹ APC 152, PDP 234, GPPN 1, AA 1, PCP 3",0,yoruba @user Ile Iba to Jo ewa lo bukun. #yoruba,0,yoruba ọ̀rọ̀ yi kún fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba RT @user: Irin ajo mi si festac leni yi ku die kaa to. Ago mejo ni mo to wole pada de. Gbogbo ara lon ro mi #TweetinYoruba,0,yoruba "Mai Mala lo sọ ọrọ naa lasiko to n yan igbimọ ẹlẹni mọkanlelọgọta kan ti yoo ṣeto apero ẹgbẹ ọhun to n bọ lọna ni ọọfisi ẹgbẹ naa to wa niluu Abuja. Gẹgẹ bo ṣe sọ, ẹgbẹ eṣelu APC ni lati wa lori ipo fun ọpọ ọdun ki ijọba tiwantiwa to ti bẹrẹ lati ọdun 2015 le fẹsẹ mulẹ daadaa. O ṣalaye pe awọn gbe igbimọ naa kalẹ ki wọn le mu ipinu naa ṣẹ. Lara awọn to wa ninu igbimọ ọhun ni awọn gomina, minisita, ṣenatọ atawọn agbagba oloṣelu, eyii ti gomina ipinlẹ Jigawa, Muhammadu Badaru Abubakar ṣe olori wọn. Lati igba ti wọn ti yan gomina ipinlẹ Yobe yii gẹgẹ bii alaga fidihẹ ẹgbẹ APC ni awọn awuyewuye kan ti n waye ninu ẹgbẹ naa. Ṣugbọn o ti n gbiyanju lati ri daju irẹpọ wa ninu ẹgbẹ ọhun. Àwọn ọ̀rọ̀ Yorùbá kan wà tí ẹ kò lè lò pọ̀ mọ́ ara wọn, àwn ọ̀rọ̀ tẹ́ẹ lè fi rọ́pò rèé",0,yoruba "RT @user: @user Pípẹ́ ni yóò pẹ́, akólòlò yóò pe bàbá ni orile ede wa NIG. Ni agbara Olorun @user #TweetYoruba""""""""""""""""",0,yoruba "Bayii ni Chelsea ṣe dijgbaju olooyi ru Manchester City nini ifẹsẹwọnsẹ aṣekagba UEFA Champions to waye lalẹ ọjọ Abamẹta ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu karun ọdun 2021. Ninu idije Premier League ni Chelsea ti kọkọ fagba han Man City lẹyin ti Thomas Tuchel di akọnimọọgba Chelsea. Kẹrẹ kẹrẹ, Man City ati Chelsea tun pade nini ipele to kangun si aṣekagba idije FA Cup, iya naa lo tun bade fun Man City lọwọ Chelsea. Ọpọ lo ti ro pe ina eṣi ko le jo Man City nigba mẹta lere wọn, amọ ina yii jo wọn raurau nio. Aṣeju Pep Guardiola ṣakoba fun Manchester City Ọpọ onimọ nipa ere bọọlu ni wọn ti di ẹbi ru olukọni Man City, Pep Guardiola fun aṣeju nipa bi o ṣe maa n to awọn agbabọọlu to maa n lo fun awọn ifẹsẹwọnsẹ to lamilaaka. Iru iṣẹlẹ yii ti ṣẹlẹ fun igba meji ninu idije Champions League nigba ti ẹgbẹ agbabọọlu Lyon ati Monaco lo City jade ninu idije naa lai ro tẹlẹ. This is Chelsea's second Champions League win after winning the title in 2012 Ohun to ya gbogbo eeyan lẹnu to fi mọ olukọni Chelsea fun ra rẹ, Tuchel ni pe Guardiola ko fi agbaọjẹ agbabọọlu arin gbungbun rẹ Fernandinho sara awọn to bẹrẹ ifẹsẹwọnsẹ aṣekagba Champions League ọjọ Abamẹta. Ohun to tumọ si nipe ko si agbabọọlu to le di aarin mu fun City ni wọn igba ti o jẹ pe Rodri tabi Fernandinho ko si nibẹ. Eyi lo ṣakoba fun City nitori ti wọn ba ti lọ siwaju bayii ni Chelsea ri ọna lọ si ile wọn lati ṣe wọn ni suta. Apa keji ere bọọlu naa ni Guardiola gbe Fernadinho wọle, ṣugbọn ẹpa ko boro mọ.",0,yoruba iṣẹ́ ṣẹlẹ ni Eko ti gbogbo eniyan sọ o dara. (2008),0,yoruba "Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Nitori eyi, ara eni lo ni ẹ̀ká àwẹ eyti o gbe lori ọ̀run.",0,yoruba Kí ní fa aáwọ̀ àárín-in Ifẹ̀ àti Modáẹ́kẹ́? Eré gbogbo d'ọ̀la láago kan ọ̀sán. #Itan #Yoruba #IjaIfeOyo,0,yoruba "Àbẹ́òkúta. Nitori eyi, ara eni lo ni ìgbà mi owó àkokò, Alàji lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn.",0,yoruba "RT @user: ✅Ọ̀bẹ ń wó ilé araa rẹ̀, ó ní òun ń ba àkọ̀ nínú jẹ́. ✅Àdá l'ẹnu tálákà, igbó la ó fi dá. ✅Bí ọwọ́ ẹni ò bá tẹ èkù idà, k…",0,yoruba obìnrin a yi yi ti o nuni ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo.,0,yoruba "ọ̀ṣun ìlú. Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba "kún jú, àwọn ènìyàn ni ó pa Ìyá lo ni àṣà yorubá eyti o gbe lori ọ̀run dídì.",0,yoruba "Agbnusọ fun ajọ naa, Fabian Benjamen, sọ wi pe ajọ naa n gbiyanju lati ri wi pe gbogbo esi idanwo t'awọn eeyan ṣe jade lori opo ayelujara rẹ. Ninu ọrọ to ba ileese iroyin Naijiria (NAN) sọ, Ọgbẹni Benjamin sọ wi pe awọn esi idanwo kan yoo jade titi ọjọ kọkandinlogun oṣu keta yii. Idi ti esi idanwo Jamb yoo se pẹ ko to jade O ṣi ṣe ileri wipe wọn n tin ṣatunṣe lori gbogbo ipenija ẹrọ ti awọn eeyan n ko lori opo ẹrọ ayelujara rẹ l'ọwọ-l'ọwọ bayii. Awọn kan ninu awọn ti wọn ko idanwo na ti kọkọ sọ wipe awọn ko ri esi idanwo wọn gba. Wọn pari idanwo naa lọjọ Abamẹta dipo ọjọ Aiku ti wọn fisi tẹlẹ.",0,yoruba Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó ṣe pàtàkì. (Item 116),0,yoruba "ko si si olukọ kankan ninu awọn yara ikẹkọ lati sisẹ ni ọgba fasiti Ibadan Ipade naa to bẹrẹ ni irọlẹ Ọjọ Aje naa jẹ ọna lati wa wọrọkọ fi se ada lori awọn ohun ti ẹgbẹ osisẹ ASUU n beere fun ti wọn fi gunlẹ iyansẹlodi. Aarẹ gbogboogbo fun ẹgbẹ olukọ fasiti lorilẹede yii, ASUU, Ọjọgbon Biodun Ogunbiyi sọ wi pe, ipade naa si n tẹsiwaju lọjọ miran nitori pe wọn ko i tii yanju aawọ naa. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Jide Kosọkọ: Isẹ́ tíátà yóò gòkè tíjọba bá gbówó kalẹ̀ láti seré Asoju fun ijọba apapọ to jẹ Minisita fun Eto Ẹkọ , Malam Adamu Adamu ni, awọn yoo tẹsiwaju pẹlu ifọrọjomitoro ọrọ lọjọ iwaju lati wa opin si iyansẹlodi naa. Ẹgbẹ osisẹ fasiti naa n beere fun owo isuna to gbooro fun ile ẹkọ giga ati sisan owo ajẹmọnu awọn olukọ fasiti. Àwòrán díẹ̀ lára àwọn ǹkan ti ASUU ń jà fún nì yíi Ọpọlọpọ ni kò mọ pe atunṣe sawọn ọgba ile iwe giga ni koko nkan ti ẹgbẹ awọn olukọ fasiti ni àwọn n jà fun lasiko yii. Kilaasi kan ni yi ni Fasiti ikọni nimọ ijinlẹ sayẹnsi ni Fasiti Pọta nipinlẹ Rivers. Ipo ti àwọn ohun eelo ikẹkọọ wa ni wọn gba pe ko dara tó. Iyara akẹkọọ kan ni Block G ni nibugbe awọn akẹkọkunrin ni Fasiti Bayero ni Kano Awọn to ti kawe nilẹ okeere ni àwọn ile ti awọn akẹkọọ Naijiria n gbé kò bọ sii rara. Gbongan kilaasi kan ni yi ni Fasiti ikọni nimọ ijinlẹ sayẹnsi ni Fasiti Pọta nipinlẹ Rivers. Ọrọ atunṣe awọn iyara ikawe yii yẹ ko kari gbogbo fasiti ni. Kilaasi kan ni yi ti wọn ti n kọ akẹkọọ ni imọ kẹmisitiri ni Fasiti Bayero nipinlẹ Kano Koda ko yọ àwọn ibi to yẹ ki akẹkọo ti kọ ẹko nipa afojuri iṣẹ silẹ. Ibudo ayẹwo fun ikọni nipa itọju ẹranko ni Fasiti Pọta nipinlẹ Rivers Kikọ ni mímọ̀ ni ọrọ àwọn iṣẹ itọju ẹranko ni ayika to jẹ ki ẹkọ dun lati kọ. Ibudo ayẹwo fun ikọni nipa itọju ẹranko ni Fasiti Pọta nipinlẹ Rivers Awọn nkan wọnyii ni àwọn olukọ ASUU gba pé o fa iyanṣẹlodi ti awọn gunle, yatọ si ti owo ajẹmọnu ti wọn. Ibudo ayewo fawọn akẹkọọ imọ iṣegun oyinbo ni Fasiti Pọta. Abọ ipade ASUU lọjọ kejilelogun, oṣu kọkanla: ASUU kọ̀ láti fopin si iyanṣẹlodi ti wọn gunle. Ọga agba ẹgbẹ awọn olukọ fasiti, ni fasiti ọlọgba ẹranko ni Ibadan, Deji Omọle ti ṣalaye fawọn eniyan pe iyanṣelodi n tẹsiwaju. O sọ eyi di mimọ leyin ipade ti ẹgbẹ ṣe pelu ikọ̀ ijọba apapọ ni ileeṣe ijọba apapọ to n mojuto eto ẹkọ ni Naijiria, eyi to wa nilu Abuja. Eyi ni igba keji ti ikọ ijọba maa ṣe ipade pẹlu egbẹ ASUU ṣugbon to n fori ṣọnpọn. O ni ohun ti ASUU n fẹ ni ki ijọba to wa lori oye yii mu ileri to ṣe lọdun 2017 ṣẹ lasiko. Ọ̀pọ̀ òṣìṣẹ́ elétò ìlera ló ti n lo tọ̀nà ìgbàlódé láti fiṣe àkọsílẹ̀ Ipade mii ti wọn fẹ ṣe lọjọ kejilelogun, oṣu kọkanla. Ni ọgba ileeṣẹ ijọba apapọ to n mojuto eto ẹkọ, nilu Abuja ni ipade naa yẹ kó ti waye. ọ̀dọ́ ni agbara orilẹ-ede nibi ti eto ẹkọ ti ṣe koko Lọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu yii ni wọn ṣe ipade gbẹyin ni eyi ti wọn ko fẹnu ọrọ jona si. Ọjọgbọn Biọdun Ogunyẹmi, to jẹ aarẹ ẹgbẹ àwọn olukọ ni Naijiria ni ipade naa yoo fun wọn laaye lati yanju ọrọ iyanṣẹlodi to n lọ lọ́wọ́. Igbakeji agbẹnusọ fun ile iṣẹ ijọba apapọ to n risi eto ẹkọ ni Naijiria, Ben Going ni oun gbagbọ pe, loni ni gbogbo ọrọ naa a yanju. Ikọ ijọba apapo ti minista fun ọrọ awọn oṣiṣẹ, Chris Ngige n ṣaaju ni yoo ba wọn ṣe ipade. Ọba Olutayọ: ìgbésẹ̀ Ọọni àti Alaafin ti ń mú ìṣọ̀kàn dé sáàrin àwọn Ọba Yorùbá ASUU Strike: Bí àwọn kan se dunnú, làwọn kan fajúro Ìjọba àpapọ̀ ti ṣèpàdé pẹ̀lú àwọn adarí ẹgbẹ́ àwọn oṣìṣẹ́ fásitì Nàìjíríà lórí ìyanṣẹ́lódì àwọn ilé ìwé giga ti ìjọba tó bẹ̀rl lọ́jọ́ kẹrin, oṣù kọ́kànlá. Àwọn tó wà níbi pàdé pàtàkì yìí tí wọ́n ṣe ní ìdákọ́nkọ́ ni Ààrẹ ẹgbẹ́ àwọn òṣìṣẹ́, ọ̀jọ̀gbọ́n Biodun Ogunyemi tó dári ikọ̀ náà. Ìgbé ayé Instagram fún ọ́sẹ̀ kan Àwọn míì tó wà níbi ìpàdé ọ̀hún ni olùṣirò owó àgbà ti orílẹ̀èdè yìí àti akọ̀wé àgbà ilé iṣẹ́ tó ń rí sí ètò ẹ̀kọ́. Àwọn olùkọ fásitì bẹ̀rẹ̀ ìyanṣklódì náà ní láti jà fún àìṣe àmúṣẹ àwọn àdéhùn lórí ìtọjú àwọn òṣìṣẹ́. Ẹ̀wẹ̀, àwọn olùkọ́ni náà gbàgbọ́ pé ìpàdé mìí tí wọ́n yóò ṣe lọ́sl tó mbọ̀ yóò so èso rere eléyìí tí mínísítà fúnrarẹ̀ yóò wà níbẹ̀. Màá gbé ASUU lọ'lé ẹjọ́ bí wọ́n bá dí mi lọ́wọ́ iṣẹ́ 'Èmi kìí ṣe ọmọ ẹgbẹ́ ASUU' Ajeje ọwọ kan ko gbẹru dori, agbajọ ọwọ ni aa fi n sọya ni Yoruba maa n wi. Ṣugbọn bii ti Ọjọgbọn Sunday Edeko olukọni ni fasiti Ambrose Ali nipinlẹ Edo kọ, lẹyin to kilọ fun ajọ ASUU pe oun ko fọwọ si iyanṣelodi ti wọn gunle. Ọjọgbọn Edeko ni ajọ ASUU ko lẹtọ labẹ ofin lati di oun lọwọ nibi ti oun ba ti n kọ awọn akẹẹkọ, nitori oun kii ṣe ọmọ ẹgbẹ ajọ naa. O kilọ pe oun yoo gba biliọnu mẹwaa owo naira ti ajọ naaba tun di oun lọwọ iṣẹ. ASUU, CONUA tako ara wọn lórí iyansẹ́lódì Lọjọ aiku ni ASUU paṣẹ ki gbogbo awọn olukọ fasiti lorilẹede Naijiria o gunle iyanṣẹlodi Ede aiyede diẹ bẹ silẹ lọgba fasiti Ọbafẹmi Awolọwọ to wa nilu Ilẹ Ifẹ lori iyanṣẹlodi ẹgbẹ olukọni fasiti, ASUU to n lọ lọwọ. Ọjọ iṣẹgun ni awọn olukọ labẹ ASUU lọgba fasiti naa to darapọ mọ iyanṣẹlodi lẹyin ipade wọn. Wọn ni ko si idi fun awọn lati ma lee darapọ mọ iyanṣẹlodi naa ati pe awọn ti paṣẹ fun awọn akẹkọ lati gba ile lọ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Amọṣa ẹgbẹ awọn olukọ fasiti miran eleyi to yapa kuro lara ẹgbẹ ASUU ni fasiti naa, ti wọn si pe orukọ ara wọn ni Congress of University Academy (CONUA) pẹlu gbe ikede jade pe digbi ni awọn wa lẹnu iṣẹ ni tawọn nitori aṣẹ ASUU ko kan awọn. ASUU ṣalaye pe o di igba ti ijọba apapọ ba mu adehun to baa ṣe ṣẹ ki awọn to pada si ẹnu iṣẹ Bakan naa ni wọn tun paṣẹ pe eyikeyi akẹkọ to ba lọ sile yoo da ara rẹ lẹbi ni nitori pe, ""igbimọ alaṣẹ ileewe fasiti yii nikan lo lee paṣẹ pe ki awọn akẹkọ maa lọ sile."" Alaga ẹgbẹ ASUU ni fasiti naa, Ọmọwe Adeọla Ẹgbẹdokun ṣalaye pe o di igba ti ijọba apapọ ba mu adehun to ba ẹgbẹ olukọ fasiti ṣe ṣẹ ki awọn to pada si ẹnu iṣẹ gẹgẹ bii igbimọ apapọ ẹgbẹ naa ti ṣe dari. Ọmọwe Niyi Sunmọnu to jẹ alaga Congress of University Academy (CONUA) ṣalaye pe ko si olukọni ti o lagbara lati paṣẹ ki akẹkọ maṣe wa sile iwe ati pe ẹni to ba jẹ ninu owo adebisi nii pe ni baba layẹyẹ. Eyi tunmọ si wi pe awọn olukọni fasiti to ba wa labẹ ẹgbẹ ASUU nikan ni aṣẹ wọn mulẹ le lori. ASUU Strike: Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ kan dunnú, àwọn míràn fajúro ko si si olukọ kankan ninu awọn yara ikẹkọ lati sisẹ ni ọgba fasiti Ibadan Ẹgbẹ awọn olukọ ilẹ ẹkọ giga fasiti ijọba lorilẹede Naijiria (ASUU), ẹka ti fasiti Ibadan (UI), naa darapọ mọ awọn akẹgbẹ wọn jakejado orilẹede yii ninu iyanṣẹlodi alainigbedeke to bẹrẹ lọjọ aje. Wọn dẹgun le iyanṣẹlodi naa lati fi ẹhonu han lori ikuna ijọba lati mu adehun ṣẹ.Lasiko ti ikọ iroyin BBC Yoruba ṣe abẹwo si ọgba ile ẹkọ giga naa lowurọ ọjọ aje, ẹnu ọna abawọle ile ẹkọ naa wa ni ṣiṣi silẹ, bẹẹ si ni ọgọrọ awọn akẹkọ n rin sokesodo, bo tilẹ jẹ wipe ko si olukọ kankan ninu awọn yara ikẹkọ to n bẹ ninu ọgba ile ẹkọ naa. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ireti Yusuf: Ìsòro àti fẹjọ́ sùn ló ń mú kí ìwà ìfipábánilòpọ̀ gbilẹ̀ si ASUU ati SSANU kọ̀ lati sọ̀rọ̀ Gbogbo igbiyanju lati ba awọn aṣoju ẹgbẹ ASUU, ẹka ile ẹkọ giga naa sọrọ lo ja si pabo, gẹgẹ bi ọkan lara awọn aṣoju ẹgbẹ naa, Deji Ọmọle ṣe s'alaye wipe ko tii t'asiko lati ba awọn oniroyin sọrọ.Bakan naa ni ikọ BBC Yoruba ṣe abẹwo si ofisi ẹgbẹ awọn olukọ agba(SSANU) ẹka ti fasiti ilẹ Ibadan, lati le mọ iha ti wọn kọ si iyanṣẹlodi naa, sugbọn awọn ọmọ ẹgbẹ kọ lati ba oniroyin sọrọ nitori alaga wọn ko si lori ijoko. Awọn ontaja ati awakọ lọgba fasiti fi igbe ta Amọ lara awọn ontaja to ni sọọbu ninu ọgba ile ẹkọ giga naa gbarata lori ipa buburu ti iyanṣẹlodi naa yoo ko lori iṣẹ wọn. Se lawọn akẹkọ fasiti Ibadan duro gogogo lai mọ ohun ti wọn yoo se Alaye wọn ni wipe, igbesẹ naa le dina atijẹ mọ wọn, nitori wipe nipasẹ ọja ti wọn ta fun awọn akẹkọ ni wọn fi n ri ọwọ mu lọ sẹnu, gẹgẹ bi wọn ṣe n l'anfani lati tọ awọn ọmọ ti wọn naa pẹlu. Wọn parọwa si ijọba lati wa ojutu si ọrọ iyanṣẹlodi naa, ki o ma baa ṣe akoba fun okoowo wọn.Awọn awakọ ero naa ko gbẹyin ninu awọn eeyan to n rawọ ẹbẹ s'ijọba lori iyanṣẹlodi Asuu, gẹgẹ bi wọn ṣe fi kun ọrọ wọn wipe, wọn ko ni ri iṣẹ ṣe ti gbogbo akẹkọ ba fi ọgba ile ẹkọ naa silẹ nipasẹ iyanṣẹlodi awọn olukọ wọn. Ero awọn akẹkọ yapa lori iyansẹlodi ASUU Ariwisi awọn akẹkọ ṣe ọtọọtọ ninu ifọrọwanilẹnuwo ti ikọ BBC Yoruba ṣe pẹlu diẹ lara awọn wọn lori iyanṣẹlodi naa.Lara wọn sọ wipe, inu awọn dun si iyanṣẹlodi naa nitori wipe yoo fun wọn l'anfani lati lọ sinmi fun igba diẹ, sugbọn wọn ko fẹ ki isinmi naa kọja ọsẹ meji si mẹta. Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ kan dunnú, àwọn míràn fajúro si iyansẹlodi Asuu Awọn akẹkọ mii ṣe alaye wipe, ifasẹhin nla gbaa ni iyanṣẹlodi naa yoo jẹ fun eto ẹkọ wọn nitori wipe wọn tii n gbaradi fun idanwo ki ẹgbẹ awọn oluko to da iṣẹ silẹ.Bi awọn kan ṣe n rin sokesodo ninu awọn akẹkọ naa, ni awọn ẹlomii n gba bọọlu lori papa iṣere ile ẹkọ giga naa nitori airi iṣẹ ṣẹ lowurọ ọjọ Aje. ASUU ni ipò tí kò dára táwọn fásitì wa lawọn ń jà fún Apapọ ẹgbẹ́ awọn olukọ ni fasiti jakejado Naijiria, Academic Staff Union of Universities, ASUU, ti kede iyanṣẹlodi alainigbedeke ni gbogbo ẹka wọn. Gẹgẹ bi wọ́n ṣe sọ, iyanṣẹlodi naa jẹ ọna lati fẹhonu han lori ipo ti awọn fasiti orilẹede Naijiria, nitori bi ijọba ko ṣe maa nawo le wọn lori daada. Latẹnu Aarẹ Apapọ ẹgbẹ́ naa, Ọjọgbọn Biọdun Ogunyẹmi, ni ASUU gba kede iyanṣẹlodi ọhun, lopin ipade igbimọ alaṣẹ gbogboogbo to waye lọjọ kẹrin, oṣu Kọkanla, ọdun 2018, ni Fasiti Imọ Ẹrọ, FUTA, to wa niluu Akurẹ, nipinlẹ Ondo. Wọn pa a laṣẹ fun gbogbo awọn olukọ ni fasiti jakejado orilẹede Naijiria, lati ṣiwọ iṣẹ loju ẹsẹ ti aṣẹ naa jade. Aarẹ ẹgbẹ́ naa, gẹgẹ bi iwe iroyin Punch ṣe jabọ̀, sọ fun awọn akọroyin pe, awọn yoo fi iyanṣẹlodi ọhun naa tan bi owo pẹlu ijọba, lẹyin ti awọn reti idunadura to nitumọ, ṣugbọn ti ko waye. Oṣu Kẹsan, ọdun 2017 ni ẹgbẹ́ naa so iyanṣẹlodi to ṣe kẹhin rọ, wọn si n fẹ ki ijọba mu gbogbo adehun to sẹ fun wọn lọdun 2009 ṣẹ. Nkan o fararọ laarin ẹgbẹ awọn olukọni nileewe giga fasiti Ọbafẹmi Awolọwọ, OAU nilu Ile ifẹ. Ẹgbẹ olukọni nileewe giga fasiti Ọbafẹmi Awolọwọ, OAU nilu Ile ifẹ ti fọ si meji bayii. Laipẹyii ni awọn olukọni labẹ isakoso ẹgbẹ awọn olukọni fasiti lorilẹede Naijiria, ASUU se ifilọlẹ awọn ọmọ igbimọ isakoso rẹ tuntun ninu eyi ti Ọmọwe O. A. Ẹgbẹdokun ti di alaga tuntun. Ni ọjọ kan naa ni ẹgbẹ miran to ya kuro labẹ ẹgbẹ ASUU ni fasiti naa ti wọn pe orukọ rẹ ni CONUA pẹlu yan awọn adari rẹ. Wahala ati ede aiyede bẹ silẹ laarin awọn olukọni ileewe fasiti OAU lasiko ti awuyewuye suyọ lori ẹni ti yoo se giwa ileẹkọ naa ni ọdun 2017. Ni ọsẹ to kọja ni ẹgbẹ CONUA de'lẹ lẹyin ti awọn olukọni fasiti ọhun kan ti ni awọn o faramọ bi nkan se n lọ laarin ẹgbẹ ASUU Bi igun-igun kan an kan laarin awọn olukọ fasiti naa se faramọ ọkọọkan awọn to n du ipo ọhun nigba naa, lo fa iyapa to way laarin ẹgbẹ olukọni fasiti, ASUU nibẹ. Lẹyin ọpọlọpọ hilahilo eleyi ti o fẹrẹ la ti isiwọluni lọ nigba naa,ni ẹgbẹ ba tuka si meji, ASUU gan an gan ati CONUA. Ni ọsẹ to kọja ni ẹgbẹ CONUA ni awọn o faramọ bi nkan se n lọ laarin ẹgbẹ naa, ni wọn fi da ẹgbẹ tuntun yii silẹ. Ninu ọrọ rẹ to sọ fawọn oniroyin, alaga ẹgbẹ ASUU nileẹkọ fasiti Ilọrin, UNILORIN, ọmọwe Usman Raheem ni 'wọn ti sọ ẹgbẹ ASUU di ẹgbẹ awọn alagbara kan.' Amọsa alamojuto ASUU ni ẹkun iwọ oorun gusu Naijiria, Ọmọwe Alex Odili se apejuwe awọn olukọni to wa ni ẹgbẹ tuntun naa gẹgẹbii awọn ti ko ni ẹkọ tio rọ mọ ẹka imọ iwe. Kii se ohun tuntun mọ wipe awọn ẹgbẹ ajafẹtọ osisẹ n fọ kaakiri bayii lorilẹede Naijiria, gẹgẹbi ati se rii ni aarin apapọ ẹgbẹ osisẹ gan an lorilẹede Naijiria, iyẹn NLC pẹlu.",0,yoruba "WHO DO WE EULOGIZE THIS WAY: Ọmọ gb'élé gbé ìgbẹ́, ọmọ gbé ní oko, gbé ní ijù - Iwájú jí ẹ̀ṣọ́ ti ń gba ọ̀tá. Ẹ̀ṣọ́ kan kìí gba ọta láti ẹ̀yìn - Ọmọ arógun jó, ọmọ arógun yọ̀ -Ọmọ agbogun ṣ'owó ṣe Ọmọ aṣáájú ogun, máà kẹ́yìn ogun?",0,yoruba "Asiko ọdun Ajinde ni awọn onigbagbọ ma n ṣe ajọdun ajinde Jesu Kristi kuro ni ipo oku, ti Iwe Mimọ Bibeli sọ wipe Jẹsu Kristi ku lori igi agbelebu ni Ọjọ Ẹti rere, Good Friday. Gẹgẹ bi bibẹli ṣe sọ, Jesu Kristi jinde ni ọjọ kẹta kuro ni ipo oku, ti o si jasi Ọjọ Ajinde. Ni ọdọọdun, ọdun Ajinde ma n yatọ to si ṣeeṣe ko waye lọjọ kan laarin ọjọ kọkanlelogun, Oṣu Kẹta si Ọjọ karundinlọgbọn, Oṣu Kẹrin, eleyii ti awọn kan gbọgbọ wipe o niṣe pẹlu bi irawọ ba ṣe tan imolẹ si(Full Moon). Lasiko ọdun Ajinde, awọn Kristẹni ma n darapọ lati gbadura ki wọn si jọ jẹun papọ. Toripe ṣaaju asiko naa, wn ti wa ninu awẹ Lẹnti Ọgbọn ọjọ gẹgẹ bi Jesu Kristi naa ṣe gba a ninu iwe mimọ. Amọ, ajakalẹ arun Coronavirus le mu ki ọpọlọpọ eniyan ma lọ si ile ijọsin tabi ki wọn darapọ mọ isin ni ori ẹrọ ayelujara. Ki lo wa n jẹ ""Ẹyin"" ọdun Ajinde? Ni Ilẹ Yuroopu, ọpọlọpọ eniyan lo ma n jẹ ṣọkoleeti ẹlẹyin lasiko ọdun Ajinde lati fi ṣe ayẹyẹ ajinde Jesu Kristi. Ni igba ti asa ẹyin bẹrẹ, awọn adari ẹsin ni igba naa lọhun kii gba ki awọn eniyan jẹ ẹyin lasiko ọṣẹ ijiya Jesu, ti awọn oloyinbo n pe ni Holy Week. Nitori naa ohun ti awọn eniyan ma n ṣe ni lati lati ko awọn ẹyin ti adiye ba ye ni asiko yii pamọ, ti wọn a si ṣe e ni ẹsọ, ti wọn a si fun awọn ọmọde gẹgẹ bi ẹbun ni ọjọ Ajinde. Titi di oni ni awọn eniyan ṣi n ṣe e, ti wọn ṣi n fun awọn eniyan ni ẹbun ẹyin ni ọdun Ajinde. ""Ehoro"" nkọ, kini wọn fi ṣe ni Ọjọ Ajinde? Itan ehoro ajinde ni o wọpọ ni awujọ awọn eniyan ni ọdun 1900 lọhun. Awọn ehoro ma n bi ọmọ to ma n tobi ti awọn oloyinbo n pe ni (kitten), ti awọn eniyan si ri wọn gẹgẹ bi ibẹrẹ igbeaye tuntun. Itan sọ fun wa pe awọn ẹyin ti ehoro ba ye ni asiko yii, ehoro ma n ṣe e ni ẹsọ ti asi lọ gbe e pamọ. Nitori naa awọn ọmọ kekeeke ma n wa ẹyin ehoro kaakiri lasiko ọdun ajinde.",0,yoruba "Agbegbe Mosafẹjọ ni Oshodi ni iṣẹlẹ naa ti waye. Gẹgẹ bi awọn iroyin abẹle kan ṣe sọ, awọn ologun naa ya bo Oshodi ""lati gbẹsan iku ọmọogun ofurufu kan, ti awọn janduku pa lagbegbe naa"" Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọpọlọpọ ọkọ ero ni wọn bajẹ tawọn awakọ ero si sa fi skọ silẹ, bẹẹ lawọn ọlọja pẹlu juba ehoro ti wọn si fi ṣọọbu wọn silẹ. Awọn miran sọ pe wọn ri oku ọmọogun naa ni agbegbe naa ti awọn eeyan si fura pe awọn janduku lo gba ẹmi rẹ ki wsn to fi awọn ṣọja naa ṣọwọ sibẹ lati lọ gbe oku rẹ ki wọn si le awọn janduku kuro lagbegbe naa. Amọṣa ileeṣẹ ọlọpaa ti fi atẹjade kan sita pe awọn ti bẹrẹ si ni wadi ohun gan to fa wahala naa. Oyo LG Polls: OYSIEC ní APC ló yẹ kò bẹ aráàlú lórí àṣìṣe rẹ̀ nípa ìbò ìjọba ìbílẹ̀ Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Eko, Muyiwa Adejọbi ṣalaye ninu atẹjade naa pe, "" Ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Eko gbọ si wahala to waye lagbegbe Capa Park/Mosafẹjọ ni Oshodi loni Ọjọbọ ogunjọ oṣu karun un ọdun 2021 ni agogo meje owurọ. A ti da alaafia pada si agbegbe naa, a si n ṣe iwadii lori rẹ. A rọ awọn olugbe ilu Eko lati maa ba iṣẹ wọn ls laisi wahala.""",0,yoruba yi gbe ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọba lo lọ.,0,yoruba Àwọn Irinṣẹ́ Ètò Kọ̀ǹpútà,0,yoruba "ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba New slang : Shey o n whine mi ni #Yoruba #Africa ♤,0,yoruba ọba. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni.,0,yoruba "tó kún jú, àwọn ènìyàn yì í tún ṣe àwọn iṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..",0,yoruba dara. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọba lo tun se fi.,0,yoruba ni òun tí a kọ eḳọ nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.,0,yoruba Wo obìnrin tó bí ìbaàrún lẹ́yìn tó bí ìbejì lẹ́ẹ̀mejì àti ọmọ mẹ́sàn-án mìí,0,yoruba RT @user: @user Oju wa l'ona o!,0,yoruba "Iroyin fi idi rẹ mulẹ pe mẹta ninu awọn to wa ninu ọkọ oju omi to dojude naa ni wọn doola ẹmi wọn. Awọn mẹrin lo wa ninu ọkọ oju omi naa lasiko ti ijamba naa fi waye ṣugbọn wọn ṣi n wa ẹni kẹrin wọn bayii. Iji nla to ja lori omi naa lasiko irinajo wọn ni wọn ni o ṣokunfa idojude ọkọ naa. Awọn alaṣẹ ajọ to n mojuto igbokegbodo ọkọ oju omi nipinlẹ Eko, LASWA atawọn ajọ miran la gbs pe wọn pawọ pọ ṣe bẹbẹ ni kete ti ijamba naa ṣẹlẹ lati doola awọn to wa ninu ọkọ naa. Lasiko ti a fi n ko iroyin yii jọ, awọn omuwẹ ṣi n wa eeyan kan to ku ninu ọkọ oju omi naa.",0,yoruba "Badenosh yii lo jẹ ọmọ ẹgbẹ oselu Conservative ati ọmọ ile asofin apapọ nilẹ Gẹẹsi, eyi to n soju ẹkun idibo Saffron Walden. Olukemi Olufunto Badenosh, tii se ẹni ọdun mọkandinlogoji ni Boris Johnson yan gẹgẹ bii minisita fun awọn ọmọde ati mọlẹbi. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Lara ojuse minisita tuntun yii si ni sise agbekalẹ ofin to nii se pẹlu igba ewe awọn ọmọde, abẹwo wọn ati ofin to de akoso wọn. Nigba to n kede iyansipo tuntun naa ni oju opo Twitter rẹ, Olukemi Olufunto Badenosh @KemiBadenoch fi idunnu rẹ han si ipo nla ti Olootu ijọba Gẹẹsi yan si ọhun. ""Pẹlu iwa irẹlẹ ni mo fi gba ipo minisita kekere ti wọn yan mi si. Anfaani nla ni eyi fun mi lati sisẹ sin, ki n si mu iyatọ rere ba ọpọ isẹlẹ to n waye eyi to jẹ mi logun. Mo n fi oju sọna lati sisẹ pẹlu ikọ awọn minisita ati ẹnikọọkan to wa lẹka eto ẹkọ nilẹ Gẹẹsi."" Ọṣu Kinni ọdun 1980 ni wọn bi Olukemi Olufunto Badenosh. Orukọ baba ati iya rẹ ni Fẹmi ati Feyi Adegoke. Ilu Eko ati ilẹ Amẹrika lo ti lo igba ewe rẹ, ko to di pe wọn gba ilẹ Gẹẹsi lọ nigba ti Olukẹmi wa lọmọ ọdun mẹrindinlogun.",0,yoruba "7. Wọ́n á máa ní """"""""""""""""""""""""""""""""owó Àbú ni a fi ń ṣe Àbú lálejò"""""""""""""""""""""""""""""""", ǹjẹ́ o lè sọ àwọn tí a máa ń pè ní Àbú ní ilẹ̀ẹ káàárọ̀ o ò jí ire? #Ibeere #Yoruba",0,yoruba àsa. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó ṣe pàtàkì.,0,yoruba "Yàtọ̀ sí oúnjẹ tí a gbọ́, t'ó ní ìwúkàrà nínú, tí a ń pè ní àkàrà, a ní oríṣiríṣi àkàrà ìbílẹ̀. #AlayeOro #Akara #Yoruba",0,yoruba "Àṣìlò òògùn: Ará ìlú sọ oun tó ń sún wọn dé'dí ìwà yí Awọn oniṣegun oyinbo ti n bẹnu atẹ lu aṣilo oogun lati ọjọ to ti pẹ, ṣugbon awọn ara ilu to ba ikọ BBC sọrọ ni wahala ti oju awọn n ri ti wọn ba lọ ile iwosan lo faa ti awọn fi di ẹni to n ṣi oogun lo. Awọn oniṣegun meji, Dokita Yetunde Adeniyi ati dokita Tope Ojo fesi si ọrọ yii, wọn ni, bo ti lẹ jẹ pe nitootọ ni pe oun ti oju ara ilu n ri lati gba iwosan ni awọn ile iwosan ko rọrun, ọpọlọpọ ewu lo wa nidi aṣilo oogun. Àwọn dọkítà ní bó tilẹ̀ jẹ́ pe àṣìlò òògùn kìí ṣe ẹ̀bi awọn ará ìlú, ó mú ewu púpọ̀ dání Àwọn iroyin miiran ti é le nifẹ si: 'Ọ̀gá ni mí nínú àwọn ẹlẹ́rìín lágbàáyé'",0,yoruba "@user: @user - Tẹ #link àwòrán náà, á darí rẹ lọ sí #webpage tí ó wà. Wà á sì #save :)",0,yoruba "Yoruba bọ wọn ni oju ni alakan fi n ṣọri, eyii lo mu BBC Yoruba kan si akọṣẹmọṣẹ kan nipa eto abo, lori awọn ohun to yẹ ki eeyan ṣe fun abo ara wọn bi ọdun ṣe n pari lọ yii. Babatunde Akande, to jẹ alaṣẹ ileeṣẹ eto abo aladani Europa Security Guard, sọ awọn ohun to yẹ ki awọn ara ilu ṣe atawọn nnkan ti ko yẹ ki wọn ṣe fun abo ara wọn. Akande kọkọ gba awọn eeyan niyanju lati maa tọju awọn ọlọde to n ṣọ ile wọn. WHO ta bayar da shawarar mutane su gana da juna ta intanet O ni ""Ẹma fi ebi pa ọlọdẹ to n ṣọ ile yin lọdun yii o, ẹ ma sọ pe ṣebi o n gba owo oṣu."" Bakan lo kilọ pe ki awọn eeyan maṣe rinrin ajo ti ko ba ṣe pataki. O ṣalaye pe ""kii ṣe gbogbo irinajo ni eeyan n lọ lasiko yii."" ""Ẹ le fi owo ranṣẹ si ẹni to ba yẹ ki ẹ ṣabẹwo si ti abẹwo naa ko ba pọn dandan."" 'Ọ̀lọ́pàá shátà mi láti Mowe dé Magboro dé Shagamu, wọ́n ní ṣé mi ò mọ̀ pé ìjọ́ba ni mo ṣiṣẹ́ fún' Bẹẹ lo ni ki awọn eeyan ṣora nipa ohun ti wọn a maa sọ ni gbangba. ""Ẹni to wa nile ọti to n dan ẹnu nipa iye owo to wa ninu apo banki rẹ kan n fi ara rẹ sinu ewu ni, nitori ko mọ irufẹ eeyan to wa layika rẹ nigab to n sọrọ."" Amoye nipa eto abo naa tun ṣalaye pe ki awọn eeyan maa gbiyanju lati maa pa iye owo to wa ninu apo ifowopamọ banki wọn rẹ lori ẹrọ alagbeka wọn. 'Pásítọ̀ ló sọ fún mi pé Ọlọ́run pè mí láti di Olokun tó ń bọ omi' O ni ki awọn eeyan ṣora nipa iye owo ti wọn yoo maa da nibi ipade adugbo, bi wọn ṣe nawo nibi ariya ati awọn aṣọ to maa n ṣafihan bi wọn ṣe lowo si. Ni ti ori ayelujara, Akande sọ pe ""ẹ ṣọra fun irufẹ ohun ti ẹ o maa fi lede loju opo Facebook."" ""Ẹlomiran yoo maa fi gbogbo igbesi aye rẹ sori Facebook."" ""Fun apẹrẹ, awọn kan maa n fi ibi ti wọn wa ati ibi ti wọn n lọ sori Facebook, eyii ko daa to."" Wo àwọn ọ̀nà mẹ́fà tí o lè gbà dáàbò bo ara rẹ bí ọdun ṣe ń lọ sópin Ni bayii ti ọdun keresimesi ati ayẹyẹ opin ọdun ku ọjọ perete, ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria ti kede awọn ohun mẹfa to yẹ ki awọn ara ilu ṣe lati dabo bo ara wọn lopin ọdun. Ọjọ Iṣẹgun ni ọọfisi ileeṣẹ ọlọpaa to n ri si ọrọ iroyin fi atẹjade naa lede niluu Abuja. Ninu atẹjade ọhun ni wọn ti ṣalaye awọn ohun ti awọn eeyan le ṣe fun abo ara wọn, paapaa awọn to n rinrinajo ile ọdun, ni ibudokọ, papakọ ofurufu ati ibudokọ oju irin. Wo awọn nnkan ti ọlọpaa ni ki o ṣe lasiko ti ọdun n lọ sopin yii fun abo ara rẹ: Lẹyin ti ileeṣẹ ọlọpaa fi ọrọ naa lede tan ni wọn tun fi fido yii lede pẹlu.",0,yoruba "Ní ọjọ́ ìsinmi tí a wà yìí , mo gbọ́ wípé oníṣẹ́ - ìròyìn ọmọ Nàìjíríà kan kò le è wà níbí GlobalFact nítorí wípé kò ní ìwé ìrìnnà .",0,yoruba "Ipasẹ̀ ìró ọ̀rọ̀ ni kíkọ èdè sílẹ̀ fi wáyé, ọ̀rọ̀ tí a pè lẹ́nu ni ọmọ aráyé sọ di àmì tí a fi dá gbólóhùn kàn kan mọ̀. #EdeAbinibi #IMLD",0,yoruba aláwọ̀fin ló di aláàfin ló di àádùn,0,yoruba Nítorí orílẹ̀ èdèe tí ó gbajúmọ̀ jù lọ nílẹ̀ Adúláwọ̀ yóò yẹ̀ gẹ̀rẹ̀ sí ìjọba ìfipámúnisìn ní kété tí òmìnira ọ̀rọ̀ sísọ bá di títẹ̀ bọlẹ̀ .,0,yoruba "ayé ọ̀ṣun. Nitori eyi, ara eni lo ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba Àjọṣepọ̀ láàárín onírúurú èdè ti wà láti ayébáyé .,0,yoruba "Europa league: Ìjàmbà tún ṣe Ole àtàwọn ọmọ rẹ níwájú AZ Alkmaar, ọ̀mì ni wọ́n ta",0,yoruba dídì yìí ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba "Akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu Liverpool, Jurgen Klopp naa ti da si arayinjiyan ""ta lo dara ju"" laarin Lionel Messi ati Cristiano Ronaldo.Ko tii si opin si ariyanjuyan yii lẹyin tawọn mejeeji ti tayọ ju awọn akẹgbẹ wọn lagbaaye lọ fun bi ọdun mẹwaa sẹyin bayii.Ronaldo ati Messi jọ dabira ninu idije La Liga nibi ti wọn ti jọ gba ami ẹyẹ loriṣiiriṣii fun ẹgbẹ agbabọọlu wọn, Real Madrid ati Barcelona ki Ronaldo to darapọ ikọ Juventus.",0,yoruba Ìdùnnù ǹlá gba ọkàn - an mi nígbà tí mo gba ìròyìn tẹl mí lọ́wọ́ wípé n ó máa sọ̀rọ̀ àkórí ètò níbi Àpérò CC ọdún - un 2019 ní Lisbon .,0,yoruba dara. Gbogbo àwọn ènìyàn yì í tún ṣe àwọn iṣẹ́ tí ọ̀pọ́lọ̀ àti àlàáfíà.,0,yoruba "Ojo arọrọda Eko ṣe idiwọ fún káràkátà Ọpọlọpọ òpópónà ló kún fún omi, ti awọn awakọ mi i si duro diẹ ki ojo naa wawọ, ki wọn to tẹsiwaju lẹnu irinajo wọn. Àsìkò yi ni ojo máa n pọ ní orílèèdè Naijirià, tí àwọn àjọ tó n mójú tó ojú ọjọ sí ti fi ìkìlọ síta pé, o ṣeéṣe kí ọjọ po lẹnu ọjọ mẹta yí. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: NISE NI OJO TO RO LEKO KUN OJU TITI Gẹgẹ bi akọroyin BBC Yoruba, to tọpinpin ojo arọrọda naa ti wi, ọpọ isẹlẹ sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ lo waye lawọn ọpọ oju popo nilu Eko, ti aimọye osisẹ si pẹ pupọ, ki wọn to de sẹnu isẹ wọn. Koda, ọpọ awọn ọja nla-nla gbogbo lo da paro-paro nitori bawọn ontaja ati onibara ko se ri ọna de awọn inu ọja yii, ti agadagodo si wa lẹnu awọn sọọbu ile itaja gbogbo. Ladugbo Ikoyi nibi ti ofisi Ile isẹ BBC wa, awọn opopona bi Lugard, Alfred Rewane ati Glover kun fọfọ fun omi.",0,yoruba Àwon Ààyè Wúnrẹ̀n_Ìwé-ẹ̀rí,0,yoruba "àìkú. Nitori eyi, ara eni lo ni ẹ̀ká àwẹ eyti o gbe lori àìmọ́ kọ.",0,yoruba Assurance 2020: Davido ní kí àwọn olólùfẹ́ òun fi ojú sọ́nà fún ìgbẹ́yàwó òun pẹ̀lú Chioma,0,yoruba "RT @user: Òjíjí bá jí wọn, ẹnikẹ́ni tí ìrànlọ́wọ́ọ̀ mi bá ń bẹ níkàwọ́ọ rẹ̀. Afà máa fà wọ́n bọ̀ pitipiti. Nítorí ẹṣin ní í pé bo…",0,yoruba RT @user: Asake orun..RT @user: Ọba Àjọkẹ́ ayé,0,yoruba "Ẹgbẹ awọn dokita onimọ iṣegun oyinbo ni Naijiria ti fagile iyanṣẹlodi ti wọn bẹrẹ, nitori bi awọn ọlọpaa ṣe fiyajẹ awọn ọmọ ẹgbẹ wọn kan lasiko isede coronavirus. Lara oun ti awọn dokita naa tọka si nipe ileeṣẹ ọlọpaa n da awọn ọmọ ẹgbẹ wọn duro, eyi ti ko yọ awọn ọkọ to n gbe alaisan silẹ. Ninu atẹjade kan ti ẹgbẹ naa fi sita, wọn ni ki awọn dokita o pada si ẹnu'ṣẹ wọn laago mẹfa irọlẹ oni. Iyanṣẹlodi naa ko pe wakati mejila ti wọn fi kede pe awọn ti fagile. Ọjọru ni wọn bẹrẹ iyanṣẹlodi naa, ti wọn si s pe yoo wa titi di igba ti ijọba yoo fopin si ifiyajẹni ti awọn ọlọpaa n ṣe si awọn ọmọ ẹgbẹ wọn lasiko ofin Konile-o-gbele. Ninu atẹjade ti ẹgbẹ ọhun fi sita ni wọn ti fikun pe awọn ọlọpaa tilẹ n ti wọn mọle ni aini idi. Ṣugbọn ṣa, Ọga Agba Ọlọpaa lorilẹede Naijiria, Muhammed Adamu paapa ti fi aṣẹ tuntun sita nipa ofin konile o-gbele kaakiri orilẹede Naijiria. Ko din ni aadọta awọn dokita , oniroyin atawọn oṣiṣẹ ẹka to ṣe koko miran lasiko ajakalẹ arun coronavirus yii ni awọn ọlọpaa ni ipinlẹ Eko ti fi panpaẹ ofin mu bayii lọjọ Iṣẹgun ni ibamu pẹlu aṣẹ kan ti ọga ọlọpaa lorilẹede Naijiria pa. Ni ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu kẹrin ni aarẹ Muhammadu Buhari paṣẹ konile o gbele eleyii to de igbokegbodo ọkọ laarin agogo mẹjọ alẹ si agogo mẹfa owurọ gẹgẹ bi ara ọna lati dena itankalẹ ajakalẹ orun COVID-19. Amọṣa aarẹ ko ṣai ṣe gafara fun awọn oṣiṣẹ ti iṣẹ wọn jẹ koṣemaani lasiko naa bii awọn oṣiṣẹ eto ilera, akọroyin ati bẹẹbẹl lọ. Ni ọjọ Iṣẹgun ni ọga ọlọpaa lorilẹede Naijiria ṣe ipade ori ayelujara pẹlu awọn lọgalọga lẹnu iṣẹ ọlọpaa lorilẹ€de Naijiria nibi to ti paṣẹ fun wọn lati tubọ rii pe aṣẹ konile o gbele naa fẹsẹmulẹ sii ti wọn si ni o paṣẹ pe ki wọn maa fi panpẹ ofin mu ẹnikẹni ti irinkerindo rẹ ba ti kọja agogo mẹjọ alẹ. Lagbegbe Alausa ni ilu Eko, gbogbo awọn dokita ati akọroyin to n bọ lati ibi iṣẹ ni awsn ọlọpaa ko da satimọle ti wọn si gbẹsẹle ọkọ wọn. Iroyin taa gbọ ni pe awọn ọmọ igbimọ amuṣẹya ti aarẹ gbe kalẹ lori kikoju arun coronavirus, PTF lo wa kan si ọga ọlọpaa lorilẹede Naijiria ki o to paṣẹ ki wọn tu wọn silẹ lẹyin ti wọn ti lo bii wakati meji lagọ ọlọpaa. Ijọba ipinlẹ Eko ti n gbeero lati fi opin si isede coronavirus patapata, ṣugbọn diẹdiẹ ni yoo bẹrẹ. Gomina Babajide Sanwo-Olu lo kede awọn ilana tuntun yii, pẹlu boṣe jẹ pe ipinlẹ Eko ni aarun coronavirus pọ si julọ ni Naijiria. Ọsẹ keji ti ijọba dẹ isede lo n pari lọ bayii, ṣugbọn gomina sọ pe ọsẹ mẹfa ni yoo gba. 1. Register-to-Open - Eyi tumọ si pe ijọba yoo kọkọ ṣe ayẹwo ile ijọsin, ileeṣẹ, tabi ile itaja to ba fẹ ẹ bẹrẹ iṣẹ pada. 2. Lẹyin ayẹwo naa, ileeṣẹ, ile ijọsin, tabi ile itaja bẹ ẹ yoo gba iwe ẹri pe o pa ilana ati ofin ti ijọba gbe kalẹ lati fi opin si Covid-19. 3. Ijọba ko ti i sọ ọjọ ti awọn eeyan wọn yii yoo pada bẹrẹ iṣẹ wọn, lẹyin ayẹwo naa, ṣugbọn o sọ pe ki awọn to ni ileeṣẹ naa mura silẹ lati tẹle ilana tuntun naa, nitori pe coronavirus ti mu ayipada ba ayika wa. 4. Awọn ti ilana tuntun naa kan ni ṣọọṣi, mọṣalaaṣi, gbọngan ayẹyẹ, ile itaja igbalode nla, gbọngan sinima, ati awọn ibi igbafẹ. 5. Awọn nkan ti ijọba yoo yẹwo kii wọn o to o fun wọn ni iwe ẹri ni, ilana ijina sira ẹni ti wọn ti gbe kalẹ, ati fun imọtoto. Awọn nkan wọnyii ni yoo si sọ boya awọn ṣọọṣi ati mọṣalaaṣi naa yoo ṣi pada. 6. Ijọba yoo paṣẹ fun awọn banki, ati ọja lati maa da awọn onibara to jẹ agbalagba lohun laarin aago mẹsan aarọ si mẹwa aabọ, ki wọn o to da awọn ọdọ lohun. 7. Dandan ni wiwọ ibomu-bo ẹnu nipinlẹ naa. Awọn ọlọkọ eero si gbọdọ tẹle ilana ijina sira ẹni. Ṣugbọn ṣa, Gomina Sanwo-Olu sọ pe o ṣeeṣe ki isede miran tun waye, ti awọn araalu ko ba tẹle awọn ilana naa. Yàtọ̀ si aríwo tó ń tàn ká pé gómínà ìpínlẹ̀ Kwara tí paṣẹ pé ki wọ́n fún awakọ̀ tó wà nínú fọ́rán kan to fójú hàn lórí ayélujára níbi ti wọ́n ti n gbé ènìyàn kan sí inú ọkọ pàjáwìrì aláàrùn Covid-19 níwèé ìdádúro, Kọmísọ́nà fún ètò ìlera ní ìpínlẹ̀ Kwara Raji Razaq ni ọ̀rọ̀ kò rí bẹ́ẹ̀ rárá. Raji Razaq ní wọ́n kan yọ awakọ̀ náà kúrò lára àwọn to n mójútó àwọn alárùn coronavirus ni, nítorí pé ó kùna láti pa àwọn ilànà tóyẹ ki o tẹ̀lé mọ́. Ó ní ọkùnrin ti wọ́n lọ gbé òun pẹ̀lú kìí ṣe àláàrùn Coronavirus, ó sì ti wà ní àkàtà ìjọba fún ìtọ́jú báyìí. Kọmísọ́nà ní gbogbo àwọn ọgálọ́gàá ilé iṣẹ́ náà to fi mọ akọwé agba ilé iṣẹ́ iléra to pàṣẹ fun awakọ̀ náà láti lọ gbé ẹni náà ni wọ́n ti gba iwé ìbáwí. Alhaji Razaq ni ìpàpara ni awakọ̀ náà fi bá iṣẹ́ rẹ̀ jẹ́ nítorí pé ó yẹ kí ó dúró de àwọn ti yoo gbé aṣọ ìdáàbò tó yẹ kí o wọ̀ wá, súgbọ́n ko fi àrà balẹ̀ Kíni ìlànà tó tọ́ láti gbé aláàrùn Covid-19 nílé wọn Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, Kọmísọnà ní tí wọ́n ba ti pé ilé iṣẹ́ ètò ilera bẹ́ẹ̀, ọ̀dọ̀ ọ̀gá àgbà ni ìpè náà yóò dé sí ti yóò si pàsẹ fún àwọn to wà ni ìdí, ètò pàjáwìrì láti lọ́ṣe iṣẹ́ wọn. Lórí ìtàkùn ayélujára àjọ to n gbógunti ààrùn Coronavirus ni Naijira NCDC náà, wọ́n sàlàyé àwọn ìlànà ti àwọn elétò ààbò àti ará ilú gbọdọ̀ mọ̀ ti wọ́n bá ri ẹni tó ni ààrùn Coronavirus. * O ṣe pàtàkì láti mọ àwọn ibi ìtọjú to wà ni àyíka ní ìpińlẹ̀ tàbí ni agbègbè wọ́n * Àwọn elétò ìlera ti gbọdọ̀ kọ́kọ́ lọ fún ìdánilẹ́kọ̀ọ́ bi a ṣe n tọ́jú àjàkálẹ̀ ààrùn ti wọ́n pè ni (Infection, Prevention, And Control IPC). * Gbogbo òṣìṣẹ́ tí yóò ba kójú àláàrùn Covid-19 gbọdọ̀ wọ aṣọ ìdáàbò (PPE), ìbòmú, ìbọ̀wọ́, awòojú àti fìlà * Ní kété ti òṣìṣẹ́ ìlera bá ti gbé aláàrùn coronavirus tan, o ṣe pàtàkì láti fi àwọn kẹmika apakòkòrò tọ́jú gbogbo ǹkan ti ẹni náà wọ̀ kí o to kúrò ní ilé ìwòsàn. Sáájú ní àkọ̀wé gómìnà Kwara Rafiu Ajakaye ti fi àtẹjáde kan síta pé gómìnà ìpínlẹ̀ Kwara Abdulrazaq Abdulraman ti pàṣẹ pé kí wọ́n fún àwakọ̀ náà ni iwé ìdádúró. Sùgbọ́n nígbà ti BBC padà pèé ló ní, wọ́n kan yọọ́ kúrò ni ẹ̀ka Covid -19 ní kìíṣe pé wọ́n yọọ́ lẹ́nu iṣẹ́ Atẹ́gùn òjò rán ọ̀pọ̀ lóko àdánù nílùú Ìbàdàn, aráàlú gbarata Ibadan rainstorm: Awọn olugbe ilu Ibadan gbarata lori awọn ile ti atẹgun ojo ṣidanu Awọn olugbe agbegbe Joyce B ni ilu Ibadan ti bẹrẹ sini ke irora lẹyin ti ojo to fi iṣeju marundinlaadọta rọ lopin ọṣẹ ṣe akoba fun awọn ile kan. Ninu itakurọsọ pẹlu ikọ BBC Yoruba, ọkan lara awọn ti o fi ara gba iṣẹlẹ naa, arakunrin Kayọde Popoọla ṣe alaya wi pe iru iṣẹlẹ bẹẹ ko ṣẹlẹ ri lati nnkan bii ogun ọdun sẹyin ti oun ati ayarẹ ti ya ile ti wọn fi da ile ẹkọ silẹ fun awọn akẹkọ to n bẹ ni agbegbe naa. O ni oun n wẹ lọwọ ni nigba ti ipe pajawiri kan wọle wi pe atẹgun ojo ti ṣi paanu ile lọ ti o si rọ lu ile alaja kan to n bẹ ni iwaju ibi ti wọn fi n ṣe ile ẹkọ. O ni, ""Inu ile mi ti mo n gbe ni mo wa, mo n wẹ lọwọ ni gbogbo inu ile bẹrẹ sini mi gbugbugbu. Bi mo ṣe jade nile iwẹ mo rii pe yara mi ti n jo. Yara mi o jo ri, yara awọn ọmọ mi naa bakan naa. Iyẹn ni a n mojuto lọwọ mo n pe Ọlọrun pe aanu, aanu o. Lojiji ni ẹrọ ibanisọrọ mi dun, ọkan ni ninu awọn olukọ wa lo pe mo ba gbe ipe rẹ. Jọkẹ ki lo ṣe ẹ? Daddy atẹgun ti gbe gbogbo paanu o..."" Popoọla ni iye owo ti yoo ṣe atunṣe ile ẹkọ naa ko di ni milliọnu meji naira, bẹẹ sini awọn to ya ile igbe lo jẹ gbese nitori baba to ni ile ti darugbo. O ra ọwọ ẹbẹ si ijọba ati awọn ẹlẹyin ju aanu lati ṣe iranlọwọ fun wọn lasiko yii. Gbogbo paanu ti atẹgun ojo ṣi danu ni awọn to n gbe awọn ile naa ti n gbiyanju lati kojọpọ si ẹgbẹ kan lasiko ti ikọ iroyin BBC Yoruba ṣe abẹwo si agbegbe kan.Lọkọọkan-ejeeji sini wọn duro gẹgẹ bi wọn ṣe n wo awọn ile naa pẹlu iyalẹnu. Eeyan ẹrin ọtọọtọ lo padanu ẹmi wọn ti ọgọrọ awọn eeyan mii si fi ara pa ninu ijamba ọkọ to waye nilu Ogbomoṣọ lọsan ọjọ ẹti.Ni agbegbe Apake lopopona marosẹ Ogbomọṣọ si Ilọrin atijọ ni ọkọ akẹru kan ti sa wọ ibi ti awọn ero ọkọ ati ọlọkada korajọpọ si. O ṣoju mi koro ṣe alaye fun awọn oniroyin pe eeyan mẹrin lo ku loju ẹsẹ gẹgẹ bi wọn ṣe ko awọn ti o fi ara pa lọ si ile iwosan ẹkọṣẹ iṣegun Oyinbo, LAUTECHTH to n bẹ niluu Ogbomọṣọ.Iroyin sọ wi pe ẹkun ariwa ni ọkọ naa n ri irinajo lọ ki o to di wi pe o padanu ijanu ọkọ lasiko to n sa fun awọn ẹṣọ aabo oju popo niluu Ogbọmọṣọ, ṣugbọn adari ẹṣọ aabo oju popo to n bẹ ni agbegbe naa, Bọlade Olugbẹsan sọ wi pe irọ to jina si ọọtọ ni ẹsun naa. O ni ko si oṣiṣẹ ẹṣọ aabo pupo ni ibi ti ijamba naa ti ṣẹlẹ.O ṣoju mi koro mii ti o ba awọn oniroyin sọrọ ṣe alaye wi pe ọlọkada ni awọn eeyan mẹrẹẹrin to padanu ẹmi wọn sinu ijamba naa.Lasiko ti a ṣe akojọpọ iroyin yii, awọn osiṣẹ aabo duro wamuwamu si ofisi ẹṣọ aabo oju to n bẹ ni agbegbe 'High School' niluu Ogbomọṣọ lati dena akolu awọn ara ilu to n fapajanu nitori ijamba naa. Mẹrin ninu awọn eeyan mọkanla to n ti ipinlẹ Sokoto bọ ṣugbọn ti awọn agbofinro mu lẹnu ibode ipinlẹ Oyo si Osun lo ni arun Coronavirus. Ẹni to n risi iṣẹlẹ naa, Taiwo Ladipo lo fi ọrọ ọhun lede fun awọn oniroyin lọjọ Iṣẹgun. O ni awọn mẹrin naa ti wa ni ile iwosan ti wọn ya sọtọ fun awọn to ni arun Covid-19, eyi to wa ni Olodo. Lẹyin itakurọsọ pẹlu awọn arinrin ajo naa, Gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde sọ pe oun ko ni yọnda wọn fun ijọba ipinlẹ Sokoto, ayafi ti wọn ba kọkọ ṣayẹwo arun Coronavirus fun wọn. Iye awọn to ti lugbadi arun naa nipinlẹ Oyo lọwọ yii jẹ mọkandinlogoji, ti mejidinlọgbọn ninu wọn si n gba itọju lọwọ. Bo tilẹ jẹ pe awọn mẹsan an ti ri iwosan, awọn kan ti jẹ Ọlọrun nipe nipe nitori arun naa. Ijọba ipinlẹ Oyo ti sọ pe ko si ẹni kankan to tii ni arun Coronavirus nipinlẹ naa, ati pe oun ti bẹrẹ igbesẹ lati ṣawari awọn eeyan to ṣalabapade ẹni ti wọn fura si pe o ṣeṣe ko ti ko arun naa wọ ipinlẹ ọhun. Kọmiṣọna eto ilera, Bashir Bello ni ijọbaa ti ṣayẹwo ẹni kan to ṣẹṣẹ de lati ilẹ Gẹẹsi, ti wọn si ti fi ayẹwo naa ranṣẹ si yara ayẹwọ to wa ni fasiti ẹkọṣẹ iṣegun to wa ni ilu Eko, LUTH. O ni lọwọ yii, oun ko tii le fidi rẹ mulẹ pe ẹnikẹni ti lugbadi arun naa nipinlẹ Oyo titi di igba ti esi ayẹwo naa yoo jade. Bello sọ pe ijọba ipinlẹ naa mọ pe ẹni to ko arun Coronavirus wọ ipinlẹ Ekiti lo akoko diẹ nilu Ibadan. O ni ileeṣẹ eto ilera ipinlẹ Oyo ti n gbaradi lati koju arun ọhun lati igba to ti ṣẹyọ lorilẹ-ede Naijiria. Bello tẹsiwaju pe ""Bo tilẹ jẹ pe arun yii ti n peleke si ni Naijiria, ileeṣẹ eto ilera ipinlẹ wa n ṣiṣẹ takuntakun lati ri pe arun naa ko si ni ipinlẹ Oyo."" Bello wa rọ awọn eeyan ipinlẹ Oyo lati ma foya nitori arun naa, ṣugbọn ki wọn ma ṣe awọn ohun to le mu arun jina si ayika wọn, bii wiwa ni nkan bii iwọn ẹsẹ bata mẹfa si awọn elomiran ati ṣisṣọra fun ibi ti ọpọ eeyan ba korajọpọ si. Àwọn ọmọ Nàìjíríà ń kán Seyi Makinde níkòó fún ìgbàlejò ìpàdé ìtagbangba PDP níbàdàn lásìkò àjàkálẹ̀ àrùn coronavirus Ọpọ lo ti n bu ẹnu atẹ lu bi Gomina Seyi Makinde ipinlẹ Oyo ti ṣe ipade itagbangbe oṣelu ẹgbẹ oṣelu PDP niluu Ibadan l'Ọjọru, bo tilẹ jẹ wi pe ibẹrubojo awọn arun coronavirus wa nita. Nigba to n sọrọ nibi ipade ọhun to waye ni gbọngan Mapo, Makinde ni apẹrẹ wi pe ẹgbẹ oṣelu PDP ti bẹrẹ si ni gbori soke ni bi Gomina ipinlẹ Osun tẹlẹ, Olagunsoye Oyinlola ati awọn alatilẹyin rẹ ṣe pada sinu ẹgbẹ naa. Igbakeji gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ, Taofeek Arapaja, sẹnẹtọ to n ṣoju ẹkun ariwa Oyo tẹlẹ, Dokita Gbenga Babalola atawọn eekan inu ẹgbẹ oṣelu ADC to fi mọ oludije fun ipo gomina nipinlẹ Osun, Alhaji Fatai Akinbade lo darapọ mọ PDP nibi ipade ọhun. Bakan naa lawọn eekan inu ẹgbẹ oṣelu ADP ati ZLP darapọ mọ PDP nibi ipadae itagbangba naa ti wọn pe ni ipade iṣọkan ni Ibadan. ''Ipade yii jẹ ibẹrẹ iṣọkan apa iwọ oorun gusu orilẹede Naijiria, ti a ba si ti wa ni iṣọkan lapa iwọ oorun gusu, Naijiria naa ti wa ni iṣọkan niyẹn,'' Gomina Makinde lo sọ bẹẹ. Makinde ni ''awọn eeyan kan ni ko yẹ ki PDP ṣe iru ipade itagbangba bayii lasiko ti coronavirus n tankalẹ yii, ṣugbọn ọkan lara awọn olori wọn lo sọ pe arun coronavirus ti wọ inu ẹgbẹ wọn, amọ awa mọ pe ko si ninu ẹgbẹ ti wa.'' Ninu ọrọ tiẹ nibi ipade naa, Oyinlola sọ pe asiko ti to lati ṣe atunto orilẹede Naijiria, o ni itanjẹ ẹgbẹ APC ti to gẹẹ. O rọ awọn ọmọ ẹgbẹ PDP lati fi ọgbọn yanju ọrọ to ba wa laarin wọn ki iṣokan le wa ninu ẹgbẹ. ''Gbogbo ẹ̀yin tí ẹ lọ sí ibi ìpàdé PDP ní Ibadan, ẹ lọ yara yín sọ́tọ̀ fún àyẹ̀wò coronavirus'' Ọgọrọ eeyan lo dẹnu bo Gomina Seyi Makinde lori ayelujara lẹyin to ṣagbatẹru ipade itagbangba ẹgbẹ oṣelu PDP niluu Ibadan l'Ọjọru. Ohun ti ọpọ n sọ nipe kii ṣe akoko yii ti ibẹru-bojo ajankalẹ arun coronavirus wa nita lo yẹ ki Makinde ṣe iru ipade bẹẹ. Ibrahim Lawal Esq ṣapejuwe ipade itagbangba PDP bi igbesẹ omugọ ti ko mu ọgbọn wa rara. Ibeere ni @AbdulMahmud01 n beere ni tirẹ, o ni ''kinni o n ṣe wa gan an? O sọ pe o ṣeni laanu pe ko si ẹnikan to ronu pe iru ipade itagbangba yii le ṣakoba fun eto ilera araalu pẹlu bi arun covid-19 sẹ wa nita bayii. @Lucasscot_101 ṣalaye ni tiẹ wi pe ẹgbẹ oṣelu APC lo kọkọ bẹrẹ iwa aṣiwere tawọn eeyan si ro pe ko si were to le ju iyẹn lọ. Amọ o ni o ṣeni laanu pe iwa aṣiwere ti ẹgbẹ oṣelu PDP gan wa ju ti APC lọ. O pari rẹ bayii pe ko si ẹni ti ori rẹ pe ninu awọn ẹgbẹ mejeeji. Adeola @Harrdehy fi igbe bọnu ni tiẹ, o ni ẹnikẹni to ba kopa ninu ipade itagangba ẹgbẹ osẹlu PDP gbọdọ ya ara rẹ sọtọ fun ayẹwo arun coronavirus. Ọgọrọ eeyan lo fẹnu ko pe igbesẹ ẹgbẹ osẹlu PDP lati ṣe ipade naa kudiẹ kaato. Amọ ninu gbogbo eyi, ero Olamide Abimbola yatọ ni tiẹ. O ni aṣiwere ni gbogbo awọn to n ṣatilẹyin fun ẹgbẹ APC ti wọn n sọ oko ọrọ si PDP nitori ipade itagbangba ti wọn ṣe ni Ibadan. Abimbola ni ẹgbẹ oṣelu PDP ṣe iru ipade itagbangba ti ko waye ri ninu iwe itan. O rọ awọn to n bu ẹgbẹ naa loju opo Twitter pe ki wọn ronu si ọrọ naa daadaa ki wọn to maa sọrọ loju opo Twitter.",0,yoruba RT @user: ÌṢỌDẸ ÀTI ÀYÍPADÀ OJÚ ỌJỌ́ #Yoruba #EranIgbe #AyipadaOjuOjo,0,yoruba ọlọ́run ṣe àmọ̀nà wa lọ́jọ́ òní fúnwa ní oreọ̀fẹ́ àti dáríjin àwọn tó ṣẹ̀wá kí àwa fi lè rí ìdáríjìn lọ́dọ̀ rẹ,0,yoruba "RT @user: Ìyànjú l'àgbẹ̀ ńgbìn, elédùà nìkan ló mọ b'íṣu ṣe ńta /Farmers merely sow efforts; God alone knows how the yams get fo…",0,yoruba "Awọn olugbe naa ni awọn ole ma n ba mọto awọn jẹ, ti wọn a si tu ẹya ara rẹ lọ. Lara awọn to faragba ninu iṣẹlẹ naa sọ fun awọn oniroyin pe, awọn adigunjale naa ma n wọ asọ bi awọn ẹsọ alaabo to n kaakiri ni agbeegbe naa, ti wọn yoo fi raye wọle si agbeegbe yii lati ṣọṣẹ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Lara awọn agbeegbe ti ọrọ naa kan ni Agbeegbe Iyanse, Onagoruwa, Kosofe ati Iyana School bus stop, tawọ̀n eeyan agbegbe naa si ni wọn maa n gba ohun ini awọn. Wọn tiẹ fikun wi pe, awọn aidgunjale yii ti ji ẹya ara ọkọ to le ni mẹtala ni agbeegbe naa. Àwọn olúgbẹ́ agbégbé Kosofe ní ìjọba ìbílẹ̀ Agboyi-Ketu ti ké gbàjarè síta lórí àwọ̀n adigunjálè tó ń ṣọṣẹ́. Bẹẹ ni wọn kesi ijọba lati bojuto awọn eto aabo to dẹnukọlẹ ni awọn agbeegbe ti awọn adigunjale yii ti n ja ran-in. Arakunrin Tony, to ni wọn ba ọkọ SUV oun jẹ ni aago meji oru, ti wọn si ṣi bonnet ọkọ, ki wọn to fi ipa ṣi ferese ọkọ, ti wọn si raye wọle. Lẹyin eyi lo ni wọn yọ engine ọkọ, ina ọkọ, batiri ọkọ, jigi ẹgbẹ ọkọ ko to di wi pe wọn wa ọkọ ti wọn jade, lẹyin ti wọn ti yọ gbogbo ohun ti wọn fẹ́ yọ tan. Tony ni o le ni ọgbọn iṣẹju ti awọn onisẹ laabi naa fi sọṣẹ ni agbeegbe awọn, ti ko si si oluranlọwọ kankan fun awọn. Nigba ti ileeṣẹ ọlọpaa fesi, wọn ni lootọ ni iṣẹlẹ naa waye ti awọn si ti bẹrẹ̀ iwadii ni pẹrẹwu lati mu awọn adigunjale naa.",0,yoruba "fẹ. Nitori eyi, ara eni lo ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..",0,yoruba "RT @user: Ododo oro """"""""""""""""@user: @user àbí báwo?""""""""""""""""",0,yoruba a fọ aṣọ tán nínú eji eji kò dá a kò rí oòrùn sá a,0,yoruba "Iru ọdun to yọ awọn obinrin silẹ yii ni ọdun oro jẹ ọkan ninu wọn nitori igbagbọ Yoruba ni pe obinrin kii fi oju kan oro, bibẹẹkọ, oro yoo gbe. Lasiko ọdun oro ni ilu Ikorodu ti BBC Yoruba peju si, Oloye Kazeem Adeniyi Roga salaye pe, igi ìto ni yoo sọ fun awọn pe akoko ọdun oro, ti wọn n pe ni Màgbó ti to, ti igi naa yoo si wọwe. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Oloye Roga ni ti awọn oloro ba ti se etutu wọn tan, ni igi yii yoo tun ruwe pada, ti ohun gbogbo yoo si tuba tusẹ. O ni ọdun Magbo maa n ko ibi kuro ni ilu ni, ti yoo si ko ire wọle, bẹẹ ni ilu yoo tuba, tuṣẹ laisi ewu. Amọ awọn obinrin to ba wa sọrọ lori ọdun oro naa lo faraya pe, ọdun naa n tẹ ẹtọ awọn mọlẹ lasiko ti wọn ba n se e, to si maa n sọ awọn si igbekun ati ẹwọn. Wọn ni kii jẹ ki awọn raye lọ sẹnu isẹ oojọ awọn, koda awọn ko ni lee lọ se idanwo tabi se ohunkohun. Awọn obinrin naa wa gba awọn oloro yii niyanju lati maa se oro wọn lọganjọ oru dipo ọsan gangan, eyi ti ko ni di awọn lọwọ lati lọ sẹnu isẹ abi okoowo awọn.",0,yoruba RT @user: @user Olodumare iba re oooooo,0,yoruba RT @user: A dupe fun alaafia ara ati ilera to peye. @user @user: E de ku amojuba Gomina Chime ti ipinle Enugu.Eku afarad ...,0,yoruba @user Ìròhìn ò tó àmójúbà. ṣé ẹ ti báwọn fo irú ìfò yí rí? Èmi ò lè dán-an wò láíláí :),0,yoruba lo joko. Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.,0,yoruba RT @user: njẹ èdè Yorùbá ni ipa lati ko ninu ọ̀rọ̀ òsèlú ilẹ wa bi? @user @user @user @user ...,0,yoruba "Òwe Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n ló bẹ̀rẹ̀ lọ́dọ̀ obìnrin kan tó ń ta ẹ̀wà ní ìlú Abẹokuta. Wọn maa n fi eyi parọwa fun wa, kọ wa lọgbọn, fun wa loye, to si tun maa n tọ wa sọna ninu igbe aye wa lojoojumọ. Ọkan lara awọn owe to n parọwa fun wa ni ""Ṣebotimọ Ẹlẹwa Sapọn"", awọn ohun to si yẹ ka mọ nipa owe naa ree: Itan nipa owe ‘Sebótimọ Ẹlẹwa Ṣàpọ́n Obinrin kan wa nilu Abẹokuta to n ta ẹwa sise ni adugbo Sàpọ́n nilu Abẹokuta, tii se olu ilu nipinlẹ Ogun bayii. Obinrin ẹlẹwa yii mọ ounjẹ naa se debi pe awọn eeyan maa n pe biba sọdọ rẹ lati du ẹwa rẹ ra ni. Kí ló máa ń wú ìyá Nike Davies lori láti wé gèlè ràbàtá? Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Tọkọ-taya Aràrá: Àwọn èèyàn máa ń wò wá, ta bá fa ọwọ́ ara wa ní títì Agbada ikoko nla kan lo maa fi n se ẹwa fun tita, to si n jẹ ere rẹpẹtẹ nibẹ lojoojumọ. Koda, nibi ti ẹwa rẹ dun, to si tun jẹ itẹwọgba de, awọn onibara rẹ maa n ra ounjẹ naa ni awin, lai sanwo ti owo ba sa fẹrẹ lapo wọn. Nigba to ya, oju aanu n pa obinrin ẹlẹwa yii ku lọ, tori ọpọ gbese tawọn eeyan jẹ ẹ, ko jẹ ko ri owo ta ọja mọ, ti odiwọn ikoko ẹwa to n se si n din ku lojoojumọ. Niwọn igba to si jẹ pe alatise ni yoo mọ atise ara rẹ, eyi lo mu ki ẹlẹwa Ṣapọn da ọgbọn ti awọn onibara rẹ ko fi ni gba igba lori rẹ, nipa rira ọja rẹ lawin. Ti onibara kan ba si tọ obinrin naa wa pe oun fẹ ra ẹwa sise rẹ ni awin, iya ẹlẹwa yii yoo sọ fun pe ko ma ra ẹwa lawin, se ni ko ra iye ẹwa ti owo rẹ ka lai jẹ gbese. Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú Agbada ikoko nla kan lo maa fi n se ẹwa fun tita, to si n jẹ ere rẹpẹtẹ nibẹ lojoojumọ. Esi to si saaba maa n fọ jade fun wọn, lati rọ wọn ki mase ra ẹwa lawin ni pe ""Ṣe bo ti mọ"", eyi to tumọ si pe mase ra kọja iye owo too ni lapo bayii. Bi ọjọ se n gori ọjọ, ti oṣu si n gori oṣu, lawọn eeyan ba sọ di owe ati aṣa obinrin ẹlẹwa naa. Ki wọn si to beere ọja awin lọwọ rẹ, ni wọn ti mọ esi ti yoo fi da wọn lohun. Ọrọ yii si ni wọn fi maa n sa obinrin naa pe ""Ṣe bo ti mọ, Ẹlẹwa Ṣapọn"". Diẹ-diẹ si ni owe naa gbilẹ, to si di itẹwọgba titi di oni. Itumọ owe yii lo si n parọwa si ẹni kọọkan wa pe ka ma se kọja agbara wa, ka maa se ohun gbogbo ni iwọntun wọnsi, iwọn eku ni iwọn itẹ, ka maa baa maa jẹ gbese kiri, eyi to lee mu itiju ati ipaya de ba ni. Ta ni Ẹlẹwa Ṣapọn?",0,yoruba "a ní nípa ire àti ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì lẹ̀.",0,yoruba Gomina naa sọ pe awọn agbebọn ti wọn doju ija kọ awọn ẹsọ rẹ wọ aṣọ dudu ti wọn si to mẹẹdogun O ni awọn agbebọn yi fẹ ran oun lọ si ọrun aremabọ ni nitori o to kilomita meji ti awọn fi sa fun wọn Lasiko to n ba awọn akọroyin sọrọ ni Ortom tu kẹkẹ ọrọ silẹ ṣapejuwe awọn agbebọn yi gẹgẹ bi darandaran to si ni bi awọn mẹẹdogun wọn ni wọn tọ ipasẹ oun de eti odo toun ti n fẹsẹ rin. Gomina Ortom jẹ eeyan kan to n bẹnu atẹ lu ihuwasi awọn darandaran to jẹ ipenija aabo ni Naijiria lẹnu ọjọ mẹta yii. Ṣaaju lo ti sọ fun BBC ninu ifọrọwerọ kan laipẹ yi pe awọn ẹgbẹ darandaran yi tako ofin ti oun ko si faramọ iṣesi wọn. Bakan naa lo kesi ijọba lati fi iru ọwọ to fi mu awọn ẹgbẹ mii bi ti IPOB ati ESN ti ijọba ni awọn wọgile mu ẹgbẹ Miyetti Allah awọn darandaran. Taooma: Ìbáṣepọ̀ mi pẹ̀lú àwọn òbí mi yàtọ̀ sí bí mó ṣé n polongo nínú fídíò mi,0,yoruba "Ìlú Ọ̀yọ́ jẹ́ ilẹ̀ agbègbè tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Nitori eyi, ara eni lo ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.",0,yoruba Unai Emery gba ife ẹ̀yẹ mẹ́ta ní sáà méjì tó fi ṣiṣẹ́ pẹ̀lú ikò agbábọ́ọọ̀lù Paris St-Germain Mikel Arteta to jẹ igbakeji akọnimọọgba ni ikọ Manchester City lo da bi pe o ma rọpo Wenger tẹlẹ. Ṣugbọn Emery lo fakọyọ julọ ninu ifọrọwanilẹnuwo ti wọn ṣe fun awọn to kowe fun ipo akọnimọọgba ikọ Arsenal. Emery to jẹ ọmọbibi orilẹede Spain fi ẹgbẹ agbabọọlu Paris St-Germain to n dari silẹ l'opin saa yii. Unai Emery ti ṣiṣẹ́ ní Sevilla àti PSG tẹ́lẹ̀ rí Akọnimọọgba Emery to jẹ ọmọ ọdun mẹrindinlaadọta gba ifẹ ẹyẹ mẹta pẹlu ikọ PSG nigba to wa pẹlu wọn. Emery ti figba ri jẹ akọnimọgba Sevilla ni orilẹede Spain nibi ti o ti gba ife ẹyẹ Europa lẹmẹta lera wọn laarin ọdun 2014 si ọdun 2016.,0,yoruba Àwọn ènìyàn ti gba lo wey o lẹ.,0,yoruba "Jude Chukwuka, tii se ọmọ Igbo, amọ to gbọ ede Yoruba tun ti gbe tuntun de. Lọtẹ yii, Oríkì Ooni, Alaafin, Eko àti Ọlọ́fàmọjọ̀ ni Chukwuka fi n panu, eyi to yọ lẹnu rẹ ju tawọn ọmọ onilu lọ. Chukwuka ninu fidio yii ki ilu Ile Ife, Oyo, Eko ati ọba wọn, bakan naa lo ki awọn ọmọ Ọlọfamọjọ titi, ti ori eeyan fi wu. Iyalẹnu si ni yoo jẹ fun ojulowo ọmọ Yoruba ti ko mọ oriki ilu tabi ọba alade kankan, pe ọmọ ẹya Igbo tun mọ awọn oriki Yoruba ju ọmọ Kaarọ Oojire lọ. Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:",0,yoruba @user Kí Ọlọ́run dẹlẹ̀ fún ẹni ire. Mo ní ànfàní àti wòran wọn nígbà aye wọn.,0,yoruba àsà tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa àwọn ènìyàn: ti o nuni ti o wulo.,0,yoruba "Arabinrin Felicia to jẹ oniṣowo Garri ni agbègbè ilu Akure ṣalaye ilana ti wọn maa n tẹle lati yan ounjẹ ilẹ Naijiria yii, Garri. ""Owó tà ń ná láti ṣe Garri tà kìí ṣe kékeré"". Felicia jẹ ko di mimọ wi pe ki wọn to lọ wu ẹgẹ ni oko, ki wọn to bẹẹ, ṣiṣan, lilọ, kiko, titẹ ri ati bẹẹ bẹẹ lọ plu imọtoto, kii ṣe ere ọmọde rara. Bakan naa iye ọjọ ti wọn fi n ṣe Garri ko kere ṣugbọn ko le din ni ọjọ mẹfa rara. Iṣẹ Garri yiyan nilo agbara ati ọpọlọpọ iṣẹ gẹgẹ bi Felicia ati awọn akẹgbẹ rẹ to ku ṣe n ṣe e ni ibudo yii. Sibẹ pẹlu gbogbo eleyii, awọn obinrin to n yan Garri ta yii ni owo ti wọn n na lati ṣe e gan pọ ṣugbọn ere to wa lori ni wọn fi n gbe ọpọlọpọ nkan ṣe ninu ile.",0,yoruba "Oṣere tiata kan ni ẹkun ariwa, lagbo Kannywood, Safiya Yusuf, ti awọn eeyan ariwa Naijiria mọ sì 'Safara'u,' ti sọrọ lori riri rẹ lẹyin ti aworan ihoho rẹ bọ sì orí ayelujara. Safiya ni odidi oṣu mẹta ni oun lo ninu ile lẹyin ti foran naa  bọsi ori ayelujara. Safiya lo di ilumọọka lẹyin to kopa ninu ere sinima Kwana Casa 'in'. Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC News, Safiya salaye pe oun ti gba ìsinmi lẹnu isẹ tiata, lati ni asiko fun isẹ orin tí oun yan layo. O tẹsiwaju pe lẹyin iṣẹlẹ naa ni ọpọlọpọ eeyan bẹrẹ si bu oun, ti wọn ba ti pade oun níbi kibi. ""Igba ti fọnran ihoho mi bọ sorí ayelujara jẹ igba manigbagbe ninu igbesi aye mi nítorí mo lo oṣu mẹta ninu ile lai fi oju gaani ilẹkun abawọle wa. Mo kan wa ninu ile."" ""Nigba ti mo wa ṣe ọkan akin lati bọ sita, ọpọlọpọ eeyan lo bẹrẹ si n ma bu mi, koda mo ranti ẹni kan to lẹ mi ni oko. ""Safiya tẹ siwaju pe ti ko ba ṣe ọpẹlopẹ awọn mọlẹbi oun ti wọn duro ti oun, omi o ba pọju ọka lọ. ""Mo dupẹ gan-an lọwọ awọn mọlẹbi mi nítorí pe awọn ni wọn ran mi lọwọ nigba isoro lati bọ ninu rogbodiyan naa. Awọn ẹgbọn mi, awọn obi mi ati gbogbo mọlẹbi pata ni wọn duro timi.” Safiya ni ko si nkan ti o jọ mọ pe wọn le oun kuro lawujọ awọn oṣere tiata, ó ni fura oun ni oun gba ìsinmi fun igba diẹ. Safiya sọrọ imura pe lọpọ igba, ko wu oun lati ma wọ asọ ibile nítorí pe wọn ko fi kọ oun lati kekere. O ni imura asa oyinbo lo mọ oun lara julọ. Safiya tun salaye idi to fi jẹ pe awọn ọkunrin nìkan ni oun ba kọrin papọ. O ni kii ṣe wipe oun ko fẹ ba obinrin kọrin sugbọn oun ko ti rí obìnrin ti yoo ba oun kọrin papọ bayii. ""Emi ko ti rí obìnrin tí ma ba kọrin, nítorí rẹ ni lo fi jẹ pe ọkùnrin nikan ni mo n ba kọrin. ""Alaye miran ni wipe pupọ lara awọn tí a jọ dagba lo jẹ ọkùnrin, emi nkan ni obìnrin. Nítorí rẹ ni ko fi jẹ ohun iyalenu fun mi.""",0,yoruba "Ọjọ ayajọ ọdun ominira Naijiria ni ọjọ akọkọ ninu oṣu kẹwaa gbogbo ọdun jẹ nitori ayajọ naa ni ọdun 1960 ni orilẹede Naijiria gba ominira rẹ kuro lọwọ ijọba amunisin ilẹ Gẹẹsi. Ni ayajọ ọdun yii, oniruuru ara ni awọn ọmọ orilẹede Naijiria da lori ọkan o jọkan oju opo ayelujara. Bakan naa lawọn kan naa tun n lo oniruuru ọrọ idakọro ori ayelujara iyẹn hashtag # bii #NigeriaAt59#IndependenceDay, #October1st,#naijaat59, #GodBlessNigeria, #ProudlyNigerian lati fi ero ọkan wọn han nipa ajọdun naa.",0,yoruba "Bi a ba ni ka fi ti awọn iroyin to mi igboro lọsẹ kini Oṣu kini ọdun 2020 yi wo o, nkan yoo ṣẹnu 're lagbami iroyin lọdun ti a ṣẹṣẹ mu yii. O dabi ana ti a dagbere fun ọdun 2019 ti pupọ wa si n ki ara wa pe a ku ipalẹmọ 2020. 2020 ti de ti o si ti n so eso iroyin lorisirisi. Ẹ jẹ ki a fi diẹ to ara wa leti ninu wọn ki ọrọ naa ma baa di ariyanjiyan. 2020: Ọdun 2020 yii ko nìí nira fún àwọn tó bá bẹ̀rù Olorun Abuja Bank Robbery: Ọwọ́ sìkún ọlọ́pàá tẹ Ernest tí wọ́n ń wá. Ojoro la fẹ fi bẹrẹ tori ẹ le fẹ sọ pe ha ha, ọsẹ to kọja ni ọ̀rọ̀ yii bẹrẹ, ṣugbọn ẹyin yoo ri pe ko baa le daa la fi ṣe bẹ tori o ṣi wa lori igba iroyin titi di ọsẹ yii. Iroyin awọn adigunjale to lọ fọ banki nilu Abuja tọwọ ọlọpaa tẹ wọn la kọkọ fẹ mu. Lootọ ni pe lọjọ Kejidinlọgbọn oṣu to pari 2019 ni ọwọ tẹ wọn ṣugbọn ẹni tawọn ọlọpaa sọ pe o jẹ ogunagbongbo iṣẹlẹ naa, laarin ọsẹ kini 2020 ni ọwọ palaba rẹ segi. Abuja Bank Robbery: Ọwọ́ sìkún ọlọ́pàá tẹ Ernest tí wọ́n ń wá wa lara awọn iroyin tawọn eeyan n ka iroyin rẹ nipa iṣẹlẹ yii. Ni bayi ti ọwọ ọlọpaa ti tẹ Earnest, iye awọn tọwọ tẹ lori iṣẹlẹ naa ti di marun un. Ayodele Fayose: Ẹ̀yin ọ̀tá mi, ẹ lọ dì mọ́ òpò ina lọ́dún 2020 Ẹ̀yin ọ̀tá mi, ẹ lọ dì mọ́ òpò ina lọ́dún 2020- Ayodele Fayose Nise ti ọdun tuntun bẹrẹ, Gomina ipinlẹ Ekiti tẹlẹ ri, Ayodele Fayose fi eebu ọrọ ransẹ si awọn to n pẹgan rẹ. Ọrọ ko ṣẹyin bi awọn kan ṣe bu ẹnu atẹ lu u lẹyin ti fidio jade nibi ti o ti n jo pẹlu oyinbo lode kan ni ilẹ okeere. Wọn ni ṣebi itọju lo loun fẹ lọ gba nilu okeere to fi gba beeli rẹ lọdọ adajọ. Fayose da wọn lohun pe ayẹwọ ara ni oun lo se, oun ko dubulẹ aisan, nitori naa oun laṣẹ lati jo ati yọ ninu ọdun tuntun. Ẹkunrẹrẹ iroyin yi wa loju opo wa nibi yii Ẹ̀yin ọ̀tá mi, ẹ lọ dì mọ́ òpò ina lọ́dún 2020- Ayodele Fayose ìjọba ìpínlẹ̀ Kwara wó ìlè arúgbó ní ìdàjí Bi ere bi ere ni ọrọ naa bẹrẹ a mọ ki a to diju ka to la, a ijọba ipinlẹ Kwara ti wo ile Arugbo eleyi to jẹ ti Dokita Olusola Saraki, baba adari ile aṣofin agba Naijiria tẹlẹ ri. Eemọ kileyi lawọn alatilẹyin Saraki n ke ti awọn iya arugbo naa ṣi n ṣemo pe Gomina Abdulrahaman ti gba ijẹ lẹnu awọn. Ninu fọnran fidio to wa nisalẹ yii, wọn ti ṣaaju ke gbajare si ki o ma wo ile naa ṣugbọn pabo ni igbiyanju wọn ja si. Àwọn arúgbó ní kí ìjọba máà ṣe wó ilé arúgbó m'áwọn lórí Nigba ti osẹ yoo fi wa si opin, Bukola Saraki to jẹ ọmọ Dokita Olusola Saraki ati Gbemisola Saraki naa ti tutọ soke foju gba a lori igbesẹ ijọba yii. Iroyin yi ko ti jọ bi ẹni loju tu,ẹ tubọ maa tẹle wa fun atupalẹ bi ọrọ naa ba ti ṣe n lọ si. Ṣaaju igba naa, ẹ ka sii nipa rẹ loju awọn opo wọnyii: World War III: Donald Trump pàṣẹ kí wọ́n pa olórí ikọ̀ ajìjàgbara orílẹ̀èdè Iran Jẹjẹ lo jọ bi pe ọṣẹ akọkọ 2020 n palẹmọ lati pari ki iroyin bi ilẹ Amerika ti ṣe ṣekupa ọgagun ọmọ orileede Iran kan ni Iraq. Kete ti iroyin yii lu sita ni gbogbo oju opo iroyin lagbaye gbanajẹ ti awọn eeyan si n pariwo WWIII loju opo Twitter. Ẹkunrẹrẹ iroyin nipa iṣẹlẹ yii ree to ba jẹ pe ẹ ko tii maa fọkan ba a bọ tẹlẹ:",0,yoruba "A gbo̟dò̟ pèsè è̟kó̟ is̟é̟-o̟wó̟, àti ti ìmò̟-è̟ro̟ fún àwo̟n ènìyàn lápapò̟. Àǹfààní tó dó̟gba ní ilé-è̟kó̟ gíga gbo̟dò̟ wà ní àró̟wó̟tó gbogbo e̟ni tó bá tó̟ sí. 2/4",0,yoruba RT @user: @user ni otito ni oooooo awon onijibiti lo poju to nlo gtb nitori banki yen nbo asiri won,0,yoruba "Agba oye Wasiu Ayinde Ọmọgbọlahan ti ọpọlọpọ eeyan mọ si K1 ti ke sawọn ọmọ orilẹede Naijiria pe pẹlu bi nnkan ṣe n lọ yii lori arun coronavirus, gbogbo ẹni ti ko ba ni nnkan to nṣe ki wọn gbe ile wọn ni. Ninu orin rẹ kan to n kaakiri lori ayelujara bayii, K1 ṣalaye pe ọrọ coronavirus yii ki ṣe ṣereṣere rara, gbogbo ọmọ Naijiria lo si gbọdọ gbaruku ti awọn alaṣẹ lati gbe awọn igbesẹ gbogbo to yẹ ni didẹkun arun naa. Ẹwẹ, Gbajugbaja Oṣere Tiata, Toyin Abraham naa ti da si ọrọ arun coronavirus to gbode kan bayii. Toyin jẹ ọkan lara awọn wọ kilu o mọ akọkọ ti yo mẹnu le ọrọ lori arun yii. Ninu ọrọ kan to fi sori oju opo twitter rẹ, Toyin Abraham rọ awọn ololufẹ rẹ lati mojuto ilera wọn fun oun nitori oun nifẹ wọn gidigidi. Toyin Abrahams to gba ami ẹyẹ oṣere to gbamuṣe julọ lobinrin lagbo ere tiata nibi ami ẹyẹ AMVCA laipẹ yii tun fi fidio ilanilọyẹ kan lori bi a ṣe lee tọju imọtoto ara ẹni lasiko yii. Toyin Abraham kọ ni gbajugbaja oṣere akọkọ ti yoo ke sawọn ololufẹ wọn ati gbogbo ọmọ orilẹede Naijiria pe ki wọn tọju imọtoto wọn lasiko ajakalẹ arun yii. Awọn adẹrinpoṣonu bii Ushbebe to jẹ adẹrinpoṣonu, ati Ayọdele Makun to jẹ adẹrinpoṣonu naa. Bi a ko ba gbagbe arun coronavirus yii naa ti ṣọṣẹ laarin awọn ilumọọka ati wọọ-ki-ilu-mọ kaakiri agbaye. Ni ọjọ aje ni gbajugbaja oṣere sinima ni ilẹ Gẹẹsi, Idris Elba kede pe oun ti wa ni igbele bayii nitori oun pẹlu ti ko arun COVID-19 ti ọpọ n pe ni Coronavirus. Amọṣa o kọọ pe ""ara oun ji pepe, gbogbo ami to si maa n farahan lara ẹni to ba ni arun naa ko jẹyọ lara oun o oun si ti fi ara oun si igbele lati igba ti oun ti fidi rẹ mulẹ pe oun ni arun yii' Bakan naa, Tom Hanks ati Rita Wilson lorilẹede Naijiria naa ti koo. Hanks kede faraye pe oun ati iyawo oun, Rita ti ko arun naa lorilẹede Australia. Kristofer Hivju to jẹ ọkan pataki lara awọn oṣere to kopa ninu sinimọ 'Game of thrones"" naa kede pe oun pẹlu ti ko arun ọhun. O nioun atawọn mọlẹbi oun ti fi ara wọn si igbele titi di igba ti aisan naa yoo fi wọn silẹ. Amọṣa o ni 'ṣaka lara emi ati idile mi le'",0,yoruba Isegun yi àlùfáà lo je gbogbo ise ibile tèmi. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba "Boya eyi ni gbajumọ osere tiata kan lobinrin, Folukẹ Daramọla Salakọ ro, to fi kọ̀ ironu akewi soju opo Instagram rẹ, eyi to fi n gba awọn akẹẹgbẹ rẹ nimọran nipa igbe aye rere. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Foluke ni ko si bi eeyan kan se lero pe oun gbajumọ to, saa ni yoo ni, ti irawọ rẹ yoo si tan fun igba kan nitori ko lee jẹ irawọ ti yoo tan fun gbogbo igba. O ni awọn irawọ atijọ yoo wọọkun lọjọ kan, ti awọn irawọ tuntun yoo si maa dide bii itanna lawọn akoko kan. Osere tiata naa ni ojoojumọ ni wọn n bi awọn irawọ tuntun, ti awọn irawọ kan si n jade laye, amọ ohun to se pataki ni pe ki eeyan jẹ gbajumọ to pegede. O ni iru ẹni bẹẹ gbọdọ jẹ ẹni to n ko ipa gidi si awujọ to wa, ati ẹni ti eeyan lee gbẹkẹle, ti wọn yoo si maa gboju soke wo lọọkan bii awokọse rere gẹgẹ bii iwuri ati koriya lati de ibi giga, tabi ẹni to n huwa rere, ti wọn lee wo lati se imusẹ awọn afojusun wọn nile aye. Daramola ni Gbajumọ kii se gbajumọ gidi ti igbe aye rẹ ko ba lee se iwuri fun awọn ẹlomiran lati se lakaka fun ohun to dara ti wsn n fẹ laye. O wa kadi asamọ rẹ nilẹ pe gbajumọ ko nilo lati maa tẹ ifẹ awọn eeyan kan lọrun ki wọn lee nifẹ rẹ nitori irufẹ igbe aye to n gbe ati awọn aseyọri rẹ, amọ o yẹ ko lee se koriya fawọn ẹlomiran lati lakaka de ibi giga.",0,yoruba "ọsẹ àlùfáà. Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.",0,yoruba "Ojú tó r'íbi tí kò fọ́, ó npadà bọ̀ wá r'íre. #DanaAir",0,yoruba "Ọ̀pọ̀ ènìyàn ni ò mọ̀ pé Ọjọ́-ọ̀sẹ̀ ti wà pẹ̀lú wa ti pẹ́, kí ojú tó ó là. Ọjọ́ #Orunmila; Ẹlẹ́rìípín nílẹ̀ #Yoruba ni Ọjọ́-ọ̀sẹ̀/Ọjọ́ awo.",0,yoruba "Amọ, bi awọn arẹwa Olori ṣe rọgba yi Iku Baba ka naa ni Eleduwa fi awọn ọmọ to rẹwa ta baba lọrẹ. Laipẹ yii ni Ọmọbabinrin Adedoja Adeyemi gba ami ẹyẹ arinrin oge gẹgẹ bi ọdọbinrin to rẹwa julọ nipinlẹ Oyo. Adedoja, ẹni ọdun mẹrinlelogun gba la awọn oludije mii ti wa lati ẹkun mẹrinla ipinlẹ mọlẹ lati gba ami ẹyẹ naa. Ọmọbabinrin Adedoja gba ẹbun ọkọ ayọkẹlẹ Toyota Camry lọ ile atawọn ẹbun miiran. Adedoja to kẹkọọ gboye nipa itan nile iwe fsaiti ipinlẹ Oṣun, UNIOSUN ti lọ si aafin Oyo fun adura lati ẹnu baba lẹyin to pegede tan nibi idije to ti kopa. Ọmọbabinrin Adedoja n kẹkọọ lọwọ bayii lati gboye ẹkeji ni fasiti ilu Eko, UNILAG lori ilẹ Afirika. Oun ni oludari ẹgbẹ kan to n ṣeranwọ fawọn ọmọ to ba ni arun foni ku fọla n de tawọn oloyinbo maa n pe ni SS.",0,yoruba Ọkan tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà.. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba "obìnrin ri pe lẹ ìkòkò wey ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Nitori eyi, ara eni ni nfàn ojú kakaaki.",0,yoruba "Ó dìgbà ó se, Arsene Wenger dágbére fún Arsenal Arsenal f'agba han ikọ Burnley ninu ifẹsẹwọnsẹ to jẹ eleyi to kẹyin ti Wenger yoo jẹ oludari ikọ naa ni papa isere Emirates. Ẹlẹsẹ ayo Pierre-Emerick Aubameyang gba ayo meji wọle ninu ere bọọlu naa. Ọmọ Nigeria Alex Iwobi, Alexander Lacazette ati Sead Kolasinac naa wa lara awọn to gba bọọlu s'awọn ninu ifẹsẹwọnsẹ naa. Ikọ alatako Burnley ati awọn agbọọlu Arsenal se ayẹsi fun Wenger ki ifẹsẹwọnsẹ to bẹrẹ. Arsenal f'agba han ikọ Burnley ninu ifẹsẹwọnsẹ to jẹ eleyi to kẹyin ti Wenger yoo jẹ oludari ikọ naa ni papa isere Emirates Wenger to jẹ ẹni ọdun mejidinlaadọrin gba ife ẹyẹ mẹwa to jọju ni ọdun mejilelogun ti o lo gẹgẹ bi akọnimọọgba Arsenal.",0,yoruba eḳọ nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o nuni ti o tẹ.,0,yoruba oni ni o pe odun mokanlelogbon to baba agba pa james adegbite ti lo sinmi laya olodumare sunre o baba oninure,0,yoruba ibile. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà.,0,yoruba Mà á ri dájú pé gbogbo ètò ìdìbò 2023 kẹ́sẹjárí – Buhari,0,yoruba Pèrègún tí ń bẹ lódò kìí kú. Ọdọọdún ní í yọ àwọ̀ tuntun. #ekaaaro #omoYoruba,0,yoruba "Aṣọ ẹ̀yẹ ìkẹhìn tí ọmọlẹ́bí fi fún òkú, tí òkú yíó gbé wọ ibi-ojì ni aṣọ-ẹbí. #AsoEbi #Yoruba",0,yoruba ènìyàn ni ó pa Ọba lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba "tí Ọmọ fè mú, Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba "Ikọ̀ Portugal fi Super Eagles panu níbi ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ olọ́rẹ̀ẹ́ sí ọ̀rẹ́ tó wáyé ní pápá ìṣeré José Alvalade nílùú Lisbon lálẹ́ yìí. Ami ayo merin si odo ni ikọ agbabọọlu Portugal fun ti Super Eagles Naijiria. Idije ife ẹyẹ agbaye yoo bẹ\rẹ ni orilẹ-ede Qatar. Naijiria ko pegede lati kopa nibe rara. Ẹgbẹ agbabọlu Super Eagles Naijiria yoo koju Portugal fun ifẹsẹwọnsẹ ọlọrẹsọrẹ  kan lọjọbọ. Ifẹsẹwọnsẹ yii n waye lọjọ diẹ si ibẹrẹ idije ife ẹyẹ agbaye Qatar 2022. Orilẹede Naijiria ko ni kopa ni idije ife ẹyẹ agbaye FIFA yii ṣugbọn Portugal yoo kopa, wọn yoo si ma koju Ghana, Uruguay ati South Korea ni ipin H. Ifẹsẹwọnsẹ yii yoo waye lẹyin ifọrọwerọ Christiano Ronaldo pẹlu Piers Morgan to gbalẹkan bayii nibi to ti bu ẹnu atẹ lu awọn alaṣẹ Manchester United pe wọn da oun. Nigba wo ni ifẹsẹ̀wọnsẹ Portugal ati Naijiria yoo waye? Ifẹsẹwọnsẹ naa yoo waye ni Ọjọbọ, ọjọ kẹtadinlogun oṣu kọkanla ni nnkan bii agogo mẹjọ ku iṣẹju marundinlogun aṣalẹ. Agbabọọlu mẹtalelogun ni Naijiria pe fun ifẹsẹwọnsẹ naa. Amọṣa, akọnimọọgba Super Eagles, Jose Peseiro ti fi Cyriel Dessers rọpo Victor Osimhen, ti Chidozie Awaziem fun Olisah Ndah nitori pe wọn ṣeṣe. Aṣọle: Maduka Okoye, Francis Uzoho, Adebayo Adeleye Agba ọwọ ẹyin (Defenders) : William Ekong, Olisa Ndah, Calvin Bassey, Kevin Akpoguma, Chidiebube Duru, Tyronne Ebuehi, Bruno Onyemaechi, Bright Osayi Samuel Agba ọwọ aarin (Midfielders) : Joseph Ayodele-Aribo, Alex Iwobi, Wilfred Ndidi, Frank Onyeka, Oghenekaro Etebo Atamatase (Forward) : Moses Simon, Samuel Chukwueze, Ademola Lookman, Terem Moffi, Paul Onuachu and Emmanuel Dennis Aṣọle: Diogo Costa, Jose Sa, Rui Patricio Agba ọwọ ẹyin (Defenders) : Diogo Dalot, Joao Cancelo, Danilo Pereira, Pepe, Ruben Dias, Antonio Silva, Nuno Mendes, Raphael Guerreiro Agba ọwọ aarin (Midfielders) : Joao Palhinha, Ruben Neves, Bernardo Silva, Bruno Fernandes, Joao Mario, Matheus Nunes, Otavio Monteiro, Vitinha, William Carvalho Atamatase (Forward) : Andre Silva, Cristiano Ronaldo, Goncalo Ramos, Joao Felix, Rafael Leao, Ricardo Horta",0,yoruba ".@user ti aro wipe o gbon, ase bintin lopolo re. Oni ti a o ba dibo fun GEJ Niger Delta yio no wa ni pasan http://t.co/EInnW5uTLb",0,yoruba "Asiko ko dẹrun fun minisita fun eto iṣuna lorilẹede Naijiria, @user lọwọlọwọ pẹlu iroyin kan to n ja kaakiri bayii pe ayederu ni iwe ẹri agunbanirọ ti o n gbe kiri. - NYSC: Kẹmi Adeọṣun ń rì sínú ọ̀gbun ayédèrú ìwé ẹ̀rí https://t.co/Xj5OtpAhfP",0,yoruba "Damilọla ni ọda owo lo sun oun de idi lilo iyarun lati maa fọn fere si orin Fẹla. O fikun pe, ibatan oun kan lo kọ oun lati lo nkan miran pẹlu ọra, ki oun si fọn bii fere, ti oun si n lo iyarun. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọkunrin to n fọn iyarun bii fere naa ni, lati igba ti wọn ti ya iyarun naa si mimọ ninu ẹgbẹ akọrin nile ijọsin oun, ni ohun gbogbo ti yipada. Damilọla wa rọ awọn obi lati maa se iwuri fun awọn ohun ara ọtọ, ti awọn ọmọ wọn ba n se, ki wọn ma si lero pe nkan naa ko seese. O fikun pe laye ode oni, ohun ti aye ko ka si nkankan ni awọn eeyan n tẹwọgba.",0,yoruba "Nkan ti baba fi ju ọmọ lọ ni ẹgbẹ agbabọọlU liverpool fi ọrọ ṣe pẹlu bi wọn ṣe din dundun iya goolu meji si odo fun Chelsea. Ifẹsẹwọnsẹ naa to waye nile Chlesea jẹ akọkọ ti wn yoo gba nibẹ lati igba ti saa bọọlu tuntun ti bẹrẹ. Sadi Mane agbawaju Liverpool lo jẹ goolu mejeeji to mu ki Liverpool gunke si ipo kẹẹta lori afara Liigi. Chelsea wa ni ipo ikẹwa bayi ti Arsenal asi n tọ Everton lẹyin ni ipo keji. Aṣiṣe meji lo ṣokunfa ifidirẹmi Chelsea ninu ifẹsẹwọnṣẹ naa. Akọkọ ni ti Christensen to gba kaadi pupa lẹyin to fa Sane titi to fi ṣubu lasiko to n gbiyanju lati lọ jẹ ni ile Chelsea. Nitori eyi, eeyan mẹwa dipo mọkanla ni Chelsea fi gba ifẹsẹwọnsẹ naa ti eleyi si fun Liverpool lagbara lati wọle siwọn lara. Aṣiṣe ẹlẹẹkeji ni ti aṣọle Chelsea Kepa Arizzabalaga to jẹ ki Sane gba goolu keji wọle.",0,yoruba ojo = coward ojo ni òjó òjó is a coward,0,yoruba mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò.,0,yoruba Ìròyìn tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa òkè: ti o lẹ. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò.,0,yoruba ìwé orisirisi. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́.,0,yoruba "yi fi ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "ó wáyé.. Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba "ènìyàn wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn ẹ̀kọ́ ọmọ aláwọ̀ wà níṣẹ̀.",0,yoruba Adeoye Damilare disabled shoe maker: Bí ẹ̀sẹ̀ mi méjèjì ṣe dédé di jọwọlọ láàrin òru ọ̀gànjọ́ ní kékeré nìyí,0,yoruba Tinubu Presidential Ambition: Aisha Yusuff fèsì padà bí Tinubu ṣe ní káwọn ọ̀dọ́ sẹ́ńpẹ́ fún ipò ààrẹ,0,yoruba won kan baa oya jaa nii sango loo nii seeree dun nii ede,0,yoruba "Oruko mi ni Paulu omo Ademujimi lati ilu Odode Idanre ni Ipinle Ondo. Iwo ti o ba wa lati ilu mi, feran tweeti yii #TweetInYoruba",0,yoruba ó ṣeun mo dúpẹ́ gidi ganan ni,0,yoruba "Ọgbọ́n ò pín síbì kan, kò sẹ́ni mọ̀ tán. A ní ọgbọ́n níbi, ó yẹ kí a múu ṣiṣẹ́ pọ̀ mọ́ ti ọ̀gá bí a ò bá fẹ́ lo ògede rẹ̀. #OmiInira57",0,yoruba "Bí a bá wí, a ó kù ú, bí a ò wí, ọ̀run là ń lọ. Ó ní bí a ti ṣe ń ṣe nílẹ̀ẹ Yoòbá. Ṣebí wọ́n ní bí a ṣe ń ṣe níbí, èèwọ̀ ibòmíì. Ẹbí méjì ní í ṣe ìgbéyàwó, ẹbí ọkọ àti ẹbí aya. #IleOkoIleEko #Yoruba",0,yoruba ìbàdandun ìlú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìwà: ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó ṣe pàtàkì.,0,yoruba nípa òkè: ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa òkè: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba "Kò sí orin ìbílẹ̀ tí a ò ní fetí kó ìrírí ayé, àkànlò èdè, ìjìnlẹ̀ ọ̀rọ̀ àti onírúurú òwe. #Sakara #Yoruba #Ajinde",0,yoruba . @user Ó hàn gedegbe pé ipá ìjọba wa kò ká àwọn èèyàn bókobòko wọ̀nyí. #BokoHaram,0,yoruba ẹkọ́ ṣẹlẹ ni Ibadan ti gbogbo eniyan sọ o dara. (2019),0,yoruba @user Bẹ́ẹ̀ni oòrùn ràn tẹ́lẹ̀ ṣùgbọ́n ó ti sá pamọ́ báyìí o!,0,yoruba "Láti ìgbà náà a ò rí ètọ́ kan pàto rí dì mú, ọdún mẹ́rìnlá tí a ti ń ṣe ìjọba tiwa. Ẹ duò náà, ẹ jọ́, kíni á ńpè ní ìdàgbàsókè gan-an?#May29",0,yoruba Nínú òǹkà kí ni ọ̀rìnlérúgba? #Ibeere #Yoruba,0,yoruba "àtọ́wọ́dá, àwọn oníṣẹ́ ìṣẹ́ ni a ní láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba ojú tí yóò ròhìn ogun ò ní kú sógun a warrior destined to recount war stories wont perish in battle keep hope alive better days are still ahead,0,yoruba "Bàbá fè lọ, Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Akẹkọọ naa, Toyinbo Olayinka wa ni ipele kẹ́rin tii ṣe aṣekagba, wọn ji i gbe lọjọ Abamẹta to kọja ni agbegbe Abule Itoko to to iwọn kilomita mẹwa si ọgba ileewe naa. Alukoro fasiti FUNAAB to kan si BBC, Kola Adepoju lo sọ aridaju pe wọn ti da a silẹ lalafia lalẹ Ọjọ Aje. Eyi jẹ lẹyin ti awọn akẹgbẹ rẹ ṣe iwọde ninu ileewe. Ọgbẹni Kola ko sọ boya awọn ajinigbe kan da a silẹ tabi ẹnikẹni san owo idoola rẹ. Ẹ wo àwọ́n lọ́balọ́ba tó ti ṣàtìlẹ́yìn jíjá fún Oduduwa Nation ní ilẹ̀ yorùbá Njẹ́ o mọ̀ pé iléèṣẹ́ kan ní UK ti ra orúkọ́ ẹ̀yà Yorùbá tí ẹlòmìí kó fi ní le lò ó? Ìdí tí àwọn aṣòfin ṣe fẹ fagilé NYSC, ohun táa mọ rèé Àwọn Ọ̀gágun tó ṣeéṣe kó gba ipò olórí àwọn ọmọogun lẹ́yìn ikú Attahiru nìyìí Ọdún 32 ni mo fi ṣiṣẹ́ oko mọ́ ìṣẹ́ tíṣà kí àwọn ọmọ mi le jẹ́ èèyàn, àmọ́ ikú mú Taiwo lọ - Baba Taiwo Asaniyi A ti ń fẹ́ Hausa, Ibo, ó sàn ka jọ ṣe é ní tùbí-ǹ-nùbí lórí ọ̀rọ̀ Nàìjíríà ju ìjà ogun lọ - Ọba Alara ""Lai si ipalara, ninu ilera pipe ni wọn tu u silẹ. Ẹkunrẹrẹ lori itusilẹ rẹ ko pọ ati pe gbogbo ẹ wa lọwọ awọn Ọlọpaa ipinlẹ Ogun"". O ni lorukọ awọn alaṣẹ ileewe fasiti naa, awọn dupẹ fun awọn oṣiṣẹ alaabo, atawọn to jẹ ti ijọba ateyi ti kii ṣe tijọba paapaa ileeṣẹ Ọlọpaa Ogun. Atawọn oniroyin to fi mọ awọn lọbalọba ati gbogbo awọn ti ọrọ̀ kan ni wọ́n ranṣẹ idupẹ si lori itusilẹ akẹkọ naa. Akẹ́kọ̀ọ́ FUNAAB tí wọ́n gbé lọ ló ń rán ara rẹ̀ nílé ìwé Agbẹnusọ fun Fasiti ti wọn ti n kẹkọọ eto ọgbin, FUNAAB, Adepoju Kola, ti sọ pe akẹkọọ ti ile ẹkọ naa, Olayinka Toyinbo ti awọn ajinigbe gbe lọ kii ṣe agbegbe ile ẹkọ naa ni wọn ti gbe e lọ. Ọgbẹni Kola ṣalaye pe ni abule kan ti wọn n pe ni Itoko ni ijọba ibilẹ Odeda ni wọn ti gbe Toyinbo lọ nibi to ti n ba ẹnikan ṣiṣẹ ninu oko rẹ. ''O ṣeni laanu pe akẹkọọ yii lo n ran ara rẹ lọ si ile ẹkọ plu iṣẹ ti o n ṣe"". Mo dúpẹ́ pé ìgbà tí mo wà nínú Jesu ni mo lọ sẹ́wọ̀n, tó bá jẹ́ pé mo wà nínú áyé ni ... - Wòlìí Genesis Ati pe lori oko to ti n ṣiṣẹ naa ni o ti n sun ki iṣẹlẹ ọhun to ṣẹlẹ,'' Ọgbẹni Kola ṣalaye. Lori boya awọn ajinigbe n beere fun owo itusilẹ fun akẹkọọ naa, Kola ni oun ko le sọ ohun kan nipa ọrọ naa. ''A ti fa ọrọ naa le ọlọpaa lọwọ, awọn ọlọpaa yii ṣi ti n ṣiṣẹ takun takun lati ri pe wọn doola akẹkọọ naa lakata awọn ajinigbe. A ko tiẹ fẹ maa pariwo gan an lori ọrọ yii ki o maa ba ṣakoba akẹkọọ wa to wa lakata awọn ajinigbe. Àbọ̀ wá bá ni ọ̀rọ̀ Iyabo Ojo àti Yomi Fabiyi lórí ọ̀rọ̀ bàbá Ijẹsha - Damola Olatunji, ẹgbẹ́ TAMPAN Àwọn Ọ̀gágun tó ṣeéṣe kó gba ipò olórí àwọn ọmọogun lẹ́yìn ikú Attahiru nìyìí Ọ̀rọ̀ Yorùbá Nation ń fa aáwọ̀ láàrin Gani Adams àti Sunday Igboho Awọn akẹkọọ akẹgbẹ rẹ tu yaya jade lati ṣe ifẹhonuhan lori bi wọn ti ji Toyinbo gbe lọ. Amọ iwọde alaafia ni wọn ṣe, ọdọ awọn ọlọpaa ni wọn ṣe iwọde lọ lati fi ẹhonu wọn han, wọn ko si ba ohun kohun jẹ,'' agbẹnusọ fasiti FUNAAB lo sọ bẹẹ. Ọjọ Abamẹta ọsẹ to lọ ni wọn gbe Toyinbo lọ ti wọn si n wa di akoko yii.",0,yoruba mo ni inudidun pe ede iya mi jẹ yorùbá nitoripe o ni ohunini pataki pupọ,0,yoruba onà.. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba àìkú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "Ní ìlú kan, Ìyá ni olùkó. àkóbì asin. A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..",0,yoruba "Ọpọ awọn osere tiata yii lo n para poro nipa awọn isẹlẹ iwa ipa to n waye lemọlemọ laarin lọkọ laye, ti wọn si n kilọ fun tọkunrin-tobinrin lati sọrase. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Toyin Abraham, loju opo Instagram rẹ lo n wa ẹkun mu poroporo, to si ni oun ko tii sunkun to bayi ri laye oun, ti idajọ naa si ba oun lọkan jẹ. Toyin Abraham wa n gba awọn lọkọlaya nimọran pe ti ede wọn ko ba yede mọ, ti igbeyawo wọn si n la ina kọja, yoo kuku dara ki tọkọtaya yago funra wọn, dipo ki wọn sekupa ara wọn. Mama Ire, ẹni to n gbarata lori ohun ti yoo sẹlẹ si ọmọ ọwọ ti Maryam Sanda gbe dani lasiko ti wọn dajọ iku fun, wa n rawọ ẹbẹ si ọba oke pe ko siju aanu wo obinrin naa. Bakan naa ni ilumọọka osere tiata miran, Femi Adebayo fi fidio kan to se si oju opo Instagram rẹ, to si n rọ awọn eeyan pe ibasepọ lọkọlaya kii se tipa tikuuku. Femi naa wa gba awọn tọkọtaya nimọran pe, ti igbeyawo wọn ko ba mu adun lọwọ, yoo dara ki wọn pin gaari, ki olukaluku si ba tirẹ lọ. Femi Adebayo, ti gbogbo eeyan mọ si Jẹlili, wa n beere pe ""Bawo la se fẹ sọ fun ọmọ tuntun ẹjẹ ọrun naa pe iya rẹ lo pa baba rẹ, idi si ree ti wọn se yẹgi fun oun naa. Ohun ibanujẹ nla gbaa ni."" Femi, ti oju rẹ kọrẹ lọwọ lori isẹlẹ bi wọn se dajọ iku fun Maryam Sanda wa rawọ ẹbẹ sawọn eeyan pe ""Ẹ jọwọ, ẹ dakun, mo rọ yin, ẹ jẹ ka maa sọra fun inufufu ati igbonara, ẹni apọnle ni abuku n wa kiri, adura mi si ni pe Ọlọrun oba yoo maa dari isisẹ wa."" Ko tan sibẹ, osere tiata obinrin miran, Tayo Sobola, to mura bii ẹni ti ọfọ sẹ loju opo Instagram rẹ ni imura oun lo n se afihan ipo ibanujẹ ti oun wa nitori inu oun bajẹ lori idajọ iku ti wọn se fun Maryam Sanda. Tayo ni ""Ile aye! Ibinu jẹ mihuwasi to lagbara pupọ eyi to maa n kesi eeyan lati kọbi ara sii amọ ibeere to yẹ ka bi ara wa ni pe bawo ni a se lee se akoso ibinu wa si?"" Sotayo salaye pe oun wo bi igbẹjọ Maryam Sanda, ti wọn dajọ iku fun tori pe o pa ọkọ rẹ lọdun 2017, se ti lọ nile ẹjọ, ti oun si rinrin ajo lai kuro loju kan soso. ""N ko tiẹ mọ ohun ti eeyan lee sọ, amọ mo kan n jẹrora ninu ọkan mi ni, ti mo si n woye pe bawo ni wọn yoo se yẹgi fun obinrin akẹẹgbẹ mi? Amọ ohun to daju ni pe lootọ lo pa ọkọ rẹ, boya lati ipasẹ asise ni abi o mọọmọ see."" Sobola fikun pe Maryam gba ibinu lati gbakoso ọkan rẹ, ohunkohun si lo lee fa isẹlẹ yii, koda awọn ọkunrin lee ti obinrin debi pe yoo fi gbẹmi eeyan, bakan naa si lawọn obinrin kan ni aseju lọwọ, ti wọn si maa n se idajọ lọwọ ara wọn, eyi to maa n mu ki nkan polukumusu sii. ""Amọ ootọ ọrọ to wa nilẹ ni pe a lee yago fun awọn nkan kan nitori ojoojumọ ni ọpọ iroyin n wa nipa awọn ọkunrin to n pa iyawo wọn ati awọn obinrin to n pa ọkọ wọn, tawọn afẹsọna lọkunrin-lobinrin naa si n gbẹmi ara wọn nitori ẹsun sise oju meji."" Osere tiata ọhun wa rawọ ẹbẹ sawọn eeyan pe ki wọn maa tiraka lati rin jinna si ohunkohun to ba lee fa wahala ba aye wọn tabi ge ẹmi wọn kuru, to si tun rọ wọn lati ta kete si ija, ki wọn si tun kẹyin si awọn eeyan to ba lee ru ibinu wọn soke. Pásítọ̀ ìjọ Redeem, Ọ́mọ́ọ́ba kan l'Eko ati èèyàn mẹ́ta míì rèé to ti gba ìdájọ́ ikú rí Sise idajọ iku fawọn ti ile ẹjọ ba fi idi ẹri mulẹ pe wọn ṣeku pa eeyan akẹẹgbẹ wọn, kii ṣe nkan tuntun. Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko fẹ̀sùn kan Lekan Shonde pé ó lu ìyàwó rẹ̀ pa, lẹ̀yín to fi ẹ̀sùn kan pé iyawo rẹ̀ pé óún yan àlè. Koda ofin orileede Naijiria fi ofin gbe awọn agbofinro lẹyin, lati se amusẹ idajọ iku tile ẹjọ ba da, lẹyin ti Gomina ipinlẹ tabi Aarẹ ba ti buwọlu aṣẹ yii. Iroyin idajọ iku fun arabinrin Maryam Sanda to pa ọkọ rẹ nilu Abuja, to waye lọjọ Aje, tun jẹ ohun aritọkasi pe iru idajọ iku bayii ṣi n waye ni Naijiria. Amọ melo ni iru awọn eeyan to daran ipaniyan, ti ile ẹjọ dajọ iku fun, ti ẹyin ranti? E jẹ ka ran ara wa leti nipa diẹ ninu wọn: Ọmọ Ọba Eko Adewale Oyekan: Ẹni aadọta ọdun ni ọmọọba Eko ana, Adewale Oyekan, ti o si gba idajọ iku lọdọ adajọ ile ẹjọ giga kan nilu Eko lori ẹsun pe o pa oniṣowo kan, Alhaja Sikirat Edun. Gẹgẹ bi ohun ti a ri akọsilẹ rẹ, ọmọọba Adewale Oyekan fun Lateef Bello, tii se ọmọ ọdọ Alhaja Edun ni ẹgbẹrun lọna ọgọta Naira. lati pa ọga rẹ. Iwaadi awọn ọlọpaa fihan pe wọn yin oloogbe lọrun pa, ti wọn si ju oku rẹ sinu kanga to wa ninu ile rẹ. Osere tiata lapa oke ọya, Rabi Ismaila: Oṣere tiata lapa ariwa ilẹ Naijiria ni Rabi Ismaila, to si fi ilu Kano ṣe ibudo. Ẹsun ti wọn tori rẹ dajọ iku fun ni pe o pa ọrẹkunrin rẹ, ọgbẹni Auwalu lọdun 2002. Ile ẹjọ giga ni Kano dajọ ki wọn yegi fun, titi ti ẹmi yoo fi bọ lara rẹ. Rabi tawọn eeyan mọ si Rabi Cecilia ninu sinima, tan ọrẹkunrin rẹ lọ si adagun omi kan, ti o si fun ni majele jẹ ki o to ju oku rẹ sinu omi. Pasitọ ijọ Redeem, Akolade Arowolo to pa iyawo rẹ: Pasitọ awọn ọdọ kan ninu ijọ Redeem naa gba idajọ iku lori pe o pa iyawo rẹ, Titilayo to n ṣiṣẹ ni ile ifowopamọ kan. Orukọ pasitọ naa ni Kolade Arowolo, ti ile ẹjọ si fidi ẹsun iwa ọdaran naa mulẹ pe oun funra rẹ lo pa iyawo rẹ sinu ile wọn. Ẹjọ yi mu iriwisi wa ti awn eeyan si n ṣe emo bi ẹni to pe ara rẹ lẹni Ọlọrun ṣele hu iru iwa bayi. Iwaadi fihan pe igba 76 ni o gun iyawo rẹ lọbẹ ti adajọ si fi wakati mta gbako ka idajọ rẹ. Khadijat Oluboyo, ti ọrẹkunrin rẹ oniyahoo yahoo ṣeku pa: Ni oṣu kẹta ọdun 2019 ni ile ẹjọ giga ni ipinlẹ Ondo da ẹjọ iku fun Seidu Adeyemi to pa ọmọ igbakeji gomina ana nipinlẹ Ondo, Khadijat Olubọyọ ni ọdun 2018. Seidu Adeyemi to jẹ ọrẹkunrin Khadijat Oluboyo ni wọn fẹsun kan wi pe o pa a, ti o si tun rii mọle si inu yara rẹ ni Aratusi, Oke-Aro ni Akure, nipinlẹ Ondo. Khadijat Oluboyo n mura lati jade fasiti ni ile iwe giga fasiti Adekunle Ajasin ni Akungba Akoko ni ipinlẹ Ondo, ki o to jade laye. Ọ̀rẹ́kùnrin Khadijat Olubọyo gba ọjọ́ ikú Lẹyin ọsẹ kan tí wọn ti ń wá Khadijat tó jẹ́ ọmọ igbákeji gómínà tẹ́lẹ̀rí ní ìpínlẹ̀ Ondo, ni wọ́n bá òkú rẹ̀ ní ilé àfẹ́sọ́nà rẹ̀, Adeyemi Alao. Alukoro fun ile iṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ondo to ba BBC Yoruba sọrọ lasiko ti isẹlẹ naa waye sọ wi pe, ṣe ni Adeyemi gbe oku Khadijat sinu ile fun ọjọ mẹfaki ẹnikẹni maa baa fura si. Stella fi ibinu pa Stella alabagbe rẹ, o gba idajọ iku Orukọ kanna ni wọn jijọ njẹ ṣugbọn arabirin Stella Gilbert ko wo eyi mọ alabagbe rẹ, Stella Godwin lara, ko to fi ibinu gun lọbẹ pa. Ile ẹjọ ko ṣe iye meji ki o to dajọ pe o jẹbi ẹsun ipaniyan ti ijọba ipinlẹ Eko fi kan. Ẹṣẹ ipaniyan to hu yii si lo tako ofin ọdaran tipinlẹ Eko, abala okoolerugbao le kan. Adugbo Ajegunle ni ojule kọkandinlọgọta, Opona Ojora ni iṣẹlẹ naa ti waye ni ọjọ kejilelogun oṣu Kẹfa ọdun 2013. Stella sọ pe, looto loun gun alabagbele oun lọbẹ laya amọ lẹẹkan ṣoṣo ni. Eyi si lo mu ki ile ẹjọ dajọ iku fun.",0,yoruba "Gutterres sọ eyi lasiko to n fi iroyin bi nkan se n lọ lagbaye to Igbimọ Ajọ Agbaye to n risi ẹtọ ọmọniyan lagbaye leti. O sọ wi pe orilẹede aadọsan lo ti fofin de idajọ iku tabi ti wọn ti wọgile ọna isekupani yiii, nigbati awọn orilẹede miran ti se ofin to n gbero lati fagile ise naa, ti wọn ko si se idajọ iku ni ọdun mẹwa. Àwọn ìlú tó ti fòpin sí ìsekúpani Ajọ Isọkan Agbaye naa ni awọn iroyin lati ọwọ awọn orilẹede naa, awọn ajọ ajafẹtọ ọmọniyan ati awọn to fi ọju gan ni awọn isẹlẹ naa. Amọ, Ajọ to n ja fẹtọ ọmọniyan, Amnesty International sọ wi pe, orilẹede mejilelogoje lo ti fi ọwọ osi juwe ile si sise idajọ iku, ati wi pe, orilẹede mẹtalelọgbọn lo ti se idajọ iku laarin ọdun marun. Ìsekúpani ní àgbáyé Orilẹede mẹrin bii Saudi Arabia, Iraq, Pakistan ati Iran lo ti kopa ninu idajọ iku ni ọdun 2017, pẹ̀lú orilẹede China ti wọn ko yẹ ki iye rẹ han si ita. Ajo ajafẹtọ ọmọniyan lagbaye sọ wi pe, awọn ọna ti wọn n gba pa eniyan ni ki wọn bẹ ori wọn, ki wọn so okun mọ wọn lọrun titi ẹmi yoo fi bọ lara wọn, ati fifun eniyan ni abẹrẹ iku, pẹlu yi yin wọn ni ibọn. Awọn orilẹede to se idajọ iku ni ọdun 2013 si 2017: Amọ, Ajọ Amnesty International ko le e sọ pato, boya orilẹede ti ogun ti n sẹlẹ lọwọlọwọ bii Libya ati Syria n se idajọ iku fun awọn eniyan. Awọn orilẹede to se idajọ iku ni ọdun 2013 si 2017 Awọn orilẹede mọkandinlogun ni ko se idajọ iku lasiko ti ko ti le jẹ eewọ.",0,yoruba "Iṣẹlẹ naa ni a gbọ pe o ṣẹlẹ ni aafin ọba to wa ni Kuta, ijọba ibilẹ Ayedire nibi ti Gomina Adegboyega Oyetola ti lọ ṣi afara kan ti ileeṣẹ ọmogun ilẹ kọ. Ohun ti a gbọ ni pe Dade n yinbọn soke pẹlu idunnu nigba ti wọn n ṣi afara naa lẹyin naa ni ọta ibọn ti ṣeeṣi ba Adebowale. Agbẹnusọ fun ajọ NSCDC, Adigun Daniel to fidi iṣẹlẹ ọhun mulẹ ṣalaye pe eṣi lo ṣe fun Dade, ko mọọ mọ yinbọn fun un. O ṣalaye siwaju sii pe Dade ti n jẹjọ bayii lori iṣẹlẹ naa. Ọga agba ileeṣẹ ọmogun ilẹ ni Naijiria, Tukur Buratai naa wa ni ibi ayẹyẹ ṣiṣi afara ọhun.",0,yoruba Jose Mourinho: Ayélujára ń hó yaya lórí ọ̀rọ̀ Mourinho pẹ̀lú Arsenal,0,yoruba Èkó yii nípa àlùfáà ni nfàn ojú kakaaki.,0,yoruba "Awọn ileeṣẹ iroyin abẹle sọ pe Fatima Ribadu, to jẹ ọmọ Alaga akọkọ fun ajọ EFCC, Nuhu Ribadu, ti fẹ ẹ di iyawo Aliyu Atiku, to jẹ ọmọ igbakeji aarẹ nigba kan, Atiku Abubakar. Ọjọ Satide, ọjọ kẹta, oṣu Kẹwaa, ọdun 2020, ni iroyin sọ pe ayẹyẹ igbeyawo naa yoo waye, gẹgẹ bi akọsilẹ to wa lori kaadi ipe sibi igbeyawo ti BBC ri. Amọ , Fatima Ribadu ati Aliyu atiku, ko ti i sọ ohunkohun lori iroyin naa. Aliyu Atiku Abubakar jẹ jẹ oye Turaki Adamawa. Ọwọ baba rẹ, Atiku Abubakar lo ti jogun oye naa, lẹyin ti Atiku fi silẹ lati joye Waziri Adamawa lọdun 2017. Oye Turaki Adamawa jẹ ọkan lara awọn oye pataki ninu eto lọbalọba nipinlẹ Adamawa. Bakan naa ni Aliyu jẹ oṣiṣẹ banki, to si tun jẹ Oludari ileeṣẹ Priam Group, to jẹ apapọ gbogbo ileeṣẹ ti baba rẹ da silẹ. Awọn ileeṣẹ naa lo ni oṣiṣẹ to pọju lọ nipinlẹ Adamawa. Fatima Ribadu jẹ ọkan lara ọmọ marun-un ti Nuhu Ribadu bi. Bakan naa lo jẹ ọrẹ timọtimọ pẹlu ọmọ Aarẹ Muhammadu Buhari, Hanan, to sẹ igbeyawo laipẹ yii. Awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria si ti n sọ oriṣiriṣi nkan nipa igbeyawo awọn ọmọ agba oloṣelu mejeeji. Paapa nitori pe ẹgbẹ osẹlu ọtọọtọ ni wọn n ṣe: Atiku Abubakar jẹ ọmọ ẹgbẹ oṣelu People's Democratic Party, Nuhu Ribadu si jẹ ọmọ ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, amọ ipinlẹ Adamawa ni awọn mejeeji ti wa. Ohun ti ọpọ eeyan n sọ lori ọrọ igbeyawo naa ni pe awọn oloṣelu Naijiria kii ṣe ọta ara wọn, tako bi awọn araalu sẹ n ri wọn. Bakan naa ni awọn kan sọ pe o yẹ ki awọn ọmọ Naijiria to ma n ba ara wọn ja nitori oloṣelu tun ero ara wọn pa.",0,yoruba Àkójú ọ̀rọ̀ yi kún fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde sí ara ilẹ̀. (Item 122),0,yoruba "Ọba fè joko, Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.",0,yoruba "Ǹjẹ́ ìwọ́ mọ̀ pé Ẹ̀gbá ò tan mọ́n Òwu? Ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ la rìn wá ni wọ́n, àmọ́ Ẹ̀gbá ṣáájú Òwu dé ìlú Abẹ́òkúta. #Owuday #Yoruba #Ogun",0,yoruba "Kọmiṣọna eto abo ipinlẹ ọhun, Samuel Aruwan lo fidi ọrọ naa mulẹ fun BBC. Aruwan sọ pe akẹkọọ mọkanla ati oṣiṣẹ fasiti mẹta ni wọn gba itusilẹ lọwọ ajinigbe ọhun. Awọn agbebọn naa tu awọn eeyan naa silẹ lọjọ Abamẹta, ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu Karun un, ọdun 2021 loju ọna marosẹ Abuja si Kaduna. Meji lara awọn awọn obi awọn ọmọ naa sọ fun awọn akọroyin pe ọgọsan (180) miliọnu naira ati alupupu mẹwaa ni awọn ajinigbe naa gba ki wọn to tu awọn ọmọ wọn silẹ. Ọkan lara wọn ni ""Ọgọsan an miliọnu naira ni awọn ajijigbe naa gba lọwọ awa obi ki wọn to tu awọn ọmọ wa silẹ."" Democracy day 2021: Kí ni Nàìjíríà ti jèrè lára gbogbo ààrẹ tó ti jẹ látọdún 1999? ""A ko ri iranlọwọ kankan gba lọdọ ijọba lati tu awọn ọmọ wa silẹ, bẹẹ naa ni a ko ri aṣoju ijọba tabi ọlọpaa kankan lati to lọwọ si itusilẹ wọn."" Bi ẹ ko ba gbagbe, ogunjọ, oṣu Kẹrin, ọdun yii ni awọn ajijigbe naa ji awọn aẹkọọ ọhun gbe lẹyin ti wọn kọlu ile ẹkọ wọn. Ni ọjọ kẹtalelogun, awọn eeyan ilu ri oku mẹta ninu awọn akẹkọọ naa labule Kwanan Bature, eyii ti ko jina sile ẹkọ ọhun. Bode George: òòtọ́ ni ìkìlọ̀ Obasanjọ ati Soyinka Ọjọ mẹta lẹyin ti wọn ri oku awọn mẹta naa ni awọn agbebọn naa tu pa meji ninu awọn eeyan naa ti wọn ji gbe. Ẹwẹ, ọkan lara awọn akẹkọọ naa ti kọkọ gba itusilẹ ṣaaju lẹyin ti awọn obi rẹ san owo itusilẹ fun awọn ajinigbe naa.",0,yoruba "Fayose ni ẹnu n kun awọn osisẹ ijọba Buhari lori ẹsun ijẹkujẹ Gomina Fayose ni niwọn igbati owo ilu ba n tipasẹ awọn ibudo yii wọ apo awọn eeyan kan, ko lee si bi opin se lee de ba wahala Boko Haram lorilẹede Naijiria. Gomina ipinlẹ Ekiti naa, ẹni to ti fi ọpọlọpọ igba lewaju awọn ipe to tako ijọba to wa lode bayii lorilẹede Naijiria ni lọdun to kọja ni ajọ to n tọpinpin iwa ibajẹ lagbaye, Transparency International kede wipe iwa ibajẹ ati ijẹkujẹ laarin ileesẹ ọmọogun orilẹede Naijiria n se ọpọlọpọ akoba fun akitiyan lati dẹkun gulegule ẹgbẹ agbesunmọmi Boko haram. Fayose sọ wipe: ""A ti gbọ iroyin awọn to n ko ounjẹ atawọn nkan arẹmọlẹkun gbogbo to wa fun awọn ibudo atipo ati awọn ti ogun le lẹkun ila oorun ariwa orilẹede Naijiria si orilẹede Chad ati Niger, bẹẹni nkan bii igba tọọnu eso ti orilẹede Saudi Arabia gbe kalẹ f'awọn ibudo awọn atipo ati awọn ti ogun le ni wọn ti n ta kaakiri ọja nilu Abuja."" Gomina ipinlẹ Ekiti naa sọ wipe asiko to fun Aarẹ Buhari lati pakiti mọra se afọmọ ijọba rẹ ki o si yọ gbogbo awọn to n fi wahala Boko Haram jẹun ninu ijọba danu bi ẹni yọ jiga iyẹn to ba jẹ lootọ lo n fẹ ki gulegule awọn Boko Haram o dopin.",0,yoruba olúwa à jẹ ki wọn pẹ ki wọn jẹ oúnjẹ ọmọ pẹ pẹ pẹ bi obi ṣe n pẹ lẹnú,0,yoruba emi gbadun itan re o,0,yoruba "#TweetinYoruba oruko mi ni Hassan Adebayo, Akanbi omo Jagun, omo Ago Ishona, ni ilu Oyo Alaafin. E kaaro. Aku ola Jimoh o. Emi ase opo e.",0,yoruba 9. Ìlẹ̀kẹ̀ yìí jẹ́ àmì ìdánimọ̀ òrìṣà ilẹ̀ Yorùbá wo? A. Ògún B. Ṣàngó D. Èṣù #ibeere #Yoruba #Iseselagba https://t.co/QO6OdFth6a,0,yoruba Omoluabi wa ni ìbadandun lo je ti ibile. A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà.. A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba 15. Ọ̀rọ̀ tó yídan-n-dé ni gúnlẹ̀ àti paradà nítorí wọ́n ní ju ìtumọ̀ kan lọ. Ṣe àpẹẹrẹ mìíràn. #ibeere #Yoruba https://t.co/z0zyv29u0H,0,yoruba "vidíò yorubá tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn yì í tún ṣe àwọn iṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba Ó sọ wípé ìgbéyàwó lè fi ààbò bo ọmọdébìnrin tí kò sí nílé ọkọ tí ó ti di abaraméjì láì tó ọjọ́ orí tí ó tọ́ .,0,yoruba "Aarẹ Frank-Walter Steinmeier lo ti kọkọ yan Merkel ko to di pe o sebura nile asofin kekere Awọn asofin orilẹede Germany lo yan-an pada pẹlu ibo ọtalelọọdunrun ati mẹrin, ti ibo alatako rẹ si jẹ okolelọọdunrun o din marun, nigbati awọn asofin mẹsan ko dibo. Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Aarẹ Frank-Walter Steinmeier lo ti kọkọ yan Merkel ko to di pe o sebura nile asofin kekere.",0,yoruba "Ní ọdún 2011 , ó lo oṣù méjì ní ẹ̀wọ̀n , àkókò yìí ni ìyàwóo rẹ̀ bí àkọ́bíi rẹ̀ , Khaled .",0,yoruba "Ọmọ Afirika mẹfa lo wa ninu ẹgbẹ agbabọọlu mejeeji yii Loni ni ko ni dọla ti agbaye yoo mọ ẹgbẹ agbabọọlu ti yoo pegede, fi gbọọrọ jẹ ka ninu idije UEFA champions league ti ọdun 2019. Ẹgbẹ agbabọọlu Liverpool ati Tottenham ni yoo maa figagbaga ni ipele aṣekagba idije naa lalẹ ọjọ Satide. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Amọṣa, eyi o wu ko gbe'gba oroke laarin awọn ẹgbẹ agbabọọlu mejeeji yii, o daju ṣaka pe ọwọ ilẹ Afirika ko ni gbẹyin lara ife ẹyẹ naa lọdun yii. Ko si idi meji fun eyi ju pe agbabọọlu ọmọ ilẹ Afirika mẹfa ọtọọtọ ni yoo kopa ninu ifẹsẹwọnsẹ naa. Igba akọkọ ree fun Tottenham ni ipele aṣekagba UEFA Champions league Eyi si tumọ si pe ikọ yoo wu to ba bori ninu ifẹsẹwọnsẹ naa, ọmọ Afrika yoo wa nikalẹ lati gba ife ẹyẹ naa. Fun ikọ Liverpool, agbabọọlu ọmọ ilẹ Afirika mẹrin lo wa ninu ikọ naa. Myanmar: kékeré ni wọ́n ti n kọ́ àwọn ọmọ nípa ọ̀nà oge ṣiṣe Agbabọọlu orilẹ-ede Guinea, Nabi Keita (lootọ oun ko ni kopa ninu ifẹsẹwọnsẹ yii nitori o fara ṣeṣe), Sadio Mane lati orilẹede Senegal, Joel Matip lati orilẹ-ede Cameroun pẹlu Mohammed Salah to jẹ agbabọọlu ọmọ orilẹ-ede Egypt. Fun ikọ Tottenham ni tirẹ, agbabọọlu orilẹ-ede Ivory Coast, Serge Aurier yoo wa n kalẹ lati darapọ mọ awọn ọmọ ilu rẹ bii Didier Drogba, Yayah Toure ati Solomon Kalou ti wọn ti f'igba kan ri gba ife ẹyẹ UEFA Champions League. Salah, Mane, Aurier, Wanyama yoo wọ ṣòkòtò kan náà láti gba ife ẹ̀yẹ UEFA Champions league ní ìlú Madrid Bakan naa ni Victor Wanyama, ọmọ orilẹede Kenya naa yoo wa nikalẹ fun ẹgbẹ agbabọọlu Tottenham hotspur. Odu ni ẹgbẹ agbabọọlu Liverpool ninu idije UEFA Champions league. Igba marun un ọtọọtọ ni wọn ti gba ife ẹyẹ yii; AC Milan ati Real Madrid nikan lo gba ife ẹyẹ yii ju wọn lọ. Real Madrid lo ṣi wọn lọwọ ninu awo ikẹfa ti wọn fẹ gba lọdun 2018. Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú",0,yoruba ẹ̀ ẹ́ gbayì ní,0,yoruba ènìyàn a yi yi ti o nuni ti o ní wúlò.,0,yoruba pataki. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọba lo fi.,0,yoruba "Oyinkansola lo fi ọrọ naa lede ninu ifọrọwerọ kan pẹlu BBC Yoruba. Gẹgẹ bo ṣe ṣọ, awọn janduku kan ṣaa ni ada lọpọ igba, ṣugbọn ada naa ko wọle si lara. Wo ohun tí Professor Peller wí tó kó bá a gẹ́gẹ́ bí ìyàwó rẹ̀, Lady Peller ṣe tú u síta Ṣaaju ni Oyinkansola ti kọkọ sọ ninu ifọrọwerọ naa pe ilẹ Amẹrika ni oun fi ṣebugbe bayii nitori awọn iṣẹlẹ to kan ṣẹlẹ si i nilu u Ibadan lọdun 2019. Iṣẹlẹ naa jẹ eyii to gbomi loju Oyinkansọla, koda, bintin bayii lo ku ki omi bọ loju rẹ lasikọ to n ṣalaye ọrọ naa fun BBC Yoruba. Sunday Igboho latest: Sunday Igboho kò gba 'Award'ti a fún un ní Ogo Yorùbá nítorí inú rẹ̀ Oyinkansola ni ""Alẹ ọjọ kan lẹyin ti mo ti ode ere de ni awọn kan wa da emi atawọn ọmọ to n gbe pẹlu mi mọle, wọn gba owo ati awọn nnkan miran lọwọ wa."" ""Ṣugbọn nigba to ya, wọn ni ki n wọle sinu yara, mo si ṣe bẹẹ, lẹyin ti wọn ko awọn ẹgba ọrun tan ni wọn ba ni ki n dubulẹ sori ibusun ti mo si kọ."" Ninu alaye rẹ, o sọ siwaju si pe ""Lẹyin ti mo bọ lọwọ wọn tan ninu ile ni mo ba ni ki n jade lẹnu ilẹkun nla to wọ inu ile ni mo to ranti pe mo ti ti ilẹkun naa pa."" ""Bi awọn eeyan yii ṣe jade simi niyẹn ti wọn si bẹrẹ si n ṣa mi ladaa, ṣugbọn ko wọle, o kan fi apa diẹ simi lara ni."" O ṣalaye pe ""ọpẹlọpẹ 'science' ni ko jẹ ki ada naa wọle simi lara, n o ba ti gba ibẹ lọ."" Ṣugbọn nigba ti atọkun BBC Yoruba bere pe ki lo n jẹ ""science"" ti Oyinkansola n sọ, lo ṣi aṣọ loju eegun pe oogun abẹnu gọngọ ni oun n poe ni 'science.' Yatọ si eyii, Oyinkansola tun sọrọ nipa bi ere ori itage ṣe jẹ ajogun ba fun oun, ati bi ko ṣe ti oun loju lati jẹ onigabgbọ ninu ẹsin adayeba ilẹ Yoruba, paapaa Ifa Olokun asọrọ dayọ. #EndSars Ogbomoso: Èmí kò ní kí wọ́n pa ọlọ́pàá tó pa Isisaka, ṣùgbọ́n...- Ramota, Iya Isi Oyinkansola sọ pe lara afojusun oun fun ọjọ iwaju ni pe yoo wu oun lati gbe aṣa Yoruna ga ju bo ṣe wa lasiko yii lọ. Nipa ibasẹpọ to wa laarin oun ati oṣere tiata kan ti irawọ rẹ n tan lọwọ yii, ti awọn kan sọ pe awọn mejeji ni ibasẹpọ, ati pe gbajumọ oṣere naa lo gbe lọ silẹ Amẹrika, Oyinkansola sọ pe ko si ohun to jọ bẹẹ rara. Francis Olusola Alao: Wọ́n ti ti ọ̀rọ̀ òṣèlú bọ ọ̀rs Sunday Igboho, ṣùgbọ́n..- Oba Olugbọn",0,yoruba "Àt'ẹni k'àwé, àt'ẹni kò kà t'ó bá ti jẹ́ ọ̀ṣọ́rọ́, ó yẹ kí I.T.F ràn án lọ́wọ́ """""""" #OhunOdoNigeriaKan",0,yoruba "Iṣẹ́ bọ́ lọ́wa ọ̀gá ilé iṣẹ́ tó bẹ́nu àtk lu Obinrin Pillay nínú akọtọ kan tó kọ ní ọ̀pọ̀ àwọn obìnrin yan iṣẹ́ kan láàyò kòṣèyìn pé ìtòjú ọmọ àti ilé ní ojúṣe wọn. 'Obinrin jẹ amuludun' O ní àwọn obìnrin máà ń yàn láti tọ ọmọ ju kí wọn yan iṣẹ̀ kan láàyo lọ Bótilẹ̀ jẹ́ pé Manglin Pillay tọrọ àforijì sùgbọn ẹgbẹ́ SAICE sọ pé àwọn ti yọ̀nda rẹ̀ lẹ́nu iṣẹ́ nítori ìhà tí àwọn ọmọ ẹgbẹ́ kọ ọ̀rọ̀ náà. Ìdá márùn-ún nínú àwọn ọmọ ẹgbẹ́ SAICE tó tó ẹgbẹ̀rùn mẹ́fà ló jẹ́ obìnrin Àjọ tó ń sègbè fábo ní orílẹ̀-èdè South Africa náà ní àwọn fọ́wọ́ sí ìgbése ẹgbẹ́ náà Aarẹ Cyril Ramaphosa s'adehun igba ọtun fun South Africa Cyril Ramaphosa, ẹni ọdun 65, jẹ okan lara awọn oselu ti wọn ni owo ju ni orilẹede South Africa Aarẹ orilẹede South African tuntun, Cyril Ramaphosa, ti s'ọrọ nipa ""igba ọtun"" ninu ọrọ rẹ akọkọ nipa bi orilẹede naa ti wa ni ile igbimọ asofin orilẹede naa. Ọgbẹni Ramaphosa, ti wọn bura fun ni ọjọbọ, se adehun ati gb'ogun ti iwa ibajẹ. O si tun s'ọrọ nipa kikan titun ilẹ pin l'oju, pẹlu sise apejuwe bi yoo ti mu idagba s'oke ba oro aje orilẹede naa ati bi yoo ti pese ise. Assaju rẹ ni ipo aarẹ, Jacob Zuma, fi ipo silẹ ni ọjọru lẹyin igba ti ẹgbẹ ANC ton s'akoso orilẹede naa ko ni papa mọra.",0,yoruba "ÀWỌN OHUN ÀMÚSỌ NÍPA ṢÀǸGÓ (2): Ṣàǹgó lọ jà gba ẹ̀gbọ́n rẹ̀, Àjàká sílẹ̀ nígbà tí àwọn ọmọ ogun Òwu mu, lábẹ́ àṣẹ Ọba Òwu. Orógbó ni Ṣàǹgó ma ń jẹ Ṣàǹgó ma ń mú Oṣé lọ́wọ́. Ó ma ń ṣíwájú àwọn ọmọ ogun rẹ̀ lọ sójú ogun.",0,yoruba Èkó yii nípa ọ̀rọ̀ ìlú ni nfàn ojú kakaaki. Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "Àkọ́kọ́, Ọmọ joko lòdì Ìjẹ̀. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé.. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..",0,yoruba o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde lẹ̀ẹ̀ní.,0,yoruba "A gbọ pe meji lara awọn 'ẹlẹ daddy' ọhun, Olori Damilola ati Olori Anu, lo sa kuro ni aafin Oyo. Ohun ti iroyin naa sọ ni pe Olori Damilola, to jẹ iyawo kekere, lo tapa si ọkan lara awọn ofin to de ihuwasi wọn ni aafin, eyi to mu ki wọn o ti i mọ yara ibawi to wa ninu aafin Oyo. Ko tan sibẹ o, iroyin naa sọ pe fun bi ọsẹ kan ni Olori Damilola, to bi ibeji fun alaafin, fi wa ninu ẹwọn naa, to si jẹ pe gbogbo dukia rẹ ni wọn gba lọwọ rẹ. Ko si aworan ikini ku ayẹyẹ ọjọ ibi fun Alaafin loju opo Instagram Olori Anu, amọ o wa ni oju opo ti Dami Bakan naa ni iroyin sọ pe, lọgan ti wọn fun ni ominira, lo sa kuro ni aafin pẹlu akẹẹgbẹ rẹ, Olori anu, ti wọn si sa lọ si ipinlẹ Eko. Koda, iroyin sọ pe aarin oru ni wọn fi sa kuro nilu Oyo lọ si Eko. Lootọ ni BBC Yoruba ko ti i le sọ pato otitọ to wa ninu iroyin yii, amọ awọn akiyesi kan ti a ri lori ayelujara Instagram Olori Anu re e: Iyatọ to ba oju opo Instagram olori Anu lẹyin iroyin pe o kọ Alaafin: Idahun Olori Anu fun BBC Yoruba lati mọ boya o si wa laafin Oyo abi o ti kuro: Awọn arigbamu yii lo mu ki BBC Yoruba kan si Olori Anu lori ẹrọ ibanisọrọ rẹ, lati fi idi ootọ ọrọ nipa iroyin yii to n lọ lori ayelujara mulẹ, lati mọ boya o si wa ni aafin Oyo abi o ti kuro. Nigba to n dahun ibeere wa lori aago, Olori Anu sọ pe ọrọ igbesi aye oun ni, ati pe oun ko ni ohunkohun sọ nipa iroyin naa. O ni ""ọrọ igbeyawo mi pẹlu Alaafin ni, ko kan ẹnikẹni, ọrọ ara mi ni."" Bẹẹ ba si gbagbe, BBC Yoruba ti se ifọrọwanilẹnuwo ri fun Olori Anu, ẹni to yonbo Ọba Adeyemi pupọ, to si ni o n kẹ oun loju-nimu, eyi ti ọdọkunrin miran ko le se. O ni ifẹ nla lo wa laarin oun ati Ọba naa, ti oun ko si kabamọ rara pe oun fẹ Alaafin, tii se ẹni ọdun mejilelọgọrin ni ọkọ. Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo Ni ti Olori Dami, a ko ṣakiyesi ayipada kankan loju opo Instagram rẹ. Oṣu Kẹjọ, ọdun 2020 ni iroyin nipa igbeyawo rẹ pẹlu Alaafin jade sita, bo tilẹ jẹ pe o ti n gbe ni aafin tipẹ, to si ti bi ọmọkunrin kan fun baba. Olori akọkọ to kuro ni aafin Oyo lọdun 2020: Ṣe ẹ o gbagbe pe ninu ọdun 2020 yii kan naa, ni iroyin sọ pe, wọn ti le ọkan lara awọn olori alaafin to gbajumọ julọ lori ayelujara, Olori Badirat, kuro ni aafin. Ẹsun ti iroyin sọ pe wọn fi kan nigba naa ni pe, o n ni ifẹ ikọkọ pẹlu gbaju-gbaja olorin Fuji, Wasiu Ayinde, K1. Bo tilẹ jẹ pe Badirat tabi aafin ilu Ọyọ ko fi idi iroyin naa mulẹ titi di asiko yii, awọn akiyesi kan nipa nkan ti Badirat n fi sori ayelujara Instagram rẹ n fihan pe, o ṣe e ṣe ko jẹ ootọ ni iroyin naa. Bakan naa lo fi oju han pe ilu Eko ni Olori Badra n gbe bayii, to si ti si ile itaja nla kan si adugbo Ikeja nilu Eko eyi to si losu kẹwaa ọdun 2020. Ninu ile itaja naa lo ti n ta aṣọ, ati ohun ẹsọ iṣaraloge, to si tun sọ lọjọ ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ to kọja pe, awọn nkan to ṣẹlẹ si oun lọdun 2020 ba oun lọkan jẹ, to si jẹ ki oun mọ pe ohun gbogbo to n dan kọ ni wura.",0,yoruba Iṣọ́ẹ̀ ìṣẹ́ ni ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi.,0,yoruba "NADECO tún pè fún ìdápada ètò ìjọba awa ara wá nítori pe ètò ìjọba to ń lọ lọ́wa yìí jẹ ti ìjọba ọlọgún, èyí ti ó gbé àgbára fún ìjọba àpapọ̀. Sáájú àsìkò yìí ni gbogbo ìhà Iwọ-òòrun -Guusu Nàíjíríà ti rí June 12 gẹ́gẹ́ bíì ayájọ ọjọ ìjọba àwa arawa, tí wọn si n ṣe ajọyọ rẹ̀. Sùgbọ́n lẹ́yìn ọ̀pọ̀lọpọ atótónú láti ọdọ àwọn ọmọ Nàìjíríà, ààrẹ Muhammadu Buhari, lọdun tó kọja kéde pé Nàìjíríà yóò ma ya June 12 sọ́tọ̀, láti fi ṣe àyájọ ọjọ ìjọba àwa ara wa, bákan náà ni ile ìgbìmọ aṣofin jan abádofin náà lóntẹ. Ààrẹ Buhari tún fún Abiola ati ẹbi rẹ̀ ni àmi ẹ̀yẹ ní Abuja, tí ìjọba tún tọrọ àforíjìn lọ́wọ́ ẹbí Abiọla lórí ìjájkulẹ̀ June 12. Kí ni ìdí ti June 12 fi ṣe pàtàkì sí ẹkùn Iwọ-òòrun Guusu Nàíjíríà: Ní ọjọ́ Kejila oṣù Kẹfa ọdun 1993, ní ẹ̀yá Yoruba gbà pé, ìjọba awa ara wa wọle tọ wa ni Naijiria, lẹ́yìn ìdìbò ti wọ́n gbàgbọ́ pé kò ni ẹja ń bakan, nínú ìtàn orílẹ̀ ede Nàìjíríà. Moshood Kashimawo Abiola jáde láti di ààrẹ orilẹ̀-èdè Naijírìa, ti Bahir Tofa náà si ta ko o latinu ẹgbẹ oselu miran, Abiola ri ìbò tó pọ láti ìhà Arewa, bákan náà ní wọn dibo fun ni iha Iwọ-òòrun Guusu nítori pe ó jẹ Yoruba. Eyìn o rẹyin, Abiola ti léwáju ninu ìdìbò náà ní ìpínlẹ̀ Mọ́kandínlógun nígbà ti Tofa bori ibo ní ìpínlẹ̀ mọkanla, Sùgbọ́n ààrẹ ológun nigbà náà, Ọ̀gágun Ibrahim Babangida wọgile ìdìbò náà, kí wọn to ka èsì ìdìbò naa tan. June 12 declaration: Àjọ eléto ìdìbò gbọdọ̀ kéde MKO Abiola bí ààrẹ Nigeria Lẹ́yìn èyí, ní wọ́n mu Abiola si atimọle tí ọ̀pọ̀ ọmọ Nàìjíríà sì gba ìgboro láti fẹ̀honu han ní ìpínlẹ̀ Eko àti Abuja pé kí wọ́n fi Abiola silẹ̀ lẹ́wọ̀n nítori pé wọ́n ni ìgbàgbọ pé òun ló jáwe olúbori nínú ìdìbò náà. Ní ọ̀jọ̀ keje oṣù keje ọdún 1998 tí ó yẹ ki Abiola jáde kúrò lẹ́wọn ni òkìkí ikú rẹ̀ kan, èyí tún fa ìfẹhonu hàn míràn. Láti ìgbà yìí ní àwọn ènìyàn ti ya June 12 sọ́tọ̀ láti máa'fi ṣe àyájọ ìjọba àwa ara wa. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ó dàbi ẹni pé ìgbésẹ̀ ààrẹ Buhari kò ti tó, Kini NADECO tún fẹ? Nígbà ti BBC Yoruba bá àkọ̀wé gbogbo-gboo fún àgbájọpọ̀ ẹgbẹ́ àwọn to ń ja fun ìjọba awa ara wa (NADECO), Ayo Opadoku nsọ̀rọ̀, o sàlàyé pé, ìgbẹ́ṣẹ̀ ààrẹ ko tíì kún ojú òṣùwọ̀n to ǹkan ti àwọn ń fẹ. Ayo Ọpadokun ni, ó ti pẹ́ ti àwọ́n ti ń bèèrè fun JUne 12 gẹ́gẹ́ bi àyájọ ọjọ́ ìjọba awa ara wa, nítori pe ọjọ náà ni gbogbo Nàìjíríà gbà pé ìdìbò àwọn ló gbé Abiola wọle. O ní ìjọba olọgun ló de, to ba gbogbo ètò ìṣèjọba Nàìjíríà jẹ́ gẹ́gẹ́ bi ìlàna ìwé ofin, nítori pe ẹyàmẹya ló pa Nàìjíríà pọ, kìí ṣe ẹ̀yà kan náà. Kò yẹ ki ìjọba àpàpọ lágbára lóri ìjọbá ìpínlẹ̀ nígbà ti wọn dé, èyí si ni ó gba àgbà lọ́wọ́ àwọn gómìnà ìpínlẹ̀, àti pé ìjọba kò ti ṣe òun ti ó tọ, ti wọ̀n ò bá pàdà sí ìgbà ti àwọn gómìnà ìpínlẹ̀ ba ní akoso ohun to tọ si wọn, láti fí mú ìdàgbàsóke bá ìpínlẹ̀ wọ́n láì kọ́kọ́ lọ si Abuja. Nǹkan ti NADECO ń bèèrè fún:",0,yoruba "Minisita feto idajọ to tun jẹ agbẹjọro agba fun ijọba Naijiria, Abubakar Malami ti darapọ mọ awọn ti yoo dije dupo gomina nipinlẹ̀ Kebbi. Malami ni oun tẹwọ gba ipe awọn eeyan ipinlẹ̀ naa lati dije fun ipo ọhun. Abẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu APC ni Malami ti fẹ dije. Ninu ọrọ to sọ nilu Birnin Kebbi lasiko ifọrọwerọ pẹlu awọn alẹnulọrọ lẹgbẹ oṣelu APC nipinlẹ̀ Kebbi, Amofin Malami sọ pe, ""Niwọn igba ti ẹ fẹ ki n dije dupo gomina ipinlẹ yii, mo gba ipe yin nitori pe ohun ti ẹ fẹ niyi."" O niọkan o jọkan awọn eeyan ipinlẹ naa ni wọn ti n kan si oun niwa lẹyin pe ki oun dije fun ipo gomina ipinlẹ̀ Kebbi lọdun 2023. Ọpọlọpọ igba lawọn iroyin kan ti n ru jade pe minisita feto idajọ ni Naijiria naa n gbero lati di aarẹ tabi igbakeji pẹlu ipo gomina. Jijade rẹ lati fifẹ han fun ipo gomina ti fopin si awọn iroyin wọnyii.",0,yoruba "fè mú, Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó.",0,yoruba Ṣí táàbù tuntun,0,yoruba àti àsà tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé.,0,yoruba "Akeredolu lo fi ọrọ naa lede ninu ifọrọwerọ kan pẹlu BBC Yoruba. O ni ""Adupẹ fun aṣeyọri ti a ri ninu idibo abẹlẹ ti a ṣe kọja, ṣugbọn oun to wa niwaju wa ṣi ju iṣẹgun ti a ti ni sẹyin lọ."" Gomina ọhun ṣalaye pe ifọwọsowọpọ nikan lo lee mu itẹsiwaju ba ẹgbẹ oṣelu APC ati ipinlẹ Ondo, nitori naa ni o ṣe gbe igbesẹ ọhun, ki alaafia lee jọba. Ni bayii, Akeredolu ti lọ ṣabẹwo si awọn ti wọn jọ dije ninu idibo abẹle naa, lara awọn ni Olusola Oke, Salo Iji ati D.I Kekemeke. Akeredolu lo jawe olubori ninu abẹle to waye ninu ẹgbẹ oṣelu APC lati yan oludije sipo gomina ninu idibo ti yoo waye loṣu kẹwaa ọdun 2020. Ṣaaju idibo abẹle naa ni oriṣiriṣi nnkan ti n ṣelẹ ninu iṣejọba Akeredolu, akọkọ ni pe igabkeji rẹ, Agboola Ajayi fi ẹgbẹ APC silẹ, to si lọ darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu PDP. Ko pẹ si asikọ ọhun ni akọwe ojọba rẹ, Ifedayo Abegunde naa kọ ẹyin si Akeredolu. Olusola Oke ní ìfẹnukò àwọn alátìlẹ́yìn òun ni yóò sọ ìgbésẹ̀ tó kàn lẹ́yìn ìdìbò abẹ́nú APC l'Ondo Olusola Oke ní ìfẹnukò àwọn alátìlẹ́yìn òun ni yóò sọ ìgbésẹ̀ tó kàn lẹ́yìn ìdìbò abẹ́nú APC l'Ondo Lootọ lawọn aidọgba pọ nipa eto idibo abẹle APC to waye lana nipinlẹ Ondo, ṣugbọn n o tii le sọ igbesẹ to kan fun mi bayii- Olusola Oke. Amofin Oluṣọla Oke to jẹ ọkan lara awọn oludije nibi idibo naa lo sọ eyi fun BBC News Yoruba. O ni oun yoo ṣepade pẹlawọn alatilẹyin ohun lati mọ ibi ti awọn yoo gbe ka. Amofin Oke ni ṣaaju eto idibo naa loun ti pariwo sita pe o ni kudiẹkudiẹ ninu eleyi ti ẹnikẹni ko fi lee tọka si ọrọ oun gẹgẹ bii ẹni to n ṣawawi nigba ti oun fidirẹmi. Ṣé lootọ ni àwọn Agba ẹgbẹ ṣe atilẹyin fún oludije kan? Lori boya awọn agbaagba ẹgbẹ naa ṣe atilẹyin fun ọkan ninu awọn oludije naa, amofin Oke sọrọ ni kikun. O ṣalaye wi pe ni ti oun o, ko si ifarahan awọn agbaagba ẹgbẹ kọkan ni ilu Akurẹ lọjọ ti idibo naa waye. Awọn aṣoju ẹgbẹ ni ipinlẹ Ondo lo dibo yan ẹni to wọle, nitori naa gẹgẹ bi ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC tootọ, ko si idi fun oun lati sọ pe bẹẹni tabi bẹẹkọ lọwọ yii. Gomina Akeredolu ni wọn kede gẹgẹ bii olubori ibo abẹnu lati mọ ẹni ti yii gbe aṣia ẹgbẹ oṣelu APC ni idibo gomina ipinlẹ Ondo to n bọ lọna ti amofin Oluṣọla Oke si gbe ipo keji. Olofa ina: ẹ parí òwe yìí pé ìgbà tí ara bá tu ìgbẹ́ láà ri eṣú.... Lẹ́yìn gbogbo sinimá oríta ní Ondo, Akẹti jáwé olúborí ní APC Èsi idibo lati yan ẹni ti yoo dije du ipo gomina fun ipinlẹ Ondo labẹ ẹgbẹ oṣelu APC ti jade. Aketi lo gebgba oroke ju. Lẹyin gbogbo sinima orita awoo wo tan to ti ṣẹlẹ sẹyin ni ipinlẹ Ondo, Gomina Rotimi Akeredolu to ti tukọ ipinlẹ naa lọdun mẹrin sẹyin ni o tun ri tikẹẹti gba lẹẹkan sii Mo káàbámọ̀ pé mo yan Ajayi gẹ́gẹ́ bíi igbákejì mi- Akeredolu . Bayii ni esi idibo naa ṣe lọ: Ibrahim Olusegun Michael PHD........ 0Adelami Olayide Owolabi MNI.......4Adetula olubukola Olarogba Okunola.....0Adejutelegan Nathaniel Olumuyiwa DR......4Akeredolu Oluwarotimi Odunayo SAN..........2458Anifowoshe Olajumoke Olubusola......2Awodeyi Akinsheyinwa Akinola Colinus......1Iji Olusola Joseph...... 9Kekemeke Duerimini Issac.....19Odimayo Okunjimi John......0Oke Olusola Alex SAN......262Oyedele Ifeoluwa Olusola.....1 Bawo ni Idibo APC Ondo ṣe lọ? Ètò ìdìbò abẹ́lé sípò gómìnà APC ni ipinlẹ Ondo ti bẹ̀rẹ̀ ní pẹrẹwu Eto idibo abẹle lati mọ ẹni ti yoo gbe apoti ibo sipo gomina ninu ẹgbẹ oṣelu APC ni ipinlẹ Ondo bẹrẹ ni pẹrẹwu. Bi wọn ṣe n yẹ kaadi idibo awọn olukopa ninu idibo abẹle ọhun wo naa ni wọn n dibo lẹsẹkẹsẹ. O kere tan, ẹgbẹrun mẹta awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC lati ẹkun idibo mẹtalenigba kaakiri ipinlẹ Ondo lop n kopa ninu idibo abẹle naa lati yan ẹni ti yoo gbe apoti ibo sipo gomina ni ipinlẹ Ondo. Ṣaaju ni mẹta lara awọn to n ba gomina Rotimi Akeredolu dije ti kọkọ sọ pe wọn ko ṣe mọ. Awọn eeyan naa ni Segun Abraham, Ife Oyedele ati Jimi Odimayo. Ẹwẹ, iroyin ti kọkọ gbode pe ọkan lara awọn oludije ọhun, Nathaniel Adojutelegan ti yọwọ lawo lati dije ninu idibo abẹle naa, ṣugbọn o sọ fun BBC pe irọ pọmbele ni. Lockdown updates: Naira Marley gbóríyìn fún Jude Chukwuka pẹ̀lú #1 míliọnù Ki lo ti ṣelẹ sẹyin? Àwọn olùdíje meji míràn tún ti jọ̀wọ́ àgá fún Akeredolu níbi ètò ìdìbò abẹ́lé APC ìpínlẹ̀ Ondo Ni kete to ku wakati diẹ ki eto idibo abẹle lati mọ ẹni ti yoo gbe apoti ibo sipo gomina ninu ẹgbẹ oṣelu APC ni ipinlẹ Ondo bẹrẹ, oludije meji miran tun ti yọnda aga fun gomina Rotimi Akeredolu. Akeredolu lo fi ọrọ naa ledeloju opo Twitter rẹ lẹyin ti ileeṣẹ iroyin abẹlẹ kan kede rẹ. Awọn oludije ọhun ni Ife Oyedele, Jimi Odimayo. Ṣaaju ni Akeredolu ti kede loju opo Twitter rẹ kan naa pe ọkan gboogi lara awọn to n ba du ipo gomina ninu ẹgbẹ oṣẹlu naa, Olusegun Abraham ti yọwọ rẹ kuro lawo idibo ọhun. Igbesẹ tuntun yii ti mu ki iye awọn to n ba gomina Akeredolu figa-gbaga ninu idibo abẹle naa, ṣugbọn ti wọn jawọ di mẹrin. O le lẹgbẹrun mẹta awọn ọmọ oṣelu APC lati ẹkun idibo mẹtalenigba kaakiri ipinlẹ Ondo ti yoo kopa ninu idibo naa lati yan ẹni ti yoo gbe apoti ibo sipo gomina ni ipinlẹ Ondo. Ọjọ kẹwaa, oṣu kẹwaa, ọdun 2020 ni idibo sipo gomina ọhun yoo waye. Ǹjẹ o yẹ kí èèyàn máa sùn lẹ́nu iṣẹ́? Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Laycon, akẹ́kọ̀ọ́jáde UNILAG tó ń kópa nínú BBNaija 2020 Àwọn àádọ́ta ọ̀dọ́ wọ gàù nítorí ilé ijó ní Ilorin Ondo APC primaries: Olùdíje míràn, Olusegun Abraham tún ti gbé àgá fún Akeredolu níbi ètò ìdìbò abẹ́lé APC ìpínlẹ̀ Ondo Bi awọn aṣoju oludibo lẹgbẹ oṣelu APC ṣe n gbaradi lati yan oludije ẹgbẹ oṣelu naa fun ibo gomina to n bọ lọna, oludije miran tun ti dide lori aga fun gomina Rotimi Akeredolu. Gomina Akeredolu ṣalaye loju opo Twitter rẹ pe Oluṣẹgun Abraham to jẹ okan lara awọn oludije mẹwaa to n ba a ta kangọn ti gba lati ti oun lẹyin. ""Mo ṣẹṣẹ ba ọmọ iya mi, Oluṣẹgun Abraham sọrọ tan lori foonu ni, o si ti jẹ ko di mimọ fun mi peoun ṣetan lati fọwọ si idije mi nigba keji. Ni ifọwọsowọpọ la o js mu ki oorun ipinlẹ Ondo o tubọ maa tan sii."" Ni bi a ṣe n sọrọ yii, eto ti n lọ ni pẹrẹ lawọn ibudo idibo abẹle lẹgbẹ oṣelu APC ni ilu Akurẹ. Akọroyin BBC News Yoruba to wa nibi idibo naa ṣalaye pe awọn aṣoju ọmọẹgbẹ gbogbo to fẹ dibo ni wọn ti wa nikalẹ ti wọn si n reti ki eto naa bẹrẹ. Ni Gbongan The Dome, awọn apoti idibo gbogbo ti wa ni ato ni isọri ijọba ibilẹ kọọkan. Bakan naa lawọn agbofinro naa wa ni sẹpẹsẹpẹ lati rii pe ẹkọ ṣoju mimu lori abo ẹmi ati dukia nibẹ. Wo bí ètò ìdìbò abẹ́lé APC yóò ṣe lọ ní ìpínlẹ̀ Ondo lónìí Loni ni ireti wa pe awọn aṣoju oludibo lẹgbẹ oṣelu APC nipinlẹ Ondo yoo gbe ipinnu wọn kalẹ lori ẹni gan an ti wọn fẹ ko gbe aṣia ẹgbẹ oṣelu naa ninu eto idibo sipo gomina to n bọ lọna. Kii ṣe ahesọ ọrọ mọ pe oniruuru awuyewuye lo ti wọ tọ ọrọ tani yoo dije ipo gomina ni ipinlẹ Ondo. Awọn oludije mọkanla lo n dije fun aṣia ẹgbẹ oṣelu APC naa bayii lẹyin ti iroyin abẹle sọ pe Ifẹ Oyedele, ọkan lara awọn oludije naa to fi pe mejila tẹlẹ ti gba lati jawọ. Ifẹ Oyedele ni oun gbe igbesẹ naa lati lee ṣe atilẹyin fun gomina Rotimi Akeredolu. Oyedele kede atilẹyin rẹ fun Akeredolu lẹyin ifikunlukun pẹlu gomina Akeredolu nileejọba ipinlẹ Ondo ni alẹ ọjọ Aiku. Gomina Yahaya Bello ni alaga igbimọ to n ṣe kokari idibo abẹle naa; oun pẹlu si ṣepade pẹlu gbogbo wọn lalẹ ọjọ Aiku kan naa. Awọn ibudo ayẹwo fawọn aṣoju oludibo niwọnyii: Awọn aṣoju lati ẹkun Ariwa Ondo- Gbongan ajọ olomi ẹrọ Water Corporation to wa ni Ijapo Estate, Awọn aṣoju ẹkun Gusu Ondo- Ileewe girama, St Thomas' Aquinas College nilu Akurẹ Awọn aṣoju ẹkun Aringbungbun Ondo- Ileegbimọ aṣofin ipinlẹ Ondo, ODHA Complex ni opopona Igbatoro Akurẹ. Awọn oludije pe fun isunsiwaju idibo abẹle naa Nibayii, iroyin n sọ pe meje ninu awọn oludije naa ni wọn ti n pe fun isunsiwaju idibo abẹnu naa. Amọṣa gomina Yahaya Bello ti ṣalaye pe oun gẹgẹ bi alaga igbimọ ibo abẹle naa ko laṣẹ lati sun un siwaju. Black women live matters: Ọdún 2015 ní àwọn ọlọ́pàá pa India Kager láìní ìdí- Gina Best Yahaya Bello ni: ""A o tẹsiwaju pẹlu idibo abẹle yii. Ko si eto idibo to pe nibiki lagbaye, koda titi de orilẹ-ede Amẹrika pẹlu."" Awọn oludije to n dije fun aṣia ẹgbẹ oṣelu APC lati dupo gomina ipinlẹ Ondo ni Gomina Rotimi Akeredolu, Chief Olusola Oke, Dokita Segun Abraham, Ọgbẹni Olaide Adelami, Ko yọ Bukola Adetula, Arabinrin Jumoke Anifowose, Ambasadọ Sola Iji, Ọgbẹni Isaac Kekemeke, Jimi Odimayo, Ọgbẹni Nathaniel Adojutelegan ati Awodeyi Akinsehinwa naa silẹ. Black women live matters: Ọdún 2015 ní àwọn ọlọ́pàá pa India Kager láìní ìdí- Gina Best",0,yoruba àwọn ènìyàn: ti o nuni ti o gbagbé ti jade pẹ̀lú àwọn alákòó.,0,yoruba "òní.. Nitori eyi, ara eni lo ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.",0,yoruba EKaRo family. Baoni ? #yoruba #wizkidvoice,0,yoruba "Èèwọ ni, a kì í da Ògún, ẹnikẹ́ni t'ó bá da Ògún yóò rí ìjà Oníjà-oòle, a dì gìrìgìrì re 'bi ìjà. #OsuOgun #Yoruba #Irunmole #Isese #culture",0,yoruba eni ti ojo ti a ya si le la ti ma soro nipa aarun jedo jedo lo se ayewo ko de gba ajesara le ni,0,yoruba Ènìyan ti nilo iye fun ìṣẹ́ tabi ìbadandun.,0,yoruba "Arabinrin Bunmi aya Femi Amao lati ile iwe Graceland Heights School ni agbegbe Wọfun, Olodo ni ilu Ibadan ni ipinlẹ Oyo ni olukọ wa fun toni. Ọrọ Ẹyan ni koko girama ti an gbe yẹwo loni. Ẹyan Asapejuwe ni o maa n sọ fun wa sii nipa ọrọ orukọ. Eto Akomolede ati Asa yii n waye lati ọwọ BBC Yoruba pẹlu ajọṣepọ ẹgbẹ Onimọ Yoruba YSAN ati apapọ ẹgbẹ Akomolede Naijiria. Oriṣi ẹyan meje to wa ni olukọ Bunmi Femi Amao kọ wa loni. Eyan Ajorukọ Ẹyan Aṣapejuwe Eyan Asorukọ Eyan Atọka Aṣafihan Eyan Aṣonka Eyan Arọpo Orukọ Eyan Afarajorukọ Eyan Awẹ gbolohun Afarahe Aṣapejuwe.",0,yoruba ṣe ògbufọ̀ gbólóhùn yìí sí èdè yorùbá life is vanity,0,yoruba "fi. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "ti Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "ayé ọ̀ṣun. Nitori eyi, ara eni lo ni ẹ̀ká àwẹ eyti o gbe lori iwa rere.",0,yoruba Kaada fun Osi. 👉 Yorùbátv ẸGBẸ ỌMỌ OLÚWA BÍ GBOGBO ÀGBÁYÉ Ojú òpó ìkànsíraẹni 🇳🇬🇹🇬🇧🇯🇧🇷🇨🇴🇨🇺🇬🇭🇨🇮______________________________□ Yoruba TV 🥰😘🔥 #yoruba #yorubatv #yorubaweddings #ebi #asoebi #nigerianwedding #hausa… https://t.co/r4PmWiv6X4,0,yoruba "fẹ. Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba "Ọ̀gá àjọ náà Olufemi Oke-Osanyintolu sàlàyé pé àwọn ìjàmbá tó ṣẹlẹ̀ níbẹ tí òun sì le sàlàyé lọ́wọ́lọ́wọ́ okú ènìyàn mẹ́jọ ní àwọn ti rí báyìí. Osanyintolu sàlàyé pé, ilé igbé márùnlélógún, àwọn sọ́ọ̀bù mẹ́rìndinlógún àti ilké iwé alákọ̀bẹ̀rl kan wà lára àwọn dúkíà tó ti bá iṣẹ́lẹ̀ náà rìn lọ́wọ́lọ́wọ́ Àwọn ǹkan míran tó tún bàjẹ́ nibẹ̀ ni ilé alájà mẹ́rin tó fi mọ ilé itura kan, ọkọ tó n gbé afẹ́fẹ́ gáàsì, kẹ̀kẹ́ márúwá, ọkọ ẹru kan. Ó fi kun pé, wọ́n ti ri ibi ti afẹ́fẹ́ gáásì ti n jáde wan si ti dii pa, sùgbọ́n ìwádìí àwọn ǹkan míran to báàjẹ́ níbẹ̀. Bákan náà ni ọkọ mẹ́ta jóna nínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà Lagos gas explosion: Iná míì tún ti ṣẹ́yọ ní agbègbè Ipaja lówùrọ òní! Ajọ tó ń rí sí ìṣẹ̀lẹ̀ pàjáwìrì ní ìpínlẹ̀ Eko LASEMA ní òun ti bẹ̀rẹ̀ ètò láti pa iná tó ṣẹyọ nilé epo kan ni Baruwa, àgbègbè ìpájà lówùrọ̀ òní. Bákan náà ni fọ́nran kan jẹyọ lójú òpó twitter níbi ti àwn ará ìlú ti ń pe fún ìrànwọ́ láti pa iná náà. Ondo Elections 2020: Ọgọ́rùn-ún ọdún tí a máa lò lórí oyè l'Ondo, ẹ ó rí àrà - Ojon YPP Gẹ́gẹ́ bí ọgá àgbà LASEMA ṣe sọ, ìná náà bẹ̀rẹ̀ ni dédé ààgo mẹ́fa owúrọ ọjọbọ ọsẹ. LASEMA ni ""ati gbé ìgbésẹ̀, bákan náà ni a ó maa fi tó yín létí bi ó bá ṣe ń lọ"". Bakan naa, ileeṣẹ Ọlọpa ti fi ikede sita pe awọn ti ran ikọ amuṣẹya lọ si oriko iṣẹlẹ naa lọgan. Àwọn kan ṣónú bí wọ́n bá di gómìnà, ẹ fún wa láyè láti wá parí iṣẹ́ táa bẹ̀rẹ̀ - Akeredolu",0,yoruba "RT @user: Ayọ̀,àlááfíà àti ìlera to péye ni Ọlọ́run afi fún wao__ @user @user @user @user @user…",0,yoruba ♪ ọ̀lájú dé la wá gbàgbé àṣà ìdílé wa ♪,0,yoruba "Ó ṣe'ni láàánú, ọ̀pọ̀ t'ó pe ara wọn ní ọ̀mọ̀wé, gbajúmọ̀ àti ọ̀tọ̀kùlú ni ò kọ'bi ara sí ohun abínibí. #OsuItanAtehinwa",0,yoruba "Adari ẹgbẹ ajijagbara Yoruba Nation, Ọjọgbọn Banji Akintoye ti sọ pe ẹṣin aayan lasan ni awọn oloṣelu iha Ariwa Naijiria n gbe Bola Ahmed Tinubu gun lẹyin ti wọn sọ pe awọn ṣe atilẹyin fun lati di Aarẹ Naijiria lọdun to n bọ. Akintoye ni oun gbagbọ pe laipẹ lai jina, awọn oloṣelu naa yoo kọ ẹyin si Tinubu lati ṣalitlẹyin fun ọmọ wọn to jẹ oludije ninu ẹgbẹ oṣelu PDP, Atiku Abubakar. Ọjọgbọn Akintoye lo sọ ọrọ naa ninu ifẹrọwerọ pẹlu ileesẹ iroyin BBC Yoruba ni Benin Republic. O ni lootọ ni pe awọn eeyan kan le ma woye pe o yẹ ki wọn jawọ ninu ọrọ Yoruba Nation lati ṣatilẹyin fun Tinubu nitori o jẹ ọmọ ilẹ Yoruba, amọ ẹtanjẹ lasan ni. Akintoye sọ pe “Awọn kan le maa sọ pe ẹ jẹ ka ṣatilẹyin fun Tinubu nitori ọmọ Yoruba ara wa naa ni... ẹ jẹ ka dan wo boya yoo ṣe daadaa, amọ ti ẹ ba wo finni-finni, wọn kan n tan Tinubu jẹ ni.” “Fun apẹrẹ, awọn eeyan PDP sọ pe awọn ko gbagbo ninu ki a maa pin ipo Aarẹ si ẹlẹkunjẹkun, ṣugbọn ni kete ti Atiku jawe olubori gẹgẹ ẹni ti yoo dije ninu ẹgbẹ PDP ni awọn gomina iha Ariwa ni awọn yoo ṣatilẹyin fun Tinubu.” “Irọ ni o, wọn kan ṣatilẹyi fun Tinubu pẹlu ẹnu lasan ni, Atiku ni wọn maa dibo fun, fun idi eyi, ko tọ ki a pa ilepa wa fun Yoruba Nation ti nitori pe Tinubu fẹ du ipo Aarẹ.” Nipa ibaṣepọ to wa laarin Ọjọgbọn Akintoye ati Bola Tinubu, Akintoye sọ pe bo tilẹ pe oun ati Tinubu kii sọrọ, amọ o da oun mọ. O ni “Mi o ni iṣoro kankan pẹlu Tinubu, aburo lo jẹ si mi, ẹgbọn ni mo si jẹ si pẹlu, amọ ohun to jẹmilogun ni bi Yoruba ṣe maa kuro lara Naijiria, ti igbeaye irọrun yoo si de ba awọn eeyan wa.” “Lootọ, ka ni pe nnkan n lọ bo ṣe yẹ ni, ti wọn si ni ki n lọ  mu ọmọ Yoruba to dantọ lati ṣe Aarẹ wa, mo maa mu Tinubu, amọ lọwọ yii nnkan ko ṣenu ire.” “Wọn n pa awọn eeyan wa nilu Owo nipinlẹ Ondo, wọn n pa wọn ni Ekiti, Igangan, Ibarapa ati bẹẹ bẹẹ lọ, ẹ wa sọ pe ọrọ Aarẹ lo kan, rara o!” Akintoye sọ pe oun ko ni ṣegbe lẹyin ẹgbẹ oṣelu kankan lọdun 2023 ju ki Yoruba Nation da wa nikan. Ni ti ọrọ oloye Sunday Adeyemo Igboho, baba Akitoye ni ijọba orilẹ-ede Benin ti fi Igboho silẹ ko maa ba tirẹ lọ awọn ololufẹ rẹ si gba tirẹ. Gẹgẹ bii ohun to sọ, olori ileeṣẹ ọmọ Naijiria ana, Lt. Gen. Tukur Buratai, gbe owo nlan kan fun Igboho ko le pada lẹyin ijijagbara fun ominira ilẹ Yoruba amọ o kọ lati gba owo naa, bẹẹ si ni ko tọwọ bọwe ọhun. Akintoye ni “Wọn wa gbe owo nla fun ọmọkunrin naa amọ o kọ jalẹ, melo ninu awọn ọdọ aye ode oni lo le kọ irufẹ owo beẹ?” “Tukur Buratai wa ba ninu ẹwọn, o si ṣeleri ẹgbẹlẹgbẹ biliọnu naira fun ti o ba le tọwọ bọwe kan ti Buratai gbe wa pe oun yoo dẹyin lẹyin Yoruba Nation amọ Igboho ni ko jọ.” Ni ti igbiyanju igbakeji Aarẹ Naijiria, Ọjọgbọn Yemi Osinbajo lati dije du ipo Aarẹ ninu ẹgbẹ oṣelu APC, Ọjọgbọn Akintoye ni iyalẹnu lo jẹ fun oun. Gẹgẹ nii ohun to sọ, oun ko dunnu pe Osinbajo padanu ipo naa amọ ko jẹ iyalẹnu pe ko wọle. O ni “Nigba ti wọn n sọ pe awọn ara iha Ariwa wa lẹyin Osinbajo mo kan n rẹrin ni, nitori mo mọ pe Osinbajo ko ni gbongbo bii Tinubu. “Ọkan lara awọn ọlọpọlọ pipe ti a ni ni Naijireia ni Osinbajo ṣugbọn ko ni gbongbo.” Yoruba Nation nikan ni a fẹ Baba Akintoye pari ọrọ rẹ si igba ti yoo pada wa si Naijiria lẹyin to lọ si Benin Republic. O ni “Mo maa pada wa si Naijiria o, amọ kii ṣe lẹyin ti Buhari ba kuro lori alefa.” “Bi mo ṣe wa yi, mi o ni kaadi idibo, nitori mi o fẹ dibi ni Naijiria.” “Mo maa pada wa si Naijiria ti a ba ti gba ominira ilẹ Yoruba.” “Mo le sọ akoko ti yoo ṣẹlẹ amọ mi o tii ni mẹnu lọ sibẹ bayii.”",0,yoruba "jú, àwọn ènìyàn ni ó pa Ọmọ lo tun se joko.",0,yoruba "nípa àìkú. Nitori eyi, ara eni lo ni ìgbà mi owó àkokò, Olùwo ri Nitori eyi, ara eni lo ni ìgbà mi owó àkokò, Ìyá ri Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba "Ajọ naa ni ohun to kan ni lati pada si ile gbimọ asofin apapọ Alukoro ikọ alalaafia lorilẹede Naijiria, arabinrin Millicent Umoru lo sọ eyi di mimọ ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC Yoruba. Lọjọ isẹgun ni Aarẹ Muhammadu Buhari kọ iwe ransẹ sile asofin agba wi pe oun kolee buwọlu abadofin idasilẹ ikọ alalafia Peace Corps ti wọn fi sọwọ si oun. Ajọ naa ni ohun to kan ni lati pada si ile igbimọ asofin apapọ lati mọ boya ọna abayọ wa fun aba ajọ naa. Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Dida abadofin wa sigbo, ko lee di wa lọwọ "" Ohun to han si ita gbangba ni wipe ileesẹ ọlọpaa ko fẹ ki eegun ajọ Peace corps suyọ. A tilẹ gbọ nipa bi ọga agba ileesẹ ọlọpaa lorilẹede Naijiria se bura wi pe gbogbo ipa oun loun yoo sa lati rii pe ajọ naa wọlẹ."" Ikọ alalafia naa ni bio tilẹ jẹ wipe aarẹ ko buwọlu aba idasilẹ rẹ, sibẹ eyi ko di itẹsiwaju ajọ naa lọwọ. ""Idaduro ranpẹ nisẹlẹ yii jẹ fun ajọ yii sugbọn kii se opin irinajo fun wa nitori o ti fi orukọ silẹ pẹlu ileesẹ to n risi eto iforukọsilẹ awọn ileesẹ lorilẹede Naijiria. ""Nitorinaa ko si ibẹru fun awọn ọmọ ajọ yii.""",0,yoruba "Tori eyi ni wọn ṣe ni ki awọn eeyan to ba ni oku sibẹ wa gbe oku mọlẹbi wọn ati awọn ẹni ire wọn to papoda kuro ni mọṣuari ọhun. Lati ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu kejila ọdun 2020 si Ọjọbọ ọsẹ yii ni wọn ti kọkọ fun wọn gẹgẹ bii gbedeke ni awọn alaṣẹ ile iwosan naa ti n pariwo pe ki awọn eeyan wa gbe oku wọn. Nibayii, ọjọ naa ti fẹ ko tan eyi tii ṣe ọjọ kẹrinlelogun oṣu kẹta ọdun 2021 lẹyin eyi ti alaṣẹ ile iwosan naa ni bi awọn eeyan ba kọ, awn yoo ni lati gbe igbesẹ ṣiṣe eto isinku ọlọgọọrọ. Ipe yii tun jẹ jade ninu atẹjade kan ti Arabinrin E.O Ajiboye to jẹ adari eto gbogbo nileewosan naa fi sita lati tun kede fun awọn araalu eyi ti wọn pe akọle rẹ ni ""Ikede isinku ọlọ́gọ̀ọ̀rọ̀"". Omi iké kan, l'èèyàn kan lè mu f'ọ́jọ́ mẹ́ta láì ro ti ekòló inú rẹ̀ - Ìlú Elega, Kwara",0,yoruba "Nípa ti àwọn ọmọ bíbí ibẹ̀ , à á fún wọn ní ohun tí ó tọ́ sí wọn , à á sì dà wọ́n pọ̀ mọ́ àwùjọ .",0,yoruba "ronú lọ́rọ̀.. Nitori eyi, ara eni ni nfàn ojú kakaaki.",0,yoruba "Ìdámọ̀ràn ohun tí ó lè fa sábàbí àrùn náà kan fi yé wí pé kòkòrò àìfojúrí kòrónà jẹ yọ látàrí ẹran ejò tàbí ẹran àdán tí àwọn ará China máa ń jẹ l'óúnjẹ , tí wọ́n ń tà ní ọjà Huanan wet ní agbègbè Wuhan níbi tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ní èrò wí pé ibẹ̀ ni orísun kòkòrò àìfojúrí yìí .",0,yoruba "àkokò, Ìyá ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì lẹ̀.",0,yoruba "Ti a ba n se ayẹyẹ, tọkunrin tobinrin lo maa n peju pesẹ lati fi ara kinra, eyi ti yoo mu ki ayẹyẹ naa dun, ko si larinrin. Sugbọn iyalẹnu gbaa lo jẹ lati ri pe ode ijo kan lee wa, ti yoo wa fun kikida awọn obinrin nikan, ti wọn yoo si le awọn akọ sẹyin. Gẹgẹ bi BBC se se awari rẹ, ilu Nairobi lorilẹede Kenya ni idan orita naa ti n waye, nibiti wọn ti haya ibudo kan to wa fun ile ijo, ti orin si n dun lakọlakọ nibẹ, sugbọn kinni kan to ba Ajao jẹ, ti apa rẹ fi gun ju itan lọ ni pe kikida awọn obinrin lo wa lagbo ijo naa, to n jo pẹlu ara wọn. Gẹgẹ bi awọn obinrin to ba BBC sọrọ ti wi, o dara ni ẹkọọkan bayii lati maa fi ọwọ lile mu awọn ọkunrin, ti awọn obinrin nikan yoo ti da wa laisi awọn ọkunrin nibẹ. Jane, ẹni ọdun mẹrindinlọgbọn, lasiko to n ba BBC sọrọ ni, ""ọkan mi balẹ lati wa si agbo ijo to wa fun obinrin nikan lai lọwọ awọn ọkunrin ninu, mo wa pẹlu ọrẹ mi obinrin, eyi to mu ki inu mi dun lati wa pẹlu ẹni to loye nipa oun."" Nibi agbo ijo naa, se ni ipese abbo to peye wa, iwọnba awọn ọkunrin ti wọn si gba laaye lo wa ja awọn obinrin silẹ, ni kete ti wọn ba si se bẹẹ tan ni wọn yoo jade kuro nibẹ. Koda, awọn eeyan to jẹ agbọti, agbounjẹ, osisẹ eleto aabo, awọn gbogbo elere to n lu awo orin, awọn atọkun eto to fi mọ awọn asọna lo jẹ obinrin, laisi ọkunrin ninu wọn. Ọdun 2018 ni wọn bẹrẹ agbo ijo awọn obinrin nikan naa, ti erongba idasilẹ rẹ si kọja jijẹ igbadun alẹ ọjọ kan. Idi ni pe oju awọn obinrin ri mabo lọdun to kọja naa nitori awọn isẹlẹ hihu iwa ipa si awọn obinrin ati ifipabanilopọ, eyi to mu ki awọn obinrin pinnu lati maa da wa laisi ọkunrin. Yatọ si eyi, agbo ijo aọn obinrin naa ko si fun awọn abo to n fẹ ara wọn, taa mọ si Lesbian, ti ode naa ko si wa fun ẹlẹsin kan pato. Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC, Munira, ẹni ọdun mejilelogun ati Khadija, ẹni ọdun mẹẹdọgbọn, ti wọn jẹ mususlumi salaye pe ode ijo naa ba ilana ẹsin Islam mu, eyi to faramọ ki awọn ọkunrin maa da wa loju kan. ""Ọpọ wa lo maa n bọ asọ ibori (Hijab) wa lati darapọ mọ awọn akẹẹgbẹ wa lasiko ta ba n jo. Idi ni pe ti wọn ba ri wa pẹlu Hijab, wọn yoo ya ẹnu pe ki la wa se nibẹ."" Iru ipejọpọ bayii ni Munira lo dara pupọ nitori wọn ko fi aaye gba awọn lati maa fara ro ọkunrin. Ireti si wa pe laipẹ laijinna, irufẹ ode ijo bayii yoo tan kalẹ bii ọwara ojo yika gbogbo ilẹ Afirika, nibiti wọn yoo ti maa gbe awọn obinrin larugẹ bo se yẹ.",0,yoruba Àkóbì níjó òní nípa abọ́jú irúngbọ lo je ti ibile.,0,yoruba nilo ayẹwo wey ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba "Fún ẹni tí kò bá mọ̀, ewì alohùn tí a tún ń pè ní ẹ̀ṣà ni ọ̀rọ̀ ẹnu egúngún tí a máa fi ń yí ohùn padà, láti mú ohùn dún bíi ti ẹbọra; ohùn ará ọ̀run. #Yoruba",0,yoruba "À rí ìgbọdọ̀ wí, baálé ilé sú 'ápẹ. #EsinOro🐎 #Yoruba https://t.co/anobpLUBqi",0,yoruba oju awa naa ti wa lona,0,yoruba "#TweetinYoruba E' ba mi gbe jesu yii gaa, Ehn a Ehn🎶",0,yoruba @user Irú alágbéká wo lẹ nlò? iPhone fúni lánfàní àti f'àmì sọ́rọ̀. Nípasẹ̀ ilé iṣẹ́ asọ̀rọ̀mágbèsì ti Abẹ́òkúta tó pèsè rẹ̀ fúnwa,0,yoruba pa ìró fáwẹ̀lì ọ̀rọ̀ wọ̀nyí jẹ kí o ṣẹ̀dá ọ̀rọ̀ mìíràn ìwòrìwò kọ́kọ́ àti ọ̀páogun,0,yoruba "lojiji. Ọmọ lo ni ìgbà mi owó àkokò, Alàji lo ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa aráyé: ti o nuni ti o nuni ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba ni ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba "Kidude , Zanzibar ni ilé èyí - ò - jọ̀yìí orin tí ó ti inúu ìbàṣepapọ̀ àṣà àti àjọṣe ọlọ́dún gbọgbọrọ tí ó wà láàárín àwọn àdúgbò ẹ̀ka Swahili .",0,yoruba "Cosmic Crisp apple: kò le bàjé nínú ẹ̀rọ amóhun tutù fún ọdún kan Apple náà si le wà nínú ẹ̀rọ amòmítutu fún ọdún kan gbáko ti kò ni bàjẹ, yóò si wọ ilẹ̀ Amerika loníì. Cosmic Crisp apple: kò le bàjé nínú ẹ̀rọ amúǹkan tutù fún ọdún kan Apple tuntun ọ̀hún ni wọ́n n pè ni Cosmic Crisp, èyí ti wọ́n fi àdàpọ oyin àti òwò ṣe, pẹ̀lú fasiti Washington ni wọ́n ti bẹ̀rẹ̀ si ni gbìn láti ọdun 1997 Àfilọ́lẹ̀ èso ẹlẹ́rindòddò yi gba mílíọnù mẹ́wàá dọ́là. (£7.9m) Ní àsìkò yìí, àwọn àgbẹ̀ láti Washington nìkan lo ní ànfàni lati gbìn èso náà títí dí ọdún mẹ́wàá si àsìkò yìí. Kate Evans tó wà lárá awọn to dari ọ̀gbìn Cosmic Crisp Apple ní olu ilu orilẹ-ede America sàlàyé pé ""Crisp apple le koko, o ni ọdiwọ̀n àdun àti ilera, bẹ́ẹ̀ lo ni omí dáradára"" Ogun Cholera: Ọdọọdún ni àrùn onígbá-méjì máa n ṣọṣẹ́ ní Nàìjíríà-NCDC Kate fí kún un pé ara apple náà kìí tètè bàjẹ bákan náà ni gbogbo èròjà rẹ yóò pé si lára ti o ba wà nínú ẹ̀rọ amómitutu fún oṣù mẹwàá sí méjìlá. Cosmic Crisp apple: kò le bàjé nínú ẹ̀rọ amúǹkan tutù fún ọdún kan Igi Cosmic Crisp Apple mílíọnu méjilá ni wọ́n ti gbìn ti iwé àṣẹ̀ rẹ̀ si wà fún àwọn níkan, kò si fi ààyè gba ẹlòmíràn láti gbìn ní apá ibi kankan lọ́rílẹ̀-èdè Amerika. Washington ló ni ibi ti o tóbi jùlọ ti wọ́n ti n pèsè Apple ni Amẹrika lóniruuru, sùgbọ́n àwọn èyí ti wọ́n ń pè ni Golden Delicious àti Red Delicious ti n ri ìpèníjà pẹ̀lú Pink Lady àti Royal Gala. Apple ni èso tó n tà julọ lẹ́yìn ọgẹdẹ ní orílẹ̀-èdè Amẹrika. FUTA: Àwọn mẹ́jọ ló ṣíná ìyà fún Bolu ní FUTA",0,yoruba "Pasitọ Biodun Fatoyinbo àti Busola Dakolo Agbẹjọrọ Pelumi Olajengbesi to ba ikọ BBC sọrọ sọ wi pe ile ẹjọ kọ lati gbẹ ẹjọ naa yẹwo nitori ọjọ ti lọ lori idajọ naa. Olajengbesi ni awọn n lọ si ile ẹjọ kotẹmilọrun ni ireti pe wọn yoo gbe ọrọ naa yẹwo daadaa lati se oun to tọ. O ni awọn ni igbagbọ pe ile ẹjọ naa yoo se oun to tọ ju nkan ti ile ẹjọ kekere se. Amọ, ile isẹ ọlọpaa ni Naijiria ti ni iwadii si n lọ lọwọ lori ẹsun ifipabanilopọ naa, pe awọn ko i tii pari isẹ lori rẹ. Busola Dakolo, ẹjọ́ ẹ ti kọjá odún mẹ́fà - Ileẹjọ Ile ẹjọ giga ni ilu Abuja ti fi ọwọ osi da ẹjọ ti ilumọọka ayaworan, Busola Fatoyinbo pe mọ pasitọ agba ile ijọsin Commonwealth of Zion Assembly (COZA). Dakolo fi ẹsun ifapabanilopọ kan Fatoyinbo ni ogun ọdun sẹyin. Idajọ ile ẹjọ waye lẹyin ti Fatoyinbo gbe ẹjọ kotẹmilọrun lati fi ẹsun kan Busola wi pe o ba orukọ oun je, ti o si puro mo oun lori esun ti busola fi kan oun. Fatoyinbo ni lati ibẹrẹ ni Busola ti n ba oun lorukọ jẹ, ti o si ba awọn oniroyin sọrọ lasiko ile isẹ ọlọpaa ti bẹrẹ iwadii lori ẹsun naa. Adajọ Oathman Musa ni ẹsun ti Busola pe mọ Fatoyinbo ko lẹsẹ n le, bakan naa ni wọn fi akoko ile ẹjọ sere.",0,yoruba ìwé orisirisi. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba "Lẹ́yìn tí ó dé ẹ̀wọ̀n gbogboògbò , Amade pe ẹgbẹ́ àwọn agbẹjọ́rò Mozambique tí ó sì sọ bí ó ṣe ti jìyà tó lọ́wọ́ àwọn ológun Mozambique tí ó ní wọ́n na òun tí wọ́n sì fi ebi pa òun .",0,yoruba "Sotitobire church: Àwọn ọ̀dọ́ ilu dáná sun ilé ìjọsìn Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa, Ọgbẹni Femi Joseph sọ fun BBC Yoruba pe awọn to dana sun ile ijọsin naa pa ọkan lara awọn ọlọpaa to lọ dena wahala. Iṣẹlẹ yi waye lasiko ti wọn n dana sun ile ijọsin naa ni owurọ Ọjọru. Lori iroyin pe ọlọpaa yinbọn pa ẹnikan nibi iṣẹlẹ naa, Ọgbẹni Joseph sọ pe oun ko le sọ pe nkan bẹ ẹ ṣẹlẹ. ""Mi o gbọ pe ọlọpaa pa ẹnikẹni nibi iṣẹlẹ naa, ṣugbọn nkan ti mo le sọ ni pe iwa ọdaran ni didana sun ile onile."" ""Ọlọpaa le lo ọnakọna, to fi mọ yinyin ibọn mọ afurasi ti ọwọ ba tẹ pe o n dana sun ile onile, ni ẹsẹ, ti iru afurasi bẹ ẹ ba n saalọ. Ti ibọn ba ba a ni ẹsẹ, to ba gba ibẹ ku, ko buru."" Ṣaaju ni iroyin kan gbode kan lowurọ yii pe wọn ri oku ọmọdekunrin Gold to dawati nile ijọsin Sotitobire nilu Akure, ni awọn ọlọpaa lọ si ile ijọsin ọhun. Bi awọn kan ṣe n sọ ina sinu ile ijọsin naa ni awọn mii n jo ọkọ̀ Ṣugbọn ọpọ ero to wa nibẹ ko jẹ ki awọn ọlọpaa ṣe iṣẹ wọn, eyii lo mu ki wọn yin tajutaju si awọn eeyan ọhun. Ni ọrọ ba di boo lọ ko yago fun mi ni eyi ti wọn ni ibọn ti ba ọdọkunrin meji. Lẹyin naa ni awọn ọdọ ilu dana sun ile ijọsin naa. Akọroyin BBC to wa nilu Akure nigba ti iṣẹlẹ ọhun waye jabọ pe, oun ko tii le fidi rẹ mulẹ pe wọn ri oku ọmọ naa nile ijọsin ọhun tabi bẹẹ kọ ṣugbọn wọn ko gbe oku ọmọ kankan sita ṣaaju didan sun ile ijọsin naa. 'Buns ni ọmọ mi jẹ tán ní ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá di àwátì' O ni awọn eeyan kan farapa ninu rogbodiyan naa, ti wọn si ti gbe wón lọ sile iwosan fun itọju ẹsẹ ti wọn ti gba ọgbẹ. Ṣaaju ni awọn ẹgbẹ obinrin ni ipinlẹ Ondo ti ṣe iwọde pe ki Gomina Akeredolu gbe igbesẹ to yẹ lori ọrọ yii Àwọn abiyamọ figbe ta lórí ọmọ ọdún kan ti wọn wá nílé ìjọsìn l'Akure Bi awọn kan ti n bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu awọn ọdọ agbegbe to dana sun ile ijọsin pe ko yẹ ki wọn gbe igbesẹ yii ni awọn miran ni awọn agb pe ijọba yoo ṣe ohun to kan bayii. Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin? Akure Kidnap: Wọ́n ti dáná sun ilé ìjọsìn Sọtitobirẹ nílú Akure Iroyin to n tẹwa lọwọ ni yajoyajo sọ pe awọn eeyan ti dana sun ile ijọsin Sọtitobirẹ Miracle Centre nilu Akure ni ipinlẹ Ondo. Bi awọn kan ṣe n sọ ina sinu ile ijọsin naa ni awọn mii n jo ọkọ̀ ti ọrọ di boolọ koo yago fun mi""Àwọn tó jí ọmọ mi gbé nílé ìjọsìn ní ń kò gbọdọ̀ wa tàbí kí ẹ̀mí mi lọ si"". Eyi ko ṣeyin iṣẹlẹ to waye nile ijọsin ọhun loṣu to kọja lataari bi ọmọdekunrin jojolọ kan ṣe di awati nibẹMissing Child: Òbí àti asọ́nà ṣọ́ọ̀ṣì 14, lọ́ búra nì'dí imọlẹ̀ l'Akure . Oṣu to kọja ni ọmọdekunrin jojolo kan di awati nile ijọsin ọhun Lẹyin naa ni iya ọmọ ọhun ke gbajari sita, ti awọn agbofinro si pe oluṣọagutan ijọ naa, woli Alfa Babatunde, fun ifọrọwanilẹnuwo. Ẹ wo awọn aworan diẹ lara awọn ohun to ṣelẹ nibẹ. Bi awon kan ṣe n pariwo pe wọn ri oku ọmọ naa nile ijọsin yii ni awọn miran ni pe irọ ni. BBC ko tii le fidi ohun to n ṣẹlẹ ni pato mulẹ. Sugbọn, ohun ti a ri dimu ni koko ni pe, wọn ti dana sun ile ijọsin naa bayii. BBC Yoruba yoo maa mu bi ohun gbogbo ba ṣe n lọ wa si oju opo yii. Oluwo Divorce: ko si ẹni ti kò mọ pé ọmọ ilẹ̀ òkèrè ni mó fi ṣe aya",0,yoruba àdùfẹ́ mi àwọn wo ni wọ́n tún ké sí ẹ tani ó tó bẹ́ẹ̀ láti bá mi du ìfẹ́ rẹ,0,yoruba Awọn oluwadii kan nileewe giga fasiti ilu Geneva lo fidi rẹ mu lẹ gbigbọ orin maa ṣe atunṣe ọpọlọ awọn ọmọde. Awọn oluwadii naa sọ siwaju pe orun orin yii maa n ran awọn ọmọ ti wọn bi nigba toṣu wọn ko tii pe lọwọ lati dagba.,0,yoruba "@user ẹ̀yin ni onísọkúsọ tí wọ́n ń sọ, ẹ kú ìsọkúsọ o.",0,yoruba "àkerekere. Nitori eyi, ara eni lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..",0,yoruba "Iroyin ni awọn oṣiṣẹ igbimọ amuṣeya to n ri si igbokegbodo oju popo ni ipinlẹ Eko, Task Force, ya bo agbegbe Abule-Egba ati Ijaiye lati ṣiṣẹ wọn, ṣugbọn awọn janduku doju ija kọ awọn osise ọhun pẹlu awọn ohun ija oloro. Wọn ni awọn oṣiṣẹ task Force yinbọn fun ọkan lara awọn janduku ọhun ti wọn jẹ awakọ, eyii to da wahala silẹ. Ija naa pọ to bẹẹ ti awọn ero ọkọ atawọn onisowo to wa lagbegbe naa ṣa asala fun ẹmi wọn. Alaga igbimọ amuṣẹya ọhun, Yinka Egbeyemi ṣo fun ileeṣẹ iroyin abẹle kan pe, ootọ ni iṣẹlẹ naa waye, ṣugbọn awọn oṣiṣẹ oun ko yinbọn pa ẹnikẹni lara awọn janduku naa. O ni ""Awọn janduku kan ko ara wọn jọ ninu ọkọ akero, wọn si kọlu awọn oṣiṣẹ wa, awa naa si kọlu wọn."" ""A ti fi panpẹ ofin mu awọn janduku ọhun, wọn si ti wa ni ahamọ wa."" Iṣẹlẹ naa mu ki ogunlọgọ awọn eeyan to yẹ ko wọ ọkọ fẹsẹ rin lẹyin ti awọn Danfo kọṣẹ lẹyin iṣẹlẹ naa. Ọkan lara awọn eeyan naa, Lanre Obabiyi sọ fun awọn akọroyin pe, ẹru ba oun nigba ti oun gbọ iro ibọn ti oun si sa lọ foripamọ ninu banki kan to wa lagbgbe ọhun. O ni oun fẹsẹ rin lati Abule-Taylor lọ si Salolo, ni Meiran. Ẹlomiran to ba awọn akọroyin sọro Esther Bajulaye ni ""Mo ti n fẹsẹ rin lati Abule Egba, mo dẹ ṣi n lọ si Tollgate, ko rọrun rara."" 'ìjà ṣẹlẹ̀ láàrín èmi àti ọ̀gá mi ní Lebanon tórí mi ò lè dá N300K padà'",0,yoruba ìrẹsì lake yìí ṣé kò ní gbéwó lórí bó bá yá,0,yoruba ènìyàn yì í tún ṣe àwọn iṣẹ́ tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa àwọn ènìyàn: ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Alàji lo tun se mú.,0,yoruba Adájọ́ Àgbà Orílẹ̀ - èdè Nàìjíríà ( CJN ) .,0,yoruba "ni ìbàdandun àtọ́wọ́dá, àwọn oníṣẹ́ ìṣẹ́ ni a ní nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò.",0,yoruba gbé lọ yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba yii nípa ìwé orisirisi ni nfàn ojú kakaaki.,0,yoruba RT @user: Ire àìkú tí í ṣe báálẹ̀ ọrọ̀..... #Aṣe #Atelewo #Yoruba,0,yoruba ìlú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba "Ní ti ẹ̀fẹ̀ , láì wí tó , panchayat náà sábà máa ń lọ́wọ́ sí ìpènìyàn ní àjẹ́ pàápàá bí kò bá pàṣẹ ìjìyà t'ó tọ́ .",0,yoruba Ìbàdandun ni ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn. (Item 165),0,yoruba "Ti Ọ̀gágun Buhari l'Èkó ń ṣe APC » 793,460 PDP » 632,341 #Lagos #NigeriaDecides #Ibo2015 #Yoruba",0,yoruba Ìbàdandun ni ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn. (Item 177),0,yoruba kí nìdí tí a ṣe wà níbí tí a kò bá tàkùrọ̀sọ pẹ̀lú ara wa,0,yoruba ♥ KÁÀSÀ! YORÙBÁ DÙN! ♥ #yobamoodua #yoruba,0,yoruba "Kodun,Kopo,Kope Eledumare loun funni. #TweetinYoruba",0,yoruba "ara eni lo ni ìgbà mi owó àkokò, Alàji lo ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba "Ikú pa abírí, abírí kú. Ikú pa abìrì, abìrì r'ọ̀run. Ikú pa Ọmọ Adú àtàtà, ó tún di ojú àlà. Sùn… https://t.co/JvC7DGa2Kg",0,yoruba Máà gbíyè lé ogún; ti ọwọ́ ẹni ní í tó 'ni. #EsinOro #Yoruba,0,yoruba Ọba lo ni ẹ̀ká àwẹ eyti o gbe lori àìmọ́ kọ.,0,yoruba "tí Ìyá fè lọ, Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..",0,yoruba "Àwọn afibisólóore kan tí a dá lóbìrin, t'ó ní ọmú, ó bímọ àmọ́ tí ò le è fún ọmọ rẹ̀ lọ́mú mu. Kí lọmú ń ṣe láyà bí kì í bá ṣoúnjẹ ọmọ.",0,yoruba "Kí a pa ti ọṣẹ dúdú gbètugbètu tì, ohun tí mò ń sọ ò ju pé, ọṣẹ dúdú dára fún àwọ̀ ara wa ju kílatińpèé ọṣẹ t'ó kúnta lọ. #Yoruba",0,yoruba ènìyàn tí oonka wọ́n jẹ́ lo fara kó àrun lana ní orílẹ̀èdè nàìjíríà |,0,yoruba "Ni kete ti Gomina tuntun ti ipinlẹ Osun, Ademola Adeleke gba eku ida lana ti wọn bura wọle fun lo ti yi ọpọlọpọ nnkan to ba nilẹ pada. Kete to wọ ọfiisi lo ṣe iyansipo gboogi mẹta kan ni ko ju wakati melo kan lọ to ṣe iburawọle. Ninu atẹjade kan ti Adeleke fi sita lọjọ Aiku ni o ti yan alaga kansu ijọba ibilẹ tẹlẹri nilu Osogbo, Ọgbẹni Kassim Akinleye gẹgẹ bii Ọga agba awọn oṣiṣẹ ni Osun.\n\nBakan naa lo buwọlu iyansipo Ọgbẹni Teslim Igbalaye gẹgẹ bii akọwe ijọba ipinlẹ naa nigba ti o ya Ọgbẹni Olawale Rasheed gẹgẹ bi Akọwe agba ijọba.\n“Gbogbo iyansipo yii gbudọ gberasọ ni waransesa.” Bakan naa ni iroyin ni gbogbo iyansipo ti gomina ana, Gboyega Oyetola ṣe ni ọjọ perete to ku ko kuro nipo ni Adeleke ti wọgile tori o ni “o lọwọ ibi ninu.”\nAdeleke ni Gomina Kẹfa ti yoo jẹ nipinlẹ Osun. Niṣe ni ariwo n ho yeee bi gomina ti wọn n bura wọle fun, Ademola Adeleke ṣe n ka ọrọ rẹ jade. Ori papa isere naa kun fọfọ fun ero to fi mọ awọn eekan oloṣelu ati ori ade ti wọn ba wọn pe nibẹ lati lọ yẹ Ademola Adeleke si. Ṣaaju ki Adeleke to bọ sori pepele ni Adajọ ti ṣe iburawọle fun igbakeji rẹ pẹlu iyawo rẹ. Ọpọlọpọ ọmọ ẹgbẹ ati agba oloṣelu ninu ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party lo wa nibi ibura wọle naa. Olu ilu Osogbo nipinle Osun ti gbe awo titun wo saaju ayeye ibura fún Gomina tuntun ti won dibo yan ọjọ kerindinlogun osu keje odun 2022, Seneto Ademola Adeleke to n waye ni oni ojo ketadinlogbon osù kọkànlá. Iyalẹnu lo jẹ fun awọn ololufẹ gbajugbaja ọdọ olorin, David Adeleke to padanu ọmọ rẹ Ifeanyi laipẹ yii pe yoo le ba ẹbi wọn pe nibi eto iburawọle aburo baba rẹ ti wọn sunmọ ara wọn timọ timọ. Akọroyin BBC Yoruba foju gaani rẹ nibẹ. Ni papa iṣere Osogbo stadium, nibi ayẹyẹ ibura fún Gomina tuntun atiwaye ni akoroyin bbc news yoruba ti ri pe gbogbo eto ni ṣepe. Orisiirisii posita Sen Ademola Adeleke ati Igbakeji Gomina Omoba Kola Adewusi ni won fi gbà gbogbo papa isere Osogbo káàkiri. Nibayi, eto aabo ti ibi pápá isere Osogbo wa ni pipe pẹlu awọn ọlọpa ti o ni ihamọra ni kikun ti n ṣọ ibi ti ayẹyẹ naa o ti wáyé. Gẹgẹ bi gbogbo eto ti wọn la kalẹ lati ibẹrẹ ọsẹ yii ṣe ti n lọ ni mẹlọ mẹlọ, oni ọjọ Kẹtadinlọgbọn Oṣu Kọkanla ọdun 20022 ni aṣekagba to si tun jẹ ọjọ ti wọn yoo bura wọle fun gomina wọn tuntun, Ademola, Nurudeen Jackson Adeleke. Bo tilẹ jẹ ke ọwẹ diẹ sẹyin yii ko fi bẹẹ rọgbọ tori gbogbo ẹjọ ti Gomina Oyetola pe Adeleke to si wọ ọ lọ ile ẹjọ, ọjọ naa tun pada ko lonii. Lara awọn nnkan to ti ṣẹlẹ ṣaaju ọjọ yii ni: Ile ẹjọ́ giga ijọba apapọ to wa nílùú Osogbo, nipinlẹ Osun, ti wọgile eto idibo ijọba ibilẹ to waye ni oṣu Kọkanla.\n\nỌjọ karundinlogun, oṣu Kẹwaa, ni ajọ eleto idibo ipinlẹ naa ṣe eto idibo ọhun.\n\nAdajọ Nathaniel Ayo-Emmanuel, sọ ninu idajọ rẹ pe eto idibo naa tako ofin idibo, abala kọkandinlọgbọn ati abala kejilelọgbọn, ti ọdun 2022.\n\nẸgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party, lo pe ẹjọ́ tako idibo naa, to si ni ki ile ẹjọ́ pàṣẹ fun ajọ eleto idibo ipinlẹ Osun OSIEC, lati má ṣe eto idibo kankan. Gomina ipinlẹ Osun, Gboyega Oyetola ti kede pe oun ti buwọlu iyansipo awọn osisẹ ijọba toto ọgbọn niye gẹgẹ akọwe agba fun awọn ẹka ijọba ni o ku ọjọ mẹta ti yoo fi po silẹ gẹgẹ gomina ipinlẹ naa.\n\nOrukọ awọn akọwe ọhun lo wa ni atẹjade ti akọwe agba fun ijọba ipinlẹ Osun, Dokita Festus Oyebade buwọlu fun awọn akọroyin lana.\n\nOyetola lo lulẹ labẹ asia ẹgbẹ oṣelu APC ninu eto idibo Gomina to waye ninu oṣu keje, ti Ademola Adeleke lati inu ẹgbẹ oṣelu PDP si gbe igba aroke.\n\nSugbọn kete ti ijọba ipinlẹ gbe ikede naa jade ni Gomina tuntun ti ilu dibo yan, Ademole Adeleke fesi pada ninu atẹjade ti agbẹnusọ rẹ, Olawale Rasheed bu wọlu to si tako igbesẹ naa. Ajọ eleto idibo, INEC, ti sọ pe awọn iwe ẹri gomina tuntun ti wọn dibo yan nipinlẹ Osun, Ademola Adeleke, ko si lọwọ oun mọ.\n\nAlaga ajọ naa nipinlẹ Osun, Ọmọwe Mutiu Agboke, sọ nile ẹjọ to n gbọ ẹsun awuyewuye to waye lẹyin idibo gomina ipinlẹ naa, lọjọ Iṣẹgun pe oun ko ni Form CF 001 ti Adeleke lo lọdun 2018 lọwọ mọ.\n\nỌsẹ to kọja ni ile ẹjọ naa paṣẹ fun INEC, pe ko mu fọọmu naa wa sile ẹjọ, lẹyin ti olupẹjọ, Gomina Gboyega Oyetola bẹ ile ẹjọ lati ṣe bẹẹ.\n\nOṣu Kẹjọ, ọdun 2022, ni Gomina Oyetola ati ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC, fi iwe ẹsun naa ranṣẹ sile ẹjọ.\n\nForm CF 001 ni fọọmu ti oludije fi forukọ silẹ lati dije, ati awọn iwe ẹri ti Adeleke fun INEC lọdun 2018. Gomina tuntun ti wọn sẹsẹ dibo yan nipinlẹ Osun, Ademola Adeleke ti rọ Gomina to ti fẹ kogba wọle, Gboyega Oyetola pe ko gba kamu pe o ti lulẹ ninu eto idibo gomina to waye ni oṣu Keje, pe ko si simi ariwo ni pipa.\n\nAgbẹnusọ Adeleke, Olawale Rasheed ninu atẹjade to fi ransẹ si Oyetola lẹyin to kede pe oun yoo gba ẹtọ oun, ni pe ko si ẹtọ kankan to fẹ gba lọwọ Adeleke nitori gbogbo ọna ni o fi fi idi rẹ janlẹ ninu eto idibo gomina to waye nipinlẹ Osun.\n\nO ni erongba buburu ni Oyetola ni si awọn eeyan ipinlẹ Osun latari bi o ṣe n fi irọ ati ailotọ ṣe ijọba rẹ.\n\nAdeleke ni kete ti Oyetola ri pe oun ti lulẹ ni o ti bẹrẹ si ni maa ṣe owo ipinlẹ naa basubasu sugbọn ti ile ẹjọ si ti tu ọpọlọpọ irọ ti Oyetola pa fun awọn eeyan. Bi ẹ ko ba gbagbe, lara ajọyọ ti gbajugbaja olorin nni Davido n ṣe nigba ti ibura wọle ẹgbọn rẹ Adeleke sunmọle naa ni pe awọn yoo jọ wa nibẹ ni. Ko pẹ rẹ ni ọlọjọ de ti o mu Ifeanyi ọmọ Davido lọ. Eyi lo faa ti ẹgbẹ oṣelu PDP ni ipinlẹ Osun ṣe daro iku ọmọ naa ti wọn si dawọ eto ti o yẹ ki wọn ṣe lọsẹ naa duro.",0,yoruba @user bẹ́ẹ̀ni o. Mo máa nyín amóhùnmáwòrán mi sílẹ̀ ni kí ará-àdúgbò má pe ọlọ́pàá sí mi. :),0,yoruba 12. #PariOweYii Bí ọlọ́pàá bá fọn fèrè... #Ibeere #Yoruba #OweIgbalode,0,yoruba gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọba lo tun se fi.,0,yoruba "kún fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba "Lórí òpó Twitter Banki náà ni wọ́n ti sàlàye pé àwọn ko ti le fi idi rẹ̀ múlẹ̀ ǹkan to baje nínú ilé iṣẹ́ náà Akọròyìn BBC tó sabewo síbẹ̀ sàlàyé pé kò si ẹni tó mọ ǹkan to fa idi ti ìnà fi ṣẹlẹ náà, Ṣùgbọ́n gbogbo àwọn panápaná àti àwọn osiṣẹ alààbo míràn ti wà níkàlẹ lati fopin si. Unity Bank: Kátàkára sí ń lọ nínú ọ̀gbà Banki náà Yollywood: Kò sí ẹni ti òbí mi kò lè sọ̀rọ̀ sí -Sisi Quadri Lórí òpó Twitter Banki náà ni wọ́n ti sàlàye pé àwọn ko ti I le fi idi nkan to faa mule. Awọn oṣiṣẹ eleto aabo sa ipa wọn ;ati tete pa ina naa Bakan naa ni wọn ko tii le sọ ni pato iye awọn ǹkan to baje nínú ilé iṣẹ́ náà, sùgbọ́n ìdùnù ló jẹ́ fún wa pé kò si ẹ̀mi to sọnu ninú ìṣẹ̀lẹ̀ náà. Won ti pa ina naa aw#on osise si ti bere ise won pada Wọ́n fi kún pé àwọn oṣiṣẹ́ àwọn si n da àwọn onibara lohun nitori pe gbogbo ko si ìdànmú to kan agbègbè rẹ̀. Awọn agbofinro ipinlẹ Eko duro wamu lati fopin si banki naa to n jona. Bakan naa ni won tun di ona to wo adugbo naa pa ki awon eniyan ma le kagbako ina Aw#on panapana sisie daadaa lati tete pa ina naa Lara mọtọ to jona ninu iṣẹlẹ ọhun Yollywood:Ṣàgbẹ̀lójú yòyò ni ọ̀ps àwọn òṣèré- Ojopagogo",0,yoruba "Olorin takasufe, David Adeleke, ti ọpọ awọn ololufẹ rẹ mọ si Davido ti kede pe oun yoo pin gbogbo owo to ri gba fun ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ si ile awọn ọmọ alainiya kaakiri Naijiria. Iye owo ti Davido ni oun yoo pin sawọn ile awọn ọmọ alainiya naa jẹ òjìlénígba lé mẹwaa miliọnu naira lapapọ. Davido lo kede igbesẹ naa ninu atẹjade kan to fi sita loju opo Instagram rẹ lọjọ Abamẹta. Atẹjade naa ni ""Mo fẹ fi ẹmi imoore mi han si gbogbo awọn ọrẹ mi atawọn ololufẹ mi fun oun ti wọn ṣe lẹnu ọjọ mẹta yii."" ""Bii ere, bi awada ni mo fi bere lọwọ awọn ololufẹ mi pe ki wọn da owo jọ fun ayẹyẹ ọjọ ibi mi ti yoo waye laipẹ, ṣugbọn iyalẹnu lo jẹ fun mi pe awọn eeyan fun mi ni igba miliọnu naira."" Lẹyin naa lo sọ pe oun yoo fi aadọta miliọnu naira kun igba miliọnu naira ti wọn da fun oun lati pin si awọn ile awọn ọmọ alainiya kaakiri Naijiria. O ni ""Inu mi maa n dun lati ṣoore fun awọn eeyan, idi ree ti inu mi ṣe dun lati kede pe gbogbo igba miliọnu naira ti mo ri gba ati aadọta miliọnu naira mii ti n o fi kun un yoo lọ sile awọn ọmọ alainiya."" Ọmọ baba olowo naa tun sọ pe oun ti gbe igbimọ kan dide ti yoo maa ri si bi wọn yoo ṣe pin owo ọhun. Ti ẹ ko ba gbagbe, ọjọ kẹtadinlogun, oṣu Kọkanla ti a wa yii ni Davido ke si awọn ọrẹ rẹ lori ayelujara pe ki wọn da miliọnu kọọkan naira fun oun lati fi ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi. Ṣugbọn ka to wi, ka to fọ, awọn eeyan ti da owo to le ni ọgọrun un miliọnu naira jọ fun lati ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi naa laarin wakati mẹrinlelogun. Ọjọ kọkanlelogun, oṣu Kọkanla, ọdun 1992 ni wọn bi Davido.",0,yoruba "#TweetYoruba #TweetYoruba #TweetYoruba #TweetYoruba #TweetYoruba Aku ajodun, emi a se opolopo #TweetYoruba http://t.co/KRb2e4hfR8",0,yoruba Àwọn ọlọ́gbọ́n àtinudá Ilẹ̀ - Adúláwọ̀ gbọdọ̀ 'ká èso ọrọ̀ tí ó pọ̀ tí ó ń dúró fún kíká',0,yoruba rara ooo omo ijesha osere onile obi ni mii sugbon mo feran awon omo ikorodu oga omo eluku mede mede,0,yoruba nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó wáyé..,0,yoruba Ikọ̀ awakọ̀ òfuurufú olóbìrin àkọ́kọ́ irúu rẹ̀ ní Mozambique | A lo àwòrán pẹ̀lú àṣẹ láti ọwọ́ Meck Antonio .,0,yoruba Baàlè ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba ".@user O ti jawe olubori níbi ìdánwò @user fún tí oṣù kọkànlá. Jọ̀wọ́ fi nọ́mbà ẹ̀rọ ìléwo rẹ àti irú netiwooku to ń lò sowo sì ibi atejise itakun yìí kì a lè fi ẹ̀bùn káàdì rẹ ṣowo sì ọ, gẹ́gẹ́ bí a ti ṣe ìlérí 👏👏👏👏🕺🕺🕺💃💃💃💃👯‍♀️👯‍♀️👯‍♀️👯‍♀️👯‍♂️👯‍♂️ https://t.co/xVz2EugWlH",0,yoruba "Ṣùgbọ́n bi àwọn ọmọ Naijiria ṣe ri ọ̀rọ̀ yìí àti ojú ti wọ́n fi wò ó ni o gbòde kan báyìí ninu àpéro ti wọ́n ń ṣe lori ọ̀rọ̀ náà lori twitter. Ọ̀pọ̀ lori ayelujara gbà pé ko tọ́nà láti ṣe eyí niwọ̀n ìgbà ti igbákeji ààrẹ Naijiria ọjọgbọ́n Yemi Osinbajo wà nílùú to si yẹ ki wọ́n gbé ìjọba silẹ̀ fún. Ibadan Torture House:Àṣírí ilé ìmúni nígbèkùn míràn tú síta ni Katsina Agbẹjọro takò ìgbésẹ yí Nígbà tí BBC Yoruba kàn sí agbẹjọro kàn tó fí ìlú Akure ṣé ibùjókòó, o sọ pé kò t'ọna bí ààrẹ Buhari ti ṣé fí Nàìjíríà sílẹ lọ sí ìlú London láì gbé àṣẹ ìjọba kalẹ fún igbákejì ààrẹ. Morakinyo sọ pe Aarẹ Buhari kuna pẹlu bi ko ti ṣe fi iwe ranṣẹ si ile aṣofin Naijiria nipa irinajo rẹ. O tẹsiwaju pe koda bi o ba tilẹ wa rinrin ajo lọ si ilẹ okere, abadofin to buwọlu kii ṣe fun awọn eeyan ilẹ miiran bi kii ṣe fun awọn ọmọorileede Naijiria. ''Ko si ipinya to yẹ laarin awọn ẹka ijọba ni Naijiria, eyi laa si n ri labẹ ijọba to wa lode yii''. Mo ti sọ ìran nípa ọkọ aképo tó gbiná ní Onitsha kó tó ṣẹlẹ̀ - Prinmate Ayodele Kíní Abadofin náà jẹ ti Abba Kyari fi gbé bàálù lọ bá ààrẹ láti tọ́wọ́ bọ̀ ọ́ Abadofin ọhun niṣe pẹ̀lú àwọn ǹkan to niṣe pẹ̀lú ọ̀rọ̀ wíwa epo Nàìjíríà (Offshoreand Basin Production Sharing Contract)Act Ààrẹ Buhari lori àtẹjiṣẹ́ twitter rẹ̀ sàpejuwe títọwọ́bọ iwé abádofin náà bi igbésẹ to lààmi laaka fún orilẹ̀-èdè Naijiria Abadófin náà yóò mú kí pínpín èrè owó epo rọrun láwọn ipin lẹ to ni kanga epo Ko yẹ ki ààrẹ fi ilu silẹ̀ lai gbé ijọba le enikẹni lọ́wọ́",0,yoruba "Gbajugbaja oṣere ori itage Nollywood, Genevieve Nnaji ja gudugbẹ ọrọ lulẹ lori ọrọ ibalopọ ati ifẹ laarin ọkunrin ati obinrin. Genevieve Nnaji gba awọn obinrin ni imọran ohun loju opo ikansiraẹni Facebook rẹ. Genevieve woye pe ""ẹni to ni Ibalopọ pẹlu rẹ le ma nifẹ rẹ, bakan naa ẹni to ni ifẹ rẹ denu le ma ni Ibalopọ pẹlu rẹ."" ""Ẹyin obinrin ẹ ronu o, ọkunrin to korira rẹ le ba ọ sun,"" Genevieve kilọ. O ni ofuutu fẹẹtẹ lasan ni erongba awọn obinrin kan to gbagbọ pe awọn le fi nini ibalopọ pẹlu ọkunrin mu un mọlẹ lati fẹ wọn gẹgẹ bi aya. Genevieve ni ""itanra ẹni jẹ ní kí obinrin maa ro pe oun le mu ki ọkunrin nifẹ oun nipa fífi ara rẹ silẹ fun Ibalopọ."" O ni ""ifẹ aiṣẹtan kii fi tipa mu obinrin lati ni Ibalopọ pẹlu rẹ."" Genevieve sọ pe ""ọkunrin to ba ni ki o fi ìfẹ hàn s'oun nipa Ibalopọ n lo ẹ ni, yóò ja ẹ ju silẹ to ba ti ri ẹlomiran to gbadun Ibalopọ pẹlu rẹ ju ẹ lọ."" ""Iwa omugọ ni ki obinrin sọ ara rẹ di ẹru ọkunrin fun Ibalopọ,"" Genevieve lo sọ bẹẹ. O rọ àwọn obìnrin tí wọn ba ti n gbero lati fi Ibalopọ de ọkunrin mọlẹ pe ki wọn tun ero wọn pa, ki wọn si ṣe ipilẹ tuntun fun Irinajo ifẹ wọn. Genevieve fikun ọrọ rẹ pe ""ewu n bẹ loko longẹ fun igbeyawo ti ọkunrin ba fẹ obinrin nitori Ibalopọ."" ""Gba lati fẹ ọkunrin to ba nifẹ rẹ denu, jẹ ki ọkunrin naa bu iyì fun ẹ, ki o si ṣetan lati lo gbogbo igbesi aye rẹ pẹlu rẹ,"" ọrọ ree lati ẹnu Genevieve.",0,yoruba ẹkú òwúrọ̀ o ẹ̀yin ọmọ oòduà ṣé dáadáa la jí,0,yoruba "Ọlọ́hun máa ṣọ́ wa, má jẹ̀ẹ́ a pàdé àgbákò.",0,yoruba "Ninu atẹjade ti ẹka iroyin ileeṣẹ ọmọogun Naijiria fi lede ni iroyin naa ti han si awọn araalu. Ọgagun Farouk ni oun dari ikọ awọn ọmọogun Naijiria to n koju ikọ Boko Haram ni ariwa orilẹede Naijiria, ti wọn pe ni HADIN KAI. Aarẹ Buhari yan adari ikọ tuntun fun awọn ọmọogun Naijiria naa lẹyin ijamba ọkọ ofurufu to mu ẹmi Ọgagun Ibrahim Attahiru lọ ati awọn ọmọogun mẹwaa miran. Ileeṣẹ ikọ ọmọogun ofurufu naa ni awọn ṣi n ṣe iwadii ijamba ọkọ ofurufu to waye ni tosi papakọ ofurufu to wa ni ilu Kaduna. Tani Ọgagun Farouk Yahaya ti wọn ṣẹṣẹ yan?",0,yoruba "Akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea, Frank Lampard ti fi idunnu rẹ han pẹlu bi wọn ṣe na Crystal Palace lalubami pẹlu ami ayo mẹrin si odo. Lampard ni aṣeyọri awọn ko ṣẹyin agbabọọlu tuntun, Ben Chilwell ti wọn ra fun miliọnu marundinlaadọta pọun. Chilwell to jẹ ẹni ọdun mẹtalelogun lo gba bọọlu wọ inu awọn, nigba ti Zouma ṣe iranwọ fun goolu keji, Jorginho gba penariti wọ inu awọn ni igba kẹta ati ikẹrin. Amọ, Frank Lampard ti rọ awọn agbabọọlu rẹ lati farabalẹ nitori ere ṣẹṣẹ bẹrẹ ni. Laipẹ yii ni Liverpool lu Chelsea ni alubami, ko to di wi pe wọn gberasọ pada. Bakan naa naa ni Everton naa Brighton ni ami ayo mẹrin si meji , nibi ti Rodriguez ti gba ami ayo meji wọ ni awọn, ti CalverLewin ati Mina naa gba bọọlu wọ inu awọn.",0,yoruba "Eni ti ko ba ni'fe iya ti o bi i tokan-tokan, a padanu ibukun nla ni'le aye e @user does making my own Yoruba proverb count? #Naijaproud #wizkid #Nigeria #LoveYourMum #Yoruba #OmoBalogun #Iya #Respect #Love #Africa 💙😍 https://t.co/HQ5HcFwqcW",0,yoruba titoole ki se ohun ti o ye ki a maa daamu le lori asiko ni titoole ti yoo koja lo,0,yoruba "Naming of Railway stations in Nigeria: Afenifere, YCE, Akitoye, Fani-Kayode ní ẹ̀tanú Obasanjo ni Buhari ṣe",0,yoruba olùparapọ̀ ri pe jẹ́ pàtàkì wey ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba "Ṣaaju abẹwo yii, aarẹ ti kọkọ ṣabẹwo si ipinlẹ Taraba, Plateau, Benue ati Zamfara Gomina Abubakar Badaru ti ipinlẹ Jigawa, Abdullahi Ganduje tipinlẹ Kano, Ibrahim Geidam ti ipinlẹ Yobe, Abdullahi Abubakar ti ipinlẹ Bauchi, pẹlu Aminu Masari lati ipinlẹ Katsina, ni wọn wa nikalẹ lati gba Aarẹ Buhari lalejo ni papakọ ofurufu ilu Dutse. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ireti wa wi pe, Aarẹ Buhari yoo ṣe abẹwo sawọn iṣẹ akanṣe kan ni agbegbe Hadejia, Auyo ati Dutse ni ipinlẹ Jigawa lasiko abẹwo ọhun. Ọ̀gọ̀rọ̀ àwọn èèyàn ló jáde wá pàdé Ààrẹ Buhari nígbà tó gúnlẹ̀ sí pápákọ̀ òfúrufú ní Dutse Nibayii, Aarẹ Buhari ti wa ni Auyo lati ṣi ibudo ipese omi to wa ni Hadejia. Wahala ọrọ aabo to gbode ni irinajo aarẹ da le lori Iroyin sọ wi pe, ọgọọrọ awọn olugbe ipinlẹ naa ni wọn tu sita lati ki Aarẹ buhari kaabọ sibẹ. Ṣaaju abẹwo yii, aarẹ ti kọkọ ṣabẹwo si ipinlẹ Taraba, Plateau, Benue ati Zamfara lori wahala ọrọ abo to gbode kan lawọn agbegbe kan lorilẹede Naijiria.",0,yoruba "Kem mo garri kin to kole, ko le nho ni bodi mi. #Yoruba",0,yoruba "àìlẹ̀, Olùwo ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó ṣe pàtàkì.",0,yoruba tèmi. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé.,0,yoruba ǹjẹ́ ìwọ mọ̀ wípé ní ọdúnun àwọn ogúnlémdé tí í ṣe ọmọ ìbàdànọ̀yọ́ ló ń gbé ní modákẹ́kẹ́,0,yoruba yẹn ti gbogbo eniyan sọ o ṣe pataki.,0,yoruba ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ àti ìbi tí wọn wà.,0,yoruba "RT @user: @user Adiitu Olodumare, Ogboju Ode ninu igbo irunmole, Ireke Onibudo, Igbo Olodumare, Irinkerindo ninu igbo elegbeje. #Fa…",0,yoruba "Ile ẹjọ to n gbọ ẹjọ aṣemaṣe pẹlu ọmọ kekere ti wọn fi kan gbajumọ oṣere sinima Yoruba, Lanre Omiyinka ti ọpọ mọ si Baba Ijesha ti sun igbẹjs lori ẹjọ naa si ọjọ kọkanla ati ati ikejila oṣu kẹjọ ọdun 2021. Ninu ile ẹjọ loni, ọmọdebinrin ti ijọba ipinlẹ Eko n pẹjọ pe Baba Ijẹṣa hu iwa aṣemaṣe pẹlu wa nile ẹjọ ti ile ẹjọ si gbọ ti ẹnu rẹ ni idakọnkọ lẹyin ti adajọ ni ki gbogbo awọn ero ati akọroyin to wa ninu ile ẹjọ naa o jade. Bakan naa ni ikọ agbẹjọro fun Baba Ijẹsha tun ṣe ifọrọwanilẹnuwo fun Princess to jẹ alagbatọ ọmọdebinrin naa. Amofin Kayọde Ọlabiran ṣalaye fun awọn oniroyin pe wọn ko tii fi ọrọ wa Baba Ijesha lẹnu wo ninu ile ẹjọ naa bayii. Baba Ijẹṣa, Princess to jẹ alagbatọ ọmọdebinrin naa ati ọmọdebinrin ti ọrọ kan ni wọn wa ni ile ẹjọ naa loni. Nibi igbẹjọ gbajugbaja oṣere fiimu Yoruba, Olanrewaju Omiyinka ti ọpọ mọ si Baba Ijesha, adajọ ti gba pe ki ọmọde kan wa jẹri. Igbẹjọ naa lo n waye ni ile ẹjọ ti wọn ti n gbọ ẹsun aṣemaṣe to lu mọ ibalopọ nilu Eko. Amọ ṣe ni adajọ le gbogbo awọn to wa nikalẹ nile ẹjọ sita tori pe o ni ni ibamu pẹlu ofin, ero ko le wa nibẹ bi ẹlẹri to jẹ ọmọde ba wa jẹri. Ọmọde naa ni wọn ni o ni ohun to lee sọ si iṣẹlẹ to waye yii. A ń gbóhùn àdúrà sókè ní orílẹ̀èdè 127 lágbàáyé torí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Baptist tí wọ́n jígbé ní Kaduna -Baptist Convention Ta ló pa Toheeb ""kunlékunlé"" nílé ọ̀rẹ́ rẹ̀ ní Ikotun? Wọ́n ti fi ẹ̀sùn míì kan Sunday Igboho ní ìlú Benin! - Agbẹ́jọ́rò Igboho Awọn alatilẹyin Baba Ijesha ati Princess Damilola ti tete de si agbegbe ile ẹjọ lati nkan bii ago mẹsan-abọ owurọ. Lọjọ Aje ni adajọ Oluwatoyin Taiwo sun igbẹjọ naa siwaju lẹyin ti olupẹjọ, oṣere Princess Commedienne ti orukọ rẹ n jẹ Adekola Adekanye kọkọ ṣalaye ẹjọ tirẹ to lodi si ti oṣere akẹgbẹ rẹ to fẹsun kan. Baba Ijesha ti wọn fi ẹsun mẹfa ọtọọtọ kan lara eyi ti ifipa bani lopọ, fifi ipa fi nkan ọmọkunrin wọ ara obinrin, aṣemaṣe pẹlu ọmọde ati bẹẹ lọ gbogbo eyi ti wọn ni o lodi si abala ofin 259, 135, 261 iwe ofin ipinlẹ Eko ọdun 2011 ati abala 135, 263, 262 ti ofin ipinlẹ Eko ti ọdun 2015. Ijọba ipinlẹ Eko rọ ile ẹjọ to n gbọ ẹjọ Baba Ijẹsha lori ẹsun aṣemaṣe pẹlu ọmọdebinrin kan pe ko fofin de gbajumọ oṣere tiata Yoruba ni, Yọmi Fabiyi pe ko gbọdọ wọ ile ẹjọ naa mọ. Agbẹjọro fun ijọba lori ẹjọ naa, Amofin Olayinka Adeyẹmi ni Yọmi fabiyi ti huwa kini ile ẹjọ yoo ṣe pẹlu sinima tuntun rẹ 'Ọkọ Iyabọ' to gbe jade. Gẹgẹ bi o ṣe sọ sinama naa da lori igbẹjọ ile ẹjọ naa to waye lọjọ kẹrinlelogun oṣu kẹfa ọdun 2021 lẹyin ti adajọ ile ẹjọ naa ti paṣẹ pe ki ẹnikẹni o dakẹ ọrọ lori ikanni gbogbo nipa ẹjọ naa. Ọkan gboogi lara awọn oṣere to gbohun soke lẹyin Baba Ijẹsa ni Yọmi Fabiyi lati igba ti ọrọ ẹsun aṣemaṣe naa ti bẹrẹ. Agbẹjọro Ijọba ipinlẹ Eko naa ṣalaye fun ile ẹjọ pe gbogbo awọn ọrọ to nii ṣe pẹlu igbẹjọ naa ni Yọmi Fabiyi fi sinu sinama tuntun to ṣẹṣẹ gbe jade naa leyi to ni o tapa si ofin ibọwọ fun ileẹjọ. Amọṣa agbẹjọro fun Baba Ijẹṣa, Amofin Dada Awoṣika SAN ṣalaye pe ọrọ ko ri bẹẹ rara nitoripe ki igbẹjọ naa to bẹrẹ ni Yọmi Fabiyi ti bẹrẹ iṣẹ lori sinima naa. Amofin Awoṣika ni oun pẹlu ti wo sinima naa ko si si sna kan to fi gba tako aṣẹ adajọ ile ẹjọ naa. Ninu ọrọ rẹ, Onidajọ Oluwatoyin Taiwo to n gbọ ẹjọ naa beere boya Yọmi Fabiyi wa ninu ile ẹjọ naa ti wọn si daa lohun pe rara. Nigba ti agbẹjọro ijọba ni o ṣeeṣe ki awọn aṣoju rẹ o wa nibẹ lati ṣoju rẹ, Onidajọ Taiwo ni ko si bi ile ẹjọ ṣe lee mọ ẹni to wa ṣoju rẹ nile ẹjọ niwọn igba ti ko si ẹnikẹni to kọọ siwaju ori pe awọn n ṣoju fun un. Ile ẹjọ to n gbẹjọ osẹre tiata Yoruba, James Omiyinka ti ọpọ mọ si Baba Ijesha ti sun igbẹjọ siwaju. Adajọ Oluwatoyin Taiwo sun igbẹjọ naa si ọjọ kẹtadinlogun oṣu keje ọdun 2021 yii. Ẹsun ifipabanilopọ lo wa ni ile ẹjọ ti wọn fi kan Baba Ijesha. Ẹwẹ, adẹrinpoṣonu, Gbenga Adeyinka ba BBC Yoruba sọrọ pe ododo gbọdọ fi oju han lori ọrọ Baba Ijesha. Adeyinka ni ẹlẹṣẹ ko gbọdọ lọ lai jiya ẹṣẹ rẹ lori ọrọ to wa nilẹ yii. Oṣere akẹgbẹ rẹ to n tii lẹyin lati ọjọ yii, Yomi Fabiyi ko farahan nile ẹjọ tori ko si ni orilẹede Naijiria lati igba ti ẹgbẹ awọn oṣere TAMPAN ti pee fun ẹjọ ti ko si yọju. Lara awọn to peju si ile ẹjọ ni gbajugbaja oṣerebinrin to n ti Princess, iya ọmọ ti wọn ni baba Ijesha fẹ fipa ba lopọ lẹyin, Iyabo Ojo amọ o kọ lati ba awọn oniroyin sọrọ. Bakan naa, awọn mọlẹbi Baba ijesha bii aburo rẹ ati iya iyawo rẹ ṣi duro gba gba tii lẹyin lai mira ti wọn si wa nile ẹjọ. A o maa mu ẹkunrẹrẹ wa fun un yin.",0,yoruba "lòdì Ìbàdàn. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba lọ yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ẹkọ́: ti o pataki.,0,yoruba iwa rere. Bàbá lo ni ẹ̀ká àwẹ eyti o gbe lori iwa rere.,0,yoruba "Iku ojiji to ma n pa awọn ọmọ tuntun, eyi ti awọn onimọ n pe ni Sudden Infant Death Syndrome (SIDS) ma n waye nitori oriṣiriṣi nkan. Ọpọ iku yii si lo ma n ṣẹlẹ laarin oṣu mẹfa akọkọ ti ọmọ ba de ile aye. Yatọ si pe afọwọfa le fa a, ọmọ ti oyun rẹ ko pe oṣu mẹsan-an tabi ti ko tobi daadaa nigba ti wọn bi naa wa ninu ewu iku ojiji. Iku ojiji yii ṣaba ma n ṣẹlẹ lasiko ti ọmọ tuntun ba sun. Nitori naa, ẹ wo awọn nkan mẹsan-an to le dena iku ojiji fun ọmọ tuntun. Jẹ ki ọmọ tuntun fi ẹyin sun Iwadii awọn onimọ iṣegun oyinbo fihan pe ewu to le fa iku ọmọ tuntun wa ninu ki ọmọ ma a fi ẹgbẹ sun tabi da ikùn bolẹ sun. Idi ni pe ọmọ to ba fi ẹgbẹ sùn le yi, ko si doju bolẹ. Ti iru ọmọ bẹ ẹ ba doju bolẹ si ori ibusun, ibusun le di eemi to n jade tabi wọle si iho imu ọmọ tuntun naa. Eyi to le fa iku. Titẹ ọmọ tuntun si ori ibusun to le Lati le dena ki aisi eemi pa ọmọ tuntun, o ṣe pataki lati tẹ wsn si ori ibusun 'mattress' to le daadaa, tabi awọn ibusun ti wọn ṣe fun ọmọ tuntun. O ko si gbọdọ fi ohunkohun bi i aṣọ ibora, irọri tabi awọn nkan iṣere si ori ibusun naa, eyi to le fun ni ọrun pa. Awọn onimọ iṣegun ni US Department of Health and Human Services sọ pe eyi ma n mu adinku ba ijamba oju orun to le pa ọmọ tuntun. Ma ṣe fa siga ni ẹgbẹ ọmọ tuntun Awọn onimọ iṣegun oyinbo sọ pe o dara ki obinrin to ba n mu siga fi opin si lasiko to ba wa ninu oyun, lati le dena iku ọmọ tuntun. Iwadii fihan pe awọn ọmọ ti iya wọn ba fa siga ninu oyun wọn kii ṣaba tobi bo ṣe yẹ lasiko ibi wọn - eyi si jẹ ara nkan to n fa iku ọmọ tuntun. Bakan naa, fifa siga nitori ọmọ tuntun le ṣeku pa a. Gbe ọmọ rẹ si tosi rẹ Iwadii fihan pe ko fi bẹ ẹ si ewu iku fun ọmọ tuntun to ba sun sinu yaara kan naa pẹlu iya rẹ. Idi ni pe iya naa yoo mojuto daadaa. Ṣugbọn ṣa, iru iya bẹẹ gbọdọ kiyesara ki o ma sun lọ lasiko to ba n fun ọmọ ni ọmu. Eyi lewu, nitori pe ọyan rẹ le di ọmọ ni imu, ti ko ni i le mi daadaa, to si le fa iku. Fifun ọmọ ni ọyan daadaa Oriṣiriṣi anfaani lo wa ninu fifun ọmọ ni ọyan, lara wọn si ni pe o le dena iku ọmọ tuntun. Awọn eroja to wa ninu omi ọyan ni agbara lati dena awọn aarun to le ṣeku pa ọmọde. Ṣugbọn, o tun lewu fun obinrin to n fun ọmọ lọyan lati ma a mu ọti. Abẹrẹ ajẹsara Iwadii imọ ijinlẹ sọ pe awọn ọmọ to ba gba abẹrẹ ajẹsara ni ilana awọn onimọ iṣegun oyinbo ni anfaani ida aadọta pe wọn o le ku ni smọ tuntun. Eyi ko ṣẹyin bi awsn abẹrẹ naa ṣe ma n dena aarun to le ṣeku pa ọmọ. Ma jẹ ki ooru mu ọmọ tuntun ju Lootọ ni awọn agbalagba tabi awọn to ti bimọ ri ma n gba iya ọmọ tuntun ni imọran pe ko fi aṣọ bo ọmọ nitori otutu. Ṣugbọn, ti ooru ba tun pọ ju fun ọmọ tuntun, o le ṣeku pa a. O dara lati wọ aṣọ fẹlẹfẹlẹ fun ọmọ tuntun lasiko ooru, o si tun le wọ ibọsẹ ati ibọwọ fun. Bakan naa ni ki atẹgun to n wọ inu yaara o si jẹ eyi ti ko tun pọju. Ifeto sọmọ bibi Yatọ si pe o lewu fun obinrin lati tete bimọ le ọmọ tuntun, o tun le ni ipa ti ko dara ni ilera ọmọ. Idi ni pe ti obinrin ba tete loyun le ọmọ, ko ni i ni okun lati tọju ọmọ to wa nilẹ tabi ara rẹ. Nitori naa ni awọn onimọ ṣe ma sọ pe ki obinrin duro fun bi ọdun kan tabi meji ko to o loyun le ọmọ. Ọmọ ti ko ti i pe ọdun kan ko gbọdọ jẹ oyin Kokoro aifojuri to ma n fa 'botulism spores' to wọpọ ninu omi, erupẹ, tabi ounjẹ ti wọn ko ṣe daadaa, ma n wa ninu oyin naa. Nitori naa ni o ko gbọdọ fun ọmọ ti ko ti i pe ọdun kan ni oyin.",0,yoruba kí la npe aṣo ti a fi npọnmọn,0,yoruba Nigeria Politics: Àwọn gómìnà lábẹ́ àsíá ẹgbẹ́ PDP tó darapọ̀ mọ́ APC rèé,0,yoruba àwọn ènìyàn ni ó pa Ìyá lo ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba "Ojúmọ́ t'ó mọ́ mi lónìí, ojúmọ́ ire ni kó jẹ́. Ojúmọ́ ayọ̀. Ojúmọ́ ìdùnnú. Ojúmọ́ ọlá. Ojúmọ́ àlàáfíà. Ojúmọ́ ire ni!",0,yoruba Baba Ijesha: Iyabo Ojo àti Nkechi Blessing gbà alàáfíà láàyè,0,yoruba Òòṣà ìyá méjì ní ń bẹ. Òòṣà wo ni ìwọ́ jẹ́ nínú ìyá? #AyajoOjoIya,0,yoruba wáyé. ti A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba "Ìbà Olódùmarè, ọmọ-aṣehun-ribiti kárí ayé. Ìbà okó tó dorí kodò tí kò ṣ'ẹ̀jẹ̀. Ìbà òbò t'ó dorí k'odò tí ò ṣ'omi. Ìbà là á kọ́ọ́ jú. Nítorí bí olú igbó bá jí à júbà igbó, b' ólú ọ̀dàn-án bá jí, à júbà ọ̀dàn. Mo sùn mo jí ire, ǹjẹ́ kí tún ló yẹmí bí kò bá ṣọpẹ́!",0,yoruba nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn aláìì lẹ̀.,0,yoruba RT @user: Ounje ajeju ama muni sanra. E je ka jeun n'iwon. #TweetYoruba,0,yoruba "Bí olóṣèlú ẹgbẹ́ alátakò , àwọn méjèèjì kò ní ẹ̀rí tí ó dájú tí yóò fi ìdí ẹ̀sùn tí ó fi kan ìjọba àná múlẹ̀ .",0,yoruba "gbé mú yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó ṣe pàtàkì. (Item 160),0,yoruba A lè fi ewé arère (òbéṣè) fún aró aláwọ̀ oríṣi mẹ́ta ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀. Ìtàkùn àti ewé arère sì ní èròjà agbógunti-aàrùn lágọ̀ọ́ ara. #Yoruba,0,yoruba "Ṣe ni ọrọ di boolọ, ko ya fun mi ni abule Obada Oko to wa ni agbegbe Ewekoro nipinlẹ Ogun nidaji ọjọ Aiku. Idi ni pe se ni awọn gende agbebọn kan sadede ya wọ ile ijọsin Kerubu ati Serafu kan to wa loju ọna Reluwe, ti wọn si ji olujọsin mẹta gbe lọ. Gẹgẹ bi iwe iroyin Vanguard ti salaye, orukọ awọn eeyan mẹtẹẹta naa ni Ifeoluwa Alani-Bello, Adebare Oduntan and Mary Oliyide. Awọn eeyan yii ni wọn n se iṣọ oru lọwọ saaju isin ọjọ isinmi, tawọn agbebọn si wọle wa gbe wọn lọ. Iroyin naa ni awọn agbebọn ọhun ti n beere miliọnu mẹfa naira lọwọ awọn mọlẹbi awọn eeyan ti wọn ji gbe ọhun, ki wọn to ri idande gba. Nigba to n fidi isẹlẹ naa mulẹ, agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun, Abimbola Oyeyemi ni ileesẹ ọlọpaa ti fi awọn osisẹ rẹ sọwọ si agbegbe naa lati lọ kun awọn ọlọpaa to wa ni ẹkun Obada Oko lọwọ. O fikun pe ileesẹ ọlọpaa naa ti kilọ saaju fun awọn araalu lati dẹkun sise isọ oru ati isin ni awọn agbegbe to ba da. Amọ o ni to ba jẹ dandan ki wọn se isin nibẹ, o yẹ ki iru awọn olujọsin bẹẹ fi to ileesẹ ọlọpaa leti fun ipese aabo to peye le wa fun wọn.",0,yoruba "Jíjí mo jí lónìí, mo jí s'ówó... Ire Ajé á kan gbogbo wa láṣẹ Elédùmarè. #IwureOwuro https://t.co/sPRUEVvKIn",0,yoruba "ìbàdandun àtọ́wọ́dá, àwọn oníṣẹ́ ìṣẹ́ ni a ní nípa ire àti ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì lẹ̀.",0,yoruba Èdùmàrè Adàgbàmápàrọ̀oyè ṣe ìyanu o. Àbí jíjí káa tún jí yìí ni? #ekaaro,0,yoruba ó lè jẹ́ ìdí tí òòṣà aganjú ṣe lókìkí bẹ́ẹ̀ ní àwọn ilẹ̀ náà,0,yoruba Èmi àti ẹ̀yin yóò jí ire lọ́la láṣẹ A-Wí-bẹ́ẹ̀-jẹ́-bẹ́ẹ̀.,0,yoruba "ìwájú lojiji. Bàbá lo ni ìgbà mi owó àkokò, Ọba ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba Aago náà ń ṣàfihàn àkókò àti déètì lọ́wọ́lọ́wọ́,0,yoruba "Àṣà nìlú, àṣà lorin àtijó. Ìgbésẹ̀ rere lèyìí, àkọ́kọ́ irú ẹ̀ sì ni. Ọ̀nà kan gbòógì láti polongo ara wa fáyé rí ni #NigerianDrumsFestival",0,yoruba "Owó tí à ń sọ nì, ló pàpà wọ inú ilé ìkówópamọ́sí àyà ìyá ẹlẹ́ja l'Óṣòdì. Àṣà kíki owó bọ kọ́mú nígbàogbo kìí ṣe nǹkan tó dáa. #Naira",0,yoruba se looto mo ro wipe ikan ninu awon ijo alabode yii ni e n lo o beeni oo°˚˚˚° ọmọ ìjọ kátólíkì,0,yoruba dara gan wey ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò.,0,yoruba Òyó. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ài: ti o nuni ti o nuni ti o dun.,0,yoruba "Irú ewu wo ni eni to dúró tì mí lórí ìlà tí a tò sí láti wọ ọkọ̀ BRT, àbí ṣe mo sì le máa lo si ilé oúnjẹ tàbí ki n máa wọkọ̀ èrò? Bí àwọn ìjọba orílẹ̀-èdè ṣe n sẹ́wélé òfin ìgbélé, tí àwọn ènìyàn si ti ń padà sí àwùjọ fún onírúurú ìbáraeníse pọ̀, ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn ló tí n fòyà lórí bi wọn ò ṣe ni kó ààrùn Coronavirus, èyí to sì lè mú àjàkálẹ̀ ààrùn ẹlẹ́kejì bẹ́ sílẹ̀. Ọ̀jọ̀gbọ́n Erin Bromage to jẹ́ onímọ̀ nípa àwọn èròjà tó ń gbógun ti ààrùn lágọ̀ọ́ ara bá wa sọ̀rọ̀ lórí awon ọ̀nà tí a lè gbà láti mú àdínkù bá ewu kíkó ààrùn Coronavirus, o jẹ́ olùkọ́ ìmọ̀ àjàkálẹ̀ ààrùn ni Fásitì Massachusetts Dartmouth ní US, o sì ti bojú tó ààrùn Coronavirus yìí láti ìgbà to ti bẹ̀rẹ̀. O rí ara rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí onímọ̀ nípa bi a ṣe lè lanilọ́yẹ̀ nípa ǹkan ti sáyẹ́nsì sọ ju kí a pèé ní onímọ̀ nípa ààrùn kan ni pàtó lọ, o tí kọ àwọn ǹkan to pọ̀ nípa Coronavirus lórí ayélujára ti àwọn ènìyàn to le ni mílíọ̀nù mẹ́rindínlógún sì ti kà á ní àkà tún kà. Àwọn ìmọ̀ràn rẹ̀ rèé láti wà ní àlàáfíà bí a ṣe ń padà sí bí a ṣe ń ṣe tẹ́lẹ̀. Bromage ni ọ̀pọ̀ ló ń lùgbàdì ààrùn Covid-19 nínú ilé wọn nítorí ọ̀kan nínú ẹbí wọn tó ní ló pín fún gbogbo ẹbí lẹ́yìn tó ti rí ààrùn naa he nígboro Ṣùgbọ́n bi ènìyàn ba kúrò nínú ilé ńkọ́? Șé ewu àti kó ààrùn Coronavirus wà ti mo bá lo ṣe ère ìdárayá níta pẹ̀lú àwọn tí wọn ò lo ìbòmú? Kò dájú gẹ́gẹ́ bi ọ̀jọ̀gbọ́n náà ṣe sọ. ""Ní ìta gbangba àwọn èròjà míràn wa tí kò ni jẹ́ kí ààrùn naa ràn, ènìyàn máa n mi gúle-gúle sínú àti síta lásìkò eré ìdárayá, àsìkò yìí kéré jọjọ fún kòkòrò yii láti bọ́ sí ọ̀dọ̀ ẹlòmíràn gẹ́gẹ́ bo se sọ fun BBC. "" kí o tó ni ààrùn naa, a jẹ́ pé olúwa rẹ̀ ti koju àwọn kòkòrò tó tó iye èyí tó le fún ènìyàn ni ààrùn náà, pẹ̀lú àwọn ìmọ̀ nípa MERS àti SARS, ìgbàgbọ́ ni pé o gbọ́dọ̀ tó ìwọ̀n ẹgbẹ̀rún kan kòkòrò naa ti yóò wọ àgọ́ ara ki èèyàn to le ni ààrùn naa gẹ́gẹ́ bo se ko sójú òpó ayélujára rẹ̀. Ọ̀jọ̀gbọ́n náà ṣàlàyé pé bótilẹ̀ jẹ́ pé àríyànjiyàn wà lórí iye kòkòrò àìfojúrí tí èèyàn ti fa símú ki o tó ni ààrùn naa, síbẹ̀ ó ṣeéṣe kí o gba èyí láàrin èémí kan tàbí mẹ́wàá, èyíkéyìí le mú ènìyàn ni ààrùn náà. Èyí túmọ̀ sí pé iye àsìkò tí a bá lò pẹ̀lú aláàrùn Covid-19 ni yóò sọ bóyá ènìyàn leè kó ààrùn náà, tí a bá lo àsìkò kúkúrú bí ti àwọn to n sáré lójú pópó, o ṣeéṣe ki a máa ni ààrùn náà kódà bi kò sí àlàfo mítà méjì, nítorí náà, àwọn ti ó yẹ kó kàn wá gbọ̀ngbọ̀n ni àwọn tó ti fàmìhàn Lóòótọ́ ni ikọ́ àti kàtá máa ṣe ìtànkálẹ̀ ààrùn, ṣùgbọ́n o ní bi èyí ṣe lè wáyé. Ikọ́ ẹ̀ẹ̀kan lè gbé àwọn kòkòrò ẹgbẹ̀rún mẹ́ta síta tó sì le rìn ìwọ̀ Mítà ọgọ́rin láàrín wákàtí kan gẹ́gẹ́ bí Bromage ṣe sọ, ọ̀pọ̀ àwọn kòkòrò yìí si ló tóbi to fi je pé ilẹ̀ ni yóò jábọ́ sí, ṣùgbọ́n àwọn mìíràn fúyẹ́ tí won sì le dúró nínú afẹ́fẹ́ tàbí kí wọn fò wọ yàrá. Tí o bá wa jẹ́ pé inú àkàsọ̀ ìgbàlódé ní ó ká ọ mọ́ tí ẹni náà ba wá sín, ìlọ́po mẹ́wàá ni ìṣòro tìrẹ. Tí ènìyàn ba wá sín lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo kòkòrò ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgbọ̀n ni yóò jáde tó sì kéré jọjọ, èyí leè rìn kìlómítà tó lé ní ọ̀ọ́dúrún láàrin wákàtí kan, bí Bromage ṣe sọ. ""Bí eniyan ba wá ni ààrùn náà, àwọn kòkòrò to ń jáde kọjá milionu méjì to sì ni àwọn èròjà ààrùn naa nínú"" ""Nítorí náà, tí o bá n ba ènìyàn sọ̀rọ̀ lọ́wọ́ tí ẹni náà sì sín tàbí wúkọ́ sí ọ lójú, òó ríi bóse rọrùn láti gba kòkòrò bíi ẹgbẹ̀rún kan tí ẹni náà ba tún wa ní ààrùn náà. Tí o ò bá tún wá sí níbẹ̀ lásìkò náà, àwọn kòkòrò àìfojúrí yìí le wà nínú afẹ́fẹ́ fún ìṣẹ́jú péréte ti o sì ṣeéṣe kí o tí fa èyí tó tó sì mú lásìkò péréte náà, tí ààrùn yóò sì wọlé dé. A mọ̀ pé lẹ́yìn ọjọ́ márùn-ún ni ààrùn náà tó máa n fàmìhàn tó bá mú ènìyàn, ṣùgbọ́n ki wọn tó bẹ̀rẹ̀ síní fàmìhàn nkọ́, àwọn míràn kò tilẹ̀ ni fàmìhàn rárá. Èémí wọ́n lásán máa n tí ààrùn Coronavirus jáde sí àyíká. Èémí ẹ̀ẹ̀kan ṣoṣo le tí láàrin àádọ́ta sí ẹgbẹ̀rún márùn-ún kòkòrò naa síta, ṣùgbọ́n kíá lo sábà máa jábọ́ sílẹ̀ Nítorí naa díẹ̀ nínú kòkòrò yii ni a o ríi tobba jáde láti ara èémí gẹ́gẹ́ bi àlàyé rẹ̀ fún BBC. Ní ti èémí ko sí eni tó mọ iye kòkòrò Coronavirus yìí to n jáde lẹ́ẹ̀kan náà, Ṣùgbọ́n Bromage sọ pé ìwé ìgbà dé gbà kan sọ pé ẹnikẹ́ni to bá ní ọ̀fìnkìn, ó máa ń ti kòkòrò mẹ́ta sí ogún jáde láàrín ìṣẹ́jú kan. Bí àlàyé yìí ba wá rí bẹ́ẹ̀, o túmọ̀ sí pé, èèyàn yóò mi èémí naa fún ìṣẹ́jú àádọ́ta láti gba ẹgbẹ̀rún kan kòkòrò náà ti yóò fi ní ààrùn Covid-19 (Atọ́ka ni àlàyé èyí jẹ́). Nítorí náà a o rí pé ko dájú láti kó ààrùn Coronavirus látàrí pé ènìyàn wà nínú ilé kan náà pẹ̀lú ẹni tó ní ààrùn Coronavirus ṣùgbọ́n tí kò fàmì hàn bí ikọ́ àbí kàtá kò na ṣeé. Bromage sọ pé Ọ̀rọ̀ sísọ le ṣe àfikún kòkòrò to jáde bíi mẹ́wàá sí igba láàrin ìṣẹ́jú kan, bákan náà ni ariwo pípa tàbí orin kíkọ leè fi kún iye kòkòrò tó ń jáde sínú afẹ́fẹ́. Àwọn kòkòrò yìí a ma wa láti ibi kọ́lọ́fín ẹ̀dọ̀ fóóró níbi tó jé pé ààrùn náà ti gbilẹ̀ sí nítorí agbára lo fi n jáde nítorí ariwo tí ẹni náà ń pa. ""Fún ìdí èyí gbogbo ǹkan tó bá mú ààrùn Coronavirus jáde sínú afẹ́fẹ́ láti inú ẹ̀dọ̀ fóóró yóò pọ̀ gidigidi, bótilẹ̀ jẹ́ pé kíkó ààrùn yìí nínú afẹ́fẹ́ kò tíì fìdí múlẹ̀ dáadáa síbẹ̀ ìtànkálẹ̀ ààrùn yàtọ̀ sí láti inú ilé máa n wáyé latari àwọn ti kò fàmì hàn. Láì dénà pẹnu àwọn tó n tọ́jú àwọn alárùn yìí ló léwu fún jù. Ṣùgbọ́n àwọn àyíká miran náà tún burú jai, bí àpẹẹrẹ àwọn tó wa nínú ọkọ̀ ojú omi, àwọn tí wọ́n wà nínú ọ́fíìsì kan naa, àwọn ti wọ́n péjọ síbi ìnáwó ìyàwó, ọjọ́ ìbí, ìgbáradì akọrin tàbí ìsìnkú, èyí rí bẹ́ẹ̀ nítorí iye àsìkò ti wọ́n lò pẹ̀lú alárùn náà ni. ""kódà ki wọ́n fi àlà mítà àádọ́ta jìnà sírawọn, ìsun téré tó n kan ẹnìkọ̀ọ̀kan tó láti jẹ́ kí wọ́n ni ààrùn naa, nítorí naa bi a ṣe n padà sẹ́nu iṣẹ́ àwọn ilé iṣẹ́ kan yóò ní láti ṣe àtúnṣe Àwọn ọ́fíìsì ti kò ní ibi tí atẹ́gùn le gbà wọlé léwu gidigidi, Bromage ṣàpèjúwe pé ìdá mẹ́rìnleláàọ́run ninu òjìlénígba o dín mẹ́rin ọ́fíìsì ló ni ààrùn Coronavirus ni orílè èdè South Korea, ọ̀pọ̀ sì jẹ́ àwọn to wà nínú ọ́fíìsì kàn náà tó tẹ́ gbayawu ṣùgbọ́n tí àtẹ̀gùn rẹ̀ kò to ǹkan. Àwọn Dókítà eyín náà wà nínú ewu yìí nítorí irú isẹ́ wọn. Ó ní àwọn olùkọ́ náà yóò wà nínú ewu, àwọn ọ̀jọ̀gbọ́n to ti darúgbó ló pọ̀jù tí wọ́n si ní àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tó kún kíláàsì fọ́fọ́, ìrònú jinlẹ̀ gbọ́dọ̀ wà kí irú àwọn yìí tó padà sẹ́nu isẹ́ fún ìgbé ayé àlàáfíà Bromage ní àwọn to kó ààrùn Coronavirus ní ta ko fi bẹ́ẹ̀ wọ́pọ̀ ṣùgbọ́n àwọn to kóra jọ pò sí inú ibì kan tí won ti ń kọrin, pariwo ló wọ́pọ̀, tí ènìyàn bá ju kòkòrò náà sì àárín ita, afẹ́fẹ́, oòrùn òtútù leè mú àdínkù bá ìtànkálẹ̀ rẹ̀, ẹ̀wẹ̀, ìjìnà sira ẹni àti mímú àdínkù bá ìbáṣpọ̀ elérò yóò rán gbogbo ènìyàn lọ́wọ́ láti fòpin sí ààrùn Coronavirus. Bákan náà ni àwọn ibi tó jẹ́ pé kò fi bẹ́ẹ̀ sí atẹ́gùn, ti àwọn ènìyàn si maa n gba èémí fúnra ẹni ni, yóò nira díẹ̀ láti máà ni ààrùn náà, àwọn ilé ìtajà ìgbàlódé kò fi bẹ́ẹ̀ léwu, nítorí pé àsìkò péréte ni wọn lò ní àyíká kan. Bí a bá fẹ́ lọ sóde, a ní láti ṣe àgbéyẹ̀wò irú afẹ́fẹ́ tí ènìyàn yóò máa gbà sì mú níbẹ̀, iye ènìyàn tó ṣeéṣe kí o bá pàdé níbẹ̀ àti iye àsìkò tí óò lò. To ba jẹ́ ọ́fíìsì gbayawu ni o ti n siṣẹ́ pẹ̀lú àwọn ènìyàn péréte, ewu bíntín ni ṣùgbọ́n ti èrò ba pọ̀ nibẹ̀, o ní láti gbé e yẹ̀wò dáadáa. Tó bá jẹ́ pé isẹ́ tìrẹ gba kí o maa bâ àwọn oníbàrá rẹ sọ̀rọ̀ lójú kojú ni tàbí èyí tó n mú ariwo dání, o léwu fún ọ Tó bá jẹ́ pe kí o lọ rajà lásán láwọn ilé ìtajà ni, níwọ̀ba àsìkò tí o n lò níbẹ̀, ewu rẹ̀ kéré jọjọ, ṣùgbọ́n fún àwọn òṣìṣẹ́ ilé ìtajà náà Ó ṣe pàtàkì ki a maa rántí pe kìí ṣe ṣínsín síni nìkan ni o yẹ ki a máa ṣọ́ra fún, e rántí pé àwọn kòkòrò yìí maa n bàlé àwọn irinsẹ́ tí à ń lò nítorí naa, o se pàtàkì láti máa fọ owọ́ rẹ déédéé kí o si ṣọ́ra láti máa fi owọ́ kan ojú. Bákan náà, e ṣọ́ra fún fífẹ́ àtẹ̀gùn láti paná àbẹ́là lórí àkàrà oyinbo (cakes) ọjọ́ ìbí. Coronavirus ti di ara wa, kò le è kúrò mọ láéláé - WHO Ǹjẹ́ ènìyàn tó ní àrùn coronavirus rí lè níi lẹ́ẹ̀kejì? Ǹjẹ́ ènìyàn tó ní àrùn coronavirus rí lè níi lẹ́ẹ̀kejì? Àwọn àràmọ̀ndà ìbomú-bẹnu tó gbòde lásìkò Coronavirus yìí",0,yoruba jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó wáyé..,0,yoruba ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o nuni ti o nuni ti o nuni ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo.,0,yoruba "Bí ẹ bá ṣe òfin tótó, ẹ ó rí ohun èlò ògbufọ̀ sí èdè mìíràn, bí tinú àwòrán wọ̀nyí. Èyí ni #TweetYoruba dúró fún. Àlàyé ni bàbá ọ̀rọ̀. https://t.co/dCz87OP8N2",0,yoruba "yi gbe ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba pa Ọba lo ni ẹ̀ká àwẹ eyti o gbe lori ọ̀run dídì.,0,yoruba ri pe ṣe iyalẹnu wey ti o dara.,0,yoruba Ọ̀yọ́ jẹ́ ìlú tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ àti ìbi tí wọn wà.,0,yoruba mo júbà gbogbo ẹni tí ń ṣeré ìdárayá nínú òtútù yìí ooo,0,yoruba "Nko ni sai ki awon omoge orekelewa wonyii pelu @user @user Inu mi dun wipe aye ko pare mo loni, nitori tiwon naa ni :-)",0,yoruba "Abẹ́ dídá fún obìnrin sì tún wọ́pọ̀ l'Afirika Ajajagbara fun obinrin kan, Ketcha Pertulla Enzigha sọ pe abẹ dida fun ọmọbinrin si tun wọpọ ni apa ariwa orilẹede Cameroon bo tilẹ jẹ pe ajọ iṣọkan agbaye n ke fawọn eeyan lati dẹkun rẹ. Eleyi lo mu ki ijọba ilẹ Gẹẹsi gbe ọgọta miliọnu o le mẹrin owo dọla silẹ lati fi dẹkun abẹ dida fun ọmọbinrin kaakiri ilẹ adulawọ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí: Ṣe wahala wá ti ọkọ bá kọ̀ láti fún aya tó ti kọ̀ silẹ lára ogún rẹ? Orilẹede Naijiria naa wa lara awọn orilẹede ti yoo jẹ anfani owo iranwọ yii. Ijọba ilẹ Gẹẹsi fẹ ki abẹ dida ko di ohun igbagbe nilẹ Afirika laarin ọdun mejila si asiko yii. Abẹ́ dídá fún obìnrin sì tún wọ́pọ̀ l'Afirika Owo naa tun wa fun didena abẹ dida fun awọn ọmọ ilẹ Gẹẹsi ti wọn ba lọ silẹ okere. Ajọ iṣọkan agbaye sọ pe abẹ dida fun ọmọbinrin le ṣakoba fun oju-ara rẹ, koda o le yi pada. Iwadi ajọ iṣọkan agbaye sọ pe awọn ọmọbinrin to to igba miliọnu ti wọn si wa laaye bayi ni wọn ti dabẹ fun. Gẹgẹ bi Iwadi naa tun ṣe sọ, aṣa abẹ dida yii wọpọ ni bi ọgbọn lorilẹede, ṣugbọn kii ṣe ilẹ adulawọ ni gbogbo wọn wa.",0,yoruba bí a bá ṣe ìkà fún ẹni dúdú,0,yoruba "Mọ lọ sí Ṣọ́ọ̀ṣì o """""""" <ni ohùn Ẹlẹ́jọ̀kà; Elémùré Ògúnyẹmí > https://t.co/GpqRW6SRgs",0,yoruba "igba mi owó àkokò, Ọba ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba nìkan. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó ṣe pàtàkì.,0,yoruba BRINGING BACK THE CLASSICS / A MÚ ÀWỌN ORIN AYÉBÁYÉ PADÀ WÀÁ: Sikiru Àyìndé Barrister - Fuji Garbage 1988 🎶 https://t.co/HN8eaC34eg,0,yoruba "Sylva ni wọn yoo ṣe eyi lọfẹẹ fawọn ọmọ Naijiria lọna ati mu adinku ba owo epo petirolu to gbowo lori. Ori eto kan lori mohunmaworan apapọ ilẹ wa ni Minisita ti kede bẹẹ laarọ ọjọ Aje. Sylvia ni awọn ọkọ ayọkẹlẹ ni wọn ṣe lati maa lo gaasi ati epo petirolu papọ, bẹẹ si ni afẹfẹ gaasi dinwo ju epo petirolu lọ."" Awọn ọmọ Naijiria yoo lanfaani lati yan eyi to ba wu wọn. Ijọba yoo si bẹrẹ eto naa pẹlu awọn kẹkẹ ẹlẹsẹ mẹta nilu Portharcourt."" O fikùn pe ilo afẹfẹ gaasi ba oju ọjọ wa mu ni Naijiria, ti eyi ba si dohun tán, Naijiria yoo ri iranwọ gba lati ilẹ okeere.",0,yoruba "ọlọ́run. Nitori eyi, ara eni lo ni iwa rere lojiji.",0,yoruba awon jegudujera oloselu wonyi ko ni itiju ati eri okan oun lofa bi won se,0,yoruba "Ní oṣù Ẹrẹ́nà ọdún tó kọjá , Nkurunziza gba orúkọ tuntun lọ́dọ̀ àwọn ẹgbẹ́ òṣèlúu rẹ̀ , Àjọ Agbèjà Òmìnira Àwọn Ológun – Fún Ìgbéga Ìjọba Oníbò ( CNDD - FDD ) .",0,yoruba wúlò. ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ àti ìbi tí wọn wà.,0,yoruba "òní.. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì lẹ̀.",0,yoruba dara. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Alàji lo ìgbà ọkọ.,0,yoruba Judy Austin Moghalu: Mo ti 'ùnfollow' ẹ lórí 'social media'; Ọlọ́run a ṣe idajọ fún ẹyin méjèèjì- Iyawo Yul-Edochie,0,yoruba omo tó bá solénù àpò ìyà ló sokó do not stay too from home youll lack a lot asa bbc,0,yoruba "Ọpọ ipinlẹ lo ti se ofin Sharia to tako ọti mimu ni Naijiria Gomina Abdulfatai Ahmed lohun si ofin yii ofin to tako ọti tita ati rira nigboro ilu Ilọrin lọjọ isẹgun lẹyin tile asofin ipinlẹ naa ti buwọlu abadofin ọhun. Labẹ ofin yii, wọn ko ni gba ẹnikẹni laaye lati maa se ọti lile ta tabi maa taa loju taye tabi ki wọn maa mu ọti laarin igboro lawọn agbegbe kan nigboro ilu Ilọrin. Gẹgẹbi ofin naa ti wi, ẹnikẹni to ba tapa si ofin naa yoo san owo itanran ti ko din ni ẹgbẹrun lọna ọgọrun naira tabi ko fi ẹwọn osu mẹfa jura.",0,yoruba pe dara gan wey ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọmọ lo ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba Ń sọ fáìlì tí a óò lò ní pàtó fún ẹ̀yìn àwòrán. Tí àwòrán náà bá ní ṣánẹ́ẹ̀lì alpha a óò tòójọ sórí àwòrán ẹ̀yìn ojú-iṣẹ́.,0,yoruba wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìṣẹ̀: ti o nuni ti o nuni ti o nuni ti o dara.,0,yoruba tí gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọba lo ni ọ̀gbọ́n.,0,yoruba mo júbà ọmọdé mo júbà àgbà ìbà gbogbo sọ̀rọ̀sọ̀rọ̀ tí ń bẹ lórí o ẹ ò ní tẹnu gbó lọ bí ọwọ̀,0,yoruba Ara eni lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "Ọrọ lori esi idibo aarẹ Ohun ti o ku bayii ni ki alaga ajọ Ọjọgbọn Mamood Yakubu kede ẹni to wọle ibo aarẹ ninu Atiku ati aarẹ Muhammadu Buhari. Ẹwẹ, Ọjọgbọn Yakubu kede pe iṣẹ si pọ fawọn lati ṣe lori esi idibo aarẹ ọhun. Lẹyin naa ni alaga ajọ INEC kede pe awọn fẹ lọ simi diẹ, o ni wa yoo tẹsiwaju laago mẹta orun Ọjọru. Ibo aarẹ Ẹwẹ, ẹgbẹ alako PDP ti sọ pe awọn ko ni gba esi idibo ti ajọ INEC kede lati igba ti wọn ti n ka esi ibo naa. Buahari jawe olubori ni awọn ipinlẹ bi Kano, Katsina, Bauchi, Kaduna, Bornu, Yobe pẹlu ibo to pọ yanturu. Bakan naa ni Atiku la Buhari fẹyin Buhari gbo lẹ lawọn ipinlẹ bi Adamawa, Benue, Cross River, Abia ati olu ilu Naijiria Abuja",0,yoruba Ìgbà tí gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ìyá lo mú.,0,yoruba "RT @user: Eledumare, o je o. """"""""""""""""@user: Ẹkú ojúmọ́ o. Ṣálàáfíà ni? Ṣe omi ò yalé o?""""""""""""""""",0,yoruba ìkòkò tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa òkè: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò.,0,yoruba Ọ̀run ló mọ ẹni tí ó là.,0,yoruba lọ. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "Ire wọ́ tọ̀ mí wá. Ire pàdé mi níwá, kò mí lẹ́yìn lọ́dún yìí. Orúkọ tuntun, iyì tuntun, aṣọ tuntun, bàtà tuntun."""""""" #Iwure",0,yoruba "Àkànlò èdè ni """"""""""""""""gbé sàárà kọjáa mọ́ṣáláṣí"""""""""""""""", ó sì 'túmọ̀ sí, ìkọjá-àyè. Kí wá ni ìtumọ̀ """"""""""""""""ta mí lólobo"""""""""""""""" tàbí """"""""""""""""olobo kan ta mí""""""""""""""""? #Ibeere #Yoruba",0,yoruba "Omu kon wunmi mu lataaro ni sha, mio mo why 🥺🥺🥺 #yoruba #sinzumoney",0,yoruba "Iṣẹ́ yóò wà lọ́pọ̀ yanturu l’Ekiti tí mo bá di gómìnà - Adeyinka Ali, olùdíje ẹgbẹ́ APP",0,yoruba ìròyìn. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba "Ó túmọ̀ sí “ bójúmu , """""""" tàbí “ rẹwà , """""""" tí ó súyọ láti fanimó̩ra tí í ṣe gbólóhùn Yorùbá .",0,yoruba "àwọn ìkòkò tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba Àwọn kan ti ń jí ara wọn wò 😊,0,yoruba 13. Òkéjàgbàníyà ni ẹni tí ó kóran nílẹ̀ {tí kò yọ nílẹ̀} Wọ̀bìà ni ẹni tí ń j'àjẹjù {alájẹkì} ______ ni ẹni tí ó wé l'ọ́rùn {awélọ́rùn} #Ibeere #Yoruba,0,yoruba Ọba fi. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba Àṣẹ is amen in Yorùbá #amen #yoruba #yorubaword http://t.co/AInK31uCoF,0,yoruba "RT @user: """"""""""""""""@user @user @user Egbe Oluburela ki Gomina Fashola lo ri iku Pa Fashola, Ajalu nla leyi http://…",0,yoruba olorun yo wo omo naa fun abiyamo aye ko ni gba omo naa ni owo iya e oo amin,0,yoruba Àkójú ọ̀rọ̀ yi kún fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde sí ara ilẹ̀. (Item 115),0,yoruba Mide Funmi-Martins àtí Olamide àbúrò rẹ̀ ti ayé ń bú u lé lórí ti wà papọ̀,0,yoruba ẹ jẹ́ ká ṣe ara wa ní òṣùṣù ọwọ̀ lets unite like the broomsticks ọwọ̀ ni a fi ń gbá ilẹ̀ ni a tún fi ń pè é ní ìgbál,0,yoruba Olódùmarè síjú àánú rẹ bo ìpínlẹ̀ #Kaduna lónìí o. Àti gbogbo Nàìjá lápapọ̀. #,0,yoruba ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tó gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́.,0,yoruba Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó ṣe pàtàkì. (Item 92),0,yoruba Gbé fèrèsé lọ sí ààyè-iṣẹ́ kẹrin,0,yoruba Orin náà ń fi ọ̀wọ̀ wọ agbègbè náà : bí ẹni wípé Agbègbè Papa náà ni oòrùn ní àárín àgbá - ńlá Ijó ìta - gbangba àti ohun tí ó kù ń yí i ká .,0,yoruba "Fún ọjọ́ díẹ̀ , ilé ìjọsìn náà ; # ChurchToo — tí í ṣe àpẹẹrẹ èmi náà ní àgbáyé # MeToo — gba ayélujára kan ní Nàìjíríà .",0,yoruba Àwọn ọmọ náà tí wọn kò ju ọmọ ọdún 15 sí 17 yóò ṣe ẹ̀wọ̀n ọdún márùn - ún bí wọ́n bá jẹ̀bi ẹ̀sùn ìtàbùkù bá Ààrẹ orílẹ̀ - èdè .,0,yoruba _Aládàáṣe,0,yoruba "Gbajugbaja olorin takasufe, Afeez Fashola ti ọpọ eeyan mọ si Naira Marley, ti fesi si ọrọ Pasitọ Chris Omashola to pe ni ẹlẹmi Eṣu. Ojiṣẹ Ọlọrun naa ti sọ tẹlẹ pe, Ọlọrun lo fi iran han oun pe ẹlẹmi Eṣu ni Naira Marley. Ọkunrin kan ti orukọ rẹ n jẹ @omo_billionaire loju opo Twitter, lo bi awọn eeyan leere pe kin ni idajọ lori ọrọ pasitọ Omashola ati Naira Marley. Lẹyin naa ni Naira Marley funra rẹ fi ọrọ kan naa lede loju opo Twitter tiẹ naa. Ṣugbọn orin ni Naira Marley fi fesi si ọrọ yii lẹyin to sọ pe ''Se bi omo jesu niwo, gbese ko Tesumole 🎶.'' Ero ọpọlọpọ awọn ololufẹ Naira Marley lo jọra wọn lori ọrọ naa, n ṣe ni awọn naa fi orin ''Se bi omo jesu niwo, gbese ko Tesumole 🎶'' bọ ẹnu ni idahun wọn si esi Naira Marley. Amọ, ero awọn kan ṣọtọọtọ lori ọrọ naa, fun apẹrẹ, @funshi ni oniyẹyẹ ni pasitọ Omashola, o ni pasitọ naa ko riran pe Fashola Azeez lẹmi Eṣu. Ẹlomiran, @mubaraq_a tun kin ọrọ @funshi lẹyin, o ni Naira Marley nikan ni Ọlọrun fihan ojiṣẹ Ọlọrun naa. Epe rabandẹ lawọn kan tiẹ n fi ranṣẹ si pasitọ Omashola, wọn ni ko mọ ohun to n sọ. Laipẹ yii ni Pasitọ Omashola sọrọ loju opo Twitter rẹ, nibi ti o ti kọ orukọ awọn eeyan to ro pe wọn ko le wọ ijọba ọrun ninu eyi ti Naira Marley wa loke tente. Pasitọ Omoshola fikun ọrọ rẹ pe Naira Marley ni lati ronu piwada ni kiakia ko too pẹ fun un. O ni awọn orin ti Naira Marley n kọ ni imisi Eṣu ninu, eyi to le ṣakoba fun ọjọ iwaju ati ayanmọ awọn ọdọ ni Naijira. Bakan naa ni ojiṣẹ Ọlọrun Omoshola kilọ fawọn ọdọ wi pe, ki wọn ye pe ara wọn ni ''Marlians.''",0,yoruba ọmọ ri pe lẹ ìkòkò wey ti o lẹ.,0,yoruba Ẹ̀bùn ni ó yẹ kí ọbẹ̀ náà jẹ́ fún ẹ̀gbọ́n náà .,0,yoruba "ojú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa aráyé: ti o nuni ti o ní.,0,yoruba "Ẹgbẹ Afenifere kede bẹẹ lasiko to n sọ ero rẹ lori bi ile asoju-sofin se pariwo sita pe si ijọba apapọ ti ta ominira Naijiria fun ilẹ China lati fi ya owo. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Atẹjade kan ti agbẹnusọ fun ẹgbẹ Afenifere, Yinka Odumakin fisita lo sisọ loju ọrọ yii pẹlu afikun pe ominu n kọ awọn ọmọ Naijiria lori igbesẹ ijọba apapọ naa. O ni ""Ilẹ Yoruba ko ni gba ki ajeji kankan wa gba ilẹ rẹ kankan lati fi di owo rara nitori asise ijọba kankan to kundun ko maa ya owo kiri."" Èlé orí owóyàá China rọjú la ṣe fẹ́ gbà á - Ìjọba àpapọ̀ Bi ijọba apapọ ko ba gba owoya mọ, opin de ba isẹ idagbasoke ta n se nu u. Yoruba ni ẹla lọrọ, ti a ko ba laa, kii tete ye ni. Eyi lo mu ki minisita feto irinna lorilẹede yii, Rotimi Amaechi to fi n salaye fawọn ọmọ Naijiria lori idi ti ijọba apapọ se fẹ gba owoya lọwọ ilẹ China. Amaechi, lasiko to n kopa lori eto ori mohun-maworan kan nilu Eko lo sisọ loju ọrọ yii. O ni ""ele ori owoya ti China fẹ gba kere jọjọ si tawọn orilẹede alagbara lagbaye yoku, ni ijọba apapọ se n gbe igbesẹ lati gba a. Bakan naa, awọn ilana ta gba da owoya naa pada ati isunsiwaju akoko to yẹ ki a da owoya naa pada, ko nira rara, a si ri pe owoya ti China fẹ fun wa rọrun."" Minisita feto irinna ni bi ijọba apapọ ko ba gba owqoya ilẹ okeere nitori bawọn eeyan kan se n bu ẹnu atẹ lu, a jẹ pe opin yoo de ba awọn isẹ idagbasoke tijsba apapọ dawọle ni. Eld Kabir in Nigeria: Mùṣùlùmí àti Kristiẹni sọ̀rọ̀ nípa àdun oúnjẹ́ àti ẹran ọdún Ileya Amaechi tun lo anfaani eto naa lati ja ahesọ ọrọ kan to n lọ kiri pe Naijiria ti ta ominira rẹ fun China nitori abala ofin kan to wa ninu iwe adehun ti wọn tọwọbọ lori gbigba owoya naa. ""Abala ilana yii kan wa ninu iwe adehun naa ni lati fidi rẹ mulẹ pe orilẹede Naijiria yoo da owoya naa pada, kii si se pe a fẹ gbe ominira wa le ilẹ China lọwọ. Bẹẹ ba gbagbe, igbimọ ile asoju-sofin to wa fọrọ adehun lo ke gbajare sita lori adehun to wa nidi gbigba owoya lọwọ ilẹ China naa, eyi tijọba apapọ buwọlu. Igbimọ ile naa wa pinnu lati se agbeyẹwo awọn ilana to wa nidi owoya ti Naijiria ti gba sẹyin lọwọ ilẹ China atawọn orilẹede miran lagbaye. Aarẹ laelae bẹrẹ ni China Ọgbẹni Xi patẹwọ lẹyin igba ti igbimọ asofin f'ọwọ si atunṣe naa China ti f'ọwọ si fif'opin si iye saa ti aarẹ orilẹede le ṣe, nibi igbese kan to le je ki Aarẹ Xi Jinping maa se ijọba lọ karin. Ile Igbimọ asofin orilẹede China lo ṣe awọn atunṣe (si iwe-ofin China) to fun aarẹ naa lanfani ati ma ṣe ijọba lọ lọjọ Aiku (Sunday). Asofin 2,964 lo f'ọwọ si atunṣe naa, nigba, ti mẹji tako ti mẹta si kọ lati dibo. Latin nkan bi ogun ọdun sẹyin ni China ti sofin to ni ki aarẹ ma lo ju saa meji lọ lori oye. Sugbọn Ọgbẹni Xi, to yẹ ko sọkalẹ lori oye ni ọdun 2023, o kọ lati s'afihan ẹni ti ole jẹ aarẹ lẹyin rẹ nigba ipade ẹgbẹ Kọmunisti ninu osu kẹwa. Kaka ko se bẹẹ, ofi ẹse ara rẹ rinlẹ lori oye ni nitori wipe ẹgbẹ pinnu lati fi orukọ rẹ ati igbagbọ iselu rẹ sinu iwe-ofin ẹgbẹ oselu naa- eleyi fun ni irufẹ agbega ẹni to da ẹgbẹ naa silẹ, Chairman Mao. Botilẹ jẹ wipe iwe ofin sọ wipe ile igbimọ asofin lo lagbara ju ni China- gẹgẹ bi oti wa ni awọn orilẹede yoku. Sugbọn opọ eeyan nigbagbọ wipe igbimọ naa yoo f'ọ̀wọ si gbogbo nkan ti wọn ba ni ko f'ọwọ si.",0,yoruba Vietnamese (V_PS),0,yoruba "Osere Yoruba, Oyinkansola Elebuibon ti pariwo sita pe ẹlẹsin abalaye ni oun, kii ṣe Musulumi tabi Kristiẹni. Ninu ọrọ kan to kọ si ori ayelujara Instagram rẹ, Elebuibon sọ pe Oriṣa ni oun n sin. ""O ni Olorisa ni mi, ohun naa ni ma a si jẹ ni igba gbogbo."" O ṣalaye pe jijẹ ẹni to n sin Orisa kii ṣe iwa ọdaran, bẹẹ ni kii ṣe ibi, nitori pe inu gbogbo eniyan ni ibi n gbe."" Oyinkansola Elebibon tẹsiwaju ninu ọrọ rẹ pe awọn to jẹ ẹlẹsin ibilẹ, lo jẹ baba ati iya to bi gbogbo ẹsin to ku, ""nitori naa, ẹ jawọ ninu didẹyẹ si awọn ẹlẹsin ibilẹ. Ko tan sibẹ o, o ni ofin gan-an daabo bo ominira ẹsin ati didarapọ mọ ẹgbẹ to ba wu eeyan. Ẹ fi wa silẹ ka sin Orisa wa, ati awọn alaalẹ wa ni ọna to ba wu wa. Ilẹ Yoruba kii ṣe ilẹ Araabu, arọmọdọmọ Orisa ni wa."" Oyinkansola Elebuibon jẹ ọkan lara awọn ọmọ gbajugbaja babalawo, to tun jẹ Araba ilu Osogbo, Oloye Ifayemi Elebuibon. Oṣere tiata Yoruba ni, to si n gbe ni orilẹ-ede America. Yatọ si pe o jẹ oṣere, o tun n ṣe iṣẹ agbohunsafẹfẹ ati oludari eto nibi ayẹyẹ. O kẹkọọ gba iwe ẹri ninu imọ Ọsin ẹranko ati ilera wọn, ni Federal University of Technology, FUTA, nilu Akure, nipinlẹ Ondo. O si tun jẹ Iya Awo, to ma n difa fun awọn eeyan. Laipẹ yii ni iroyin kan sọ pe oṣerekunrin, Lateef Adedimeji, lo bi ọmọ rẹ to bi laipẹ yii fun. Ṣugbọn, o ti sọrọ jade pe irọ̀ patapata ni iroyin naa. Ẹsin ibilẹ tabi abalaye ṣi wa ni awọn ẹbi ati ilu nilẹ Yoruba, bo tilẹ jẹ pe awọn to tẹwọ gba a ko pọ.",0,yoruba Èkó yii nípa ìbadandun ni nfàn ojú kakaaki. Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "August agboola Browne, to jẹ akọrin Jazz, ti gbe ni Poland fun ọdun mẹtadinlogun, ko to o darapọ mọ ikọ Nazi lọdun 1949 - itan sọ pe oun nikan ni alawọ dudu to ṣe bẹ ẹ lorilẹ-ede naa. Ko si ju ẹni ogoji ọdun lọ nigba naa. Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Botilẹ jẹ pe ìdá mẹrindinlọgọrun awọn eeyan to n gbe ni olu ilu Poland nigba naa lo kú, tabi di alainilelori nitori ogun ti Germany gbe ti wọn, amọ ori ko Agboola yọ. Ọdun to kọja ni wọn ri okuta iranti lorukọ Agboola Brownie ni Warsaw O si gbe ni orilẹ-ede naa lẹyin ti ogun pari ni ọdun mẹrindinlọgọrin titi di ọdun 1956, to ko lọ si Britain pẹlu iyawo rẹ keji. Ni olu ilu Poland, Warsaw, wọn ri okuta kekere kan mọlẹ lati ma a fi ṣe iranti Brownie. Ko si akọsilẹ kankan to ṣe e gbamu nipa igbe aye rẹ, yatọ si kekere to wa ninu iwe to kọ lati darapọ mọ ẹgbẹ awọn ajagunfẹhinti lọdun 1949. Ọgọta ọdun ni iwe naa fi wa ni ipamọ titi di ọdun 2009, ti Zbigniew Osinski lati musiọmu Warsaw, ṣe alabapade rẹ. Iwe naa si lo ran awọn olukọtan lọwọ lati ṣe akojọpọ bi igbe aye Agboola ṣe e ṣe ko ri. Akọsilẹ Brownie fihan pe o n pin iwe iroyin fun tita, bakan naa lo tun n ta awọn ohun eelo to n lo ina, to si tun pese ile fun awọn aṣatipo lasiko ogun naa. Ibẹrẹ igbe aye Agboola Brownie: Ilu Eko ni wọn bi Agboola Brownie si ni ọjọ kejilelogun, oṣu Keje, ọdun 1895. Orukọ iya ati baba rẹ ni Wallace ati Jozefina. Ilẹ Gẹẹsi ni Brownie kọkọ de si, ko to o darapọ mọ ẹgbẹ elere ori itage kan nilẹ yuroopu, eyi lo si sọ di ero ilẹ Poland. Ilu Krakow to kọkọ gbe nibẹ lo ti fẹ iyawo rẹ akọkọ, Zofia Pykowna, to bi ọmọkunrin meji fun, Ryszard ati Aleksander. Igbeyawo naa fori ṣanpọn, ṣugbọn lasiko ti ogun naa bẹrẹ, Brownie ṣeto fun awọn ọmọ rẹ ati iya wọn lati lọ ṣe atipo nilẹ England, amọ ko tẹle wọn lọ. 'Eeyan jẹjẹ, ti kii ṣe aṣehan ni Agboola' Tatiana Brownie, ọmọbinrin ti iyawo keji to fẹ, Olga Miechowicz bi fun, ṣi wa laye. Ilu London lo gbe dagba, oun si ni ọmọ rẹ kan ṣoṣo to ku laye. O ti pe ẹni ọdun mejilelọgọta bayii - baba rẹ ku ni ọdun 1976 nigba to wa ni ọmọ ọdun mẹtadinlogun. Nkan to ranti nipa baba rẹ ni pe eeyan jẹẹjẹ ni, to fẹran lati ma a da nikan wa, ti ko si sọ nipa irinajo rẹ nilu Eko tabi Poland fun ọmọ rẹ ri. Tatiana ko mọ idi pato ti awọn obi rẹ ko fi sọ pupọ nipa igbe aye wọn fun. Ṣugbọn o fura pe o ṣe e ṣe ko jẹ nitori ibanujẹ ati iporuru ọkan ti wọn farada, ati oriṣiriṣi iwa ika ti wọn ri. Bakan naa lo sọ pe, baba oun ko figba kankan kọ aṣa Poland silẹ, to fi jẹ pe ede Polish nikan ni wọn n sọ ninu ile wọn. Ọrẹ Brownie kan ti ẹ sọ pe oriṣiriṣi èdè lo gbọ, to si le sọ. Iboji Agboola Brownie niyi, nibi ti wọn sin si nilu London nigba to ku lẹni ọdun 81 lọdun 1976 Ọdun 2009 ni iroyin nipa Brownie jade si gbangba lasiko ti ija ẹlẹyamẹya kan waye ni Poland. Ohun lo si mu ki ọpọ eeyan polongo fun fifi nkankan ṣe iranti rẹ, ti wọn si tun pe e ni akọni fun orilẹ-ede naa. Aarẹ nigba naa, Lech Kaczynski gbero lati da Agboola lọla nigba to pe ẹni ọdun marundinlaadọrin ti ogun naa pari, ṣugbọn ijamba baalu to mu ẹmi rẹ lọ ba ero naa jẹ. Ọdun to kọja ni ajọ aladani kan ṣẹṣẹ ṣe okuta iranti fun. Iṣẹ orin kikọ ni Brownie ṣe nigba to pada si England, to si gbe igbe aye jẹlẹnkẹ fun ogun ọdun to gbẹyin aye rẹ.",0,yoruba nìkan. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "Ní ọjọ́ 12 oṣù Èrèlé , àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ilé ẹ̀kọ́ gíga , akẹ́kọ̀ọ́ ìmọ̀ iṣẹ́ ìròyìn , ọ̀jẹ̀ sọ̀rọ̀sọ̀rọ̀ àti àwọn alẹ́nulọ́rọ̀ nínú iṣẹ́ ìròyìn àti àwọn olólùfẹ́ẹ̀ rédíò péjúpésẹ̀ sí Lekki Coliseum ní Èkó fún àpérò láti jíròrò nípa pàtàkìi ẹ̀rọ - ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ fún ìdàgbàsókè .",0,yoruba dara. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Alàji lo aye àìlẹ̀.,0,yoruba "Ó yá ẹ̀yin tèmi. Ẹ jẹ́ ká yá ara wa lọ́gbọ́n, ìmọ̀ àti òye. #ibeere #Yoruba",0,yoruba "Ìpínlẹ̀ Ọ̀sun, Ògùn, Ọ̀yọ́, Èkìtì, Èkó, Òndó àti Kwara ma ń dá ojú abẹ́ fún obìnrin ní àṣà wọn, kí ìjọba GEJ tó f'òpin si ní 2015. Èkó ló ní ipa tó kéré jù nínú àṣà yìí. Ọ̀sun ló kópa jù nínú dídá ojú abẹ́ fún obìnrin.",0,yoruba "RT @user: """"""""""""""""@user @user ORO ABO IPINLE EKO: Ipinle Eko fi ofin de wi wa omolanke loju popo oni gere http://t.co/n…",0,yoruba Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba Ẹ wi fun Twita @user ki o dakun dabọ gbọ ti ọmọ yoruba o ;). #twitterYoruba #TweetYoruba #Yoruba @user,0,yoruba "Who read this before? """"""""""""""""""""""""""""""""In-depth Yoruba Phonology and Grammar"""""""""""""""""""""""""""""""" 😁 Ìwé pàtàkì fún ẹni tí ó fẹ́ kọ́ gírámà èdè Yorùbá fún sísọ pẹ̀lú kíkọ tó já geere. #IjinleFonolojiAtiGiramaEdeYoruba #Atelewo #Yoruba #YorubaBooks https://t.co/ZHokiFuP4B",0,yoruba Ìjọ Kátólíkì bẹ̀rẹ̀ ìwáàdì lẹ̀yìn tí àwọn sisitá méjì lóyún ójijì,0,yoruba "Ọlọ́run Àìkú o pè mí láláàyè, modúpé o, ìyìn yẹ Ọ́, Ọlọ́run Ọba.",0,yoruba "Bẹẹ ba gbagbe, gbajumọ sọrọsọrọ lori ayelujara, Tokunbo Aboderin, ti ọpọ eeyan mọ si ESABOD lo ba wọn pari ija naa lọjọ Isẹgun. Amọ ni irọlẹ Ọjọbọ ni Toyin tun n wi lele pe, oun ko lọwọ tabi mọ ohunkohun nipa bi ẹnikẹni to ba ni oun n gbeja oun, se n bu ẹnikẹni. Toyin ni ki wọn mase di ẹbi kankan ru oun ti ẹni to n gbeja oun ba n sepe tabi se ẹẹkẹ eebu. ""Mo ri awọn fidio kan lori ayelujara ninu eyi ti awọn eeyan kan ti wọn ni awọn n gbeja mi ti n sẹ epe fawọn eeyan miran. Bakan naa, ni wọn si tun n fa awọn ọmọde ti ko ni ẹsẹ lọrun sinu wahala ti wọn n da silẹ. Ẹ jọwọ n ko fara mọ iru iwa yi ni ọnakọna. Koda, n ko fi igba kankan ran yin ni iru isẹ bayii ri, ẹ jọwọ, ẹ yọ awọn ọmọde kuro ninu ere itage tẹ n se."" Toyin Abraham tẹsiwaju pe, awọn ọmọde naa yoo dagba, amọ gbogbo hun ti wọn ti sọ nipa wọn ni yoo si wa lori ayelujara, ti ko si le lọ sokun igbagbe laelae. O fikun pe oun mọ riri ifẹ ati itara awọn eeyan nipa oun amọ ko si awijare kankan lati maa ba ọja ẹlomiran jẹ. Wùnmí Toríọlá: Toyin Abraham kìí se ọ̀gá mi nínú tíátà Toyin ni oun fura pe awọn eeyan kan n ri jẹ nidi mọdaru to n waye loore koore naa, nitori fidio ti oun sẹsẹ wo tan fidi eyi mulẹ. ""Mo ri fidio kan tawọn eeyan kan ti n sẹ epe fun awọn alabasisẹpọ mi kan lagbo tiata atawọn ọmọ wọn. Eyi ko se dandan, iwa ibi si ni pẹlu, ọna ati jẹ si ni wọn se n bu epo eebo si ere oitage to n lọ lọwọ naa, eyi to ti toju su ni."" Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Toyin wa n ke si awọn eeyan ti wọn ba ti sọrọ odi si lori ayelujara, pe ki wọn fa ọrọ naa de ibi to lapẹrẹ, ki ẹni to sọrọ odi si wọn naa si sanwo gba ma binu. King Sunny Ade's son: Ohùn orin bàbá mi nìkan kọ ni l’Ọlọrun fún mi, ijó bíi kòkòrò ni ṣáá ""Ohun ti mo gbero lati maa se ree lati akoko yii lọ, igba ikẹyin si ree ti maa gbe iru ikede yii sita. Ohun to wa lọkan mi bayi ni bi sinima mi tuntun yoo se jade, mo dupẹ, ẹ se pupọ.",0,yoruba Àbẹ́òkúta. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó ṣe pàtàkì.,0,yoruba ojú òní.. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó ga.,0,yoruba ẹ̀kó. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó ṣe pàtàkì.,0,yoruba ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o nuni ti o jare.,0,yoruba "Wọ́n lá ò gbọdọ̀ gbé irun wa to rẹwà jáde sí gbangba. K'á tó ṣ'ẹ́jú pẹ́kẹ́n, wọ́n ti ṣe ayédèrú irun àtọwọ́dá tó jọ ti wa #AwaLaNiIrun",0,yoruba "Obìnrin kì í dàgbà jù lọ́wọ́ ọkọ rẹ̀; bí eyín bá ku méjì lẹ́nu ìyá, ọmọge ni lójú baba. / A woman is never too old to her husband; even if she's lost all her teeth, a maiden she remains to her man. [Love is it; with love, other concerns pale.] #Yoruba #proverb @user",0,yoruba "Àìmọ́ ni ó pa Ìyá lo ojú odò. ìgbà àkerekere. Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba Ìyá se. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí.,0,yoruba "Ajọ eleto idibo Naijiria, INEC, ti ni inu oun bajẹ bi awọn eeyan kan ṣe n dana sun ọọfisi oun, paapaa eyii to waype kẹyin niluu Enugu. Akọwe ajọ naa, Rotimi Oyekanmi, sọ ninu ifọrọwerọ kan pẹlu ileeṣẹ iroyin abẹle Punch pe o ye ki awọn ọmọ Naijiria daab bo dukia ajọ naa fun anfani ara wọn. Oyekanmi rawọ ẹbẹ yii lẹyin ti awọn eeyan kan dana sun ọọfisi ajọ naa to wa ni ijọba ibilẹ Ariwa Igboeze, ni ipinlẹ Enugu. Iṣẹlẹ naa to waye lalẹ ọjọ Aiku ni iroyin ni o ba ọọfisi naa jẹ, to fi mọ awọn oun elo to ṣe pataki ti wọn n lo ni ọọfisi ajọ naa. Ọga agba to n ri si ọrọ iroyin ati itaniji ni INEC, Festus Okoye sọ pe awọn afurasi naa bori awọn ẹṣọ alaabo to n sọ ọọfisi naa, ti wọn si wọle sibẹ lati sọ ina si ọọfisi ọhun. Okoye ni bo tilẹ jẹ pe ko si ẹnikẹni to ba iṣẹlẹ naa lọ, apoti idibo 748, ati apoti ti awọn oludibo ti maa n tẹ ika 240 ni wọn ko lọ, to fi mọ awọn ohun elo mii ti ina jo. O ni “Ajọ naa n gbiyanju lati mọ irufẹ ipo ti ẹrọ ti wọn fi n ṣe iforukọsilẹ oludibo wa, atawọn kaadi idibo ti awọn eeyan ko tii gba ti a ko pamọ sinu apoti ti ina ko le jo.” Nigba to n sọrọ lori iṣẹlẹ naa, alukoro ileẹsẹ ọlọpaa Enugu, Daniel Ndukwe ni awọn ti bẹrẹ iwadii. Ẹwẹ, INEC ti sọ pe awọn ọta ijọba awarawa lo wa nidi ikọlu ọhun. Akọwe ajọ naa, Rotimi Oyekanmi, ni “Ikọlu lemọ-lemọ ti awọn kan n ṣe si ̣ọọfisi INEC n kọ wa lominu, paapaa eyii ti wọn ṣe si ipinlẹ Enugu yii.” “A ti fi ọrọ naa to awọn ọlọpaa leti, a si gbagbọ pe wọn yoo ṣe iṣẹ wọn bii iṣẹ” “Amọ ako ni jẹ ki awọn ikọlu naa di wa lọwọ lati ṣiṣẹ wa ni igbaradi fun eto idibo gbogbogbo ti yoo waye lọdun 2023.",0,yoruba "Kò kan ẹnikéni bóyá èèyàn féràn àjọyọ̀ tàbí kò fẹ́ , kí ni ó dé tí àwọn ènìyàn ṣe fẹ́ràn láti máa fi túláàsì mú ẹlòmíràn gba èròńgbà ti wọn ?",0,yoruba "Pápáa Queen's Park Savannah , ibi tí ó ní ewéko bíi kàá - sí - nǹkan ní àárín gbùngbùn olú ìlú Trinidad , ni ibi tí ayẹyẹ Ijó ìta - gbangba àti ilé ìtàgé àjọ̀dún náà .",0,yoruba "Bring back our girls: Obi àwọn ọmọ Chibok 34 ló kú ní ọdún márùn ún Awọn to le ni ọgọrun un lo ṣi wa ni panpẹ awọn ikọ Boko Haram lẹyin ti wọn ji wọn gbe ninu ile iwe wọn lọdun 2014. Awọn obi awọn ọmọ Chibok lasiko ti wọn n ba Adaobi Tricia Nwaubani sọrọ ni ọrọ awọn kii se oju lasan mọ ni awọn se gba ọdọ Pasito ati Woli T.B. Joshua lọ lati ba wọn sawari awọn ọmọ wọn to wa ni panpẹ. Òní ni àyájọ́ ọdún karùn ún tí Boko Haram jí àwọn ọmọ náà gbé ní ilẹ́ ìwé wọn, tí 100 nínú wọn sí ti di àwátì. Parental Guidance: Ọdún méjì ni kí ẹ ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ọmọ nípa ìbálòpọ̀ Alaga ẹgbẹ awọn obi awọn ọmọ ile iwe Chibok, Yakubu Nkeki ni ibanujẹ ati ẹdun ọkan lo jẹ fun awọn nitori lẹyin ọdun marun un, ọgọrun un awọn ọmọ naa lo si wa ni panpẹ Ni eyi ti lara awọn mọlẹbi awọn ọmọ wọnyii si ti ku nipase iku ojiji, ijamba ọkọ, aisan ati ikọlu awọn Boko Haram si awọn agbeegbe wọn. Parental Guidance: Ọdún méjì ni kí ẹ ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ọmọ nípa ìbálòpọ̀ Òní ni àyájọ́ ọdún karùn ún tí Boko Haram jí àwọn ọmọ náà gbé ní ilẹ́ ìwé wọn, tí 100 nínú wọn sí ti di àwátì. Arakunrin Nkeki ni awọn obi mẹrinlelọgbọn lo ti papoda lati igba ti ikọ Boko Haram ti ji awọn ọmọ wọn gbe si isinyii. O fikun un pe ija ati asọ lo maa n waye lọjọọjọ ipade awọn obi naa, eleyii ti ko jẹ ki wọn fi imọ sọkan. Eyi lo mu ki wọn gba ile ijọsin T.B Joshua lo ni ilu Eko lati beere iranwọ lọdọ Ọlọrun. Kíni ìdí tí àwọn ẹbí àwọn ọmọ Chibok fi ń tọ woli lọ? Alaga ẹgbẹ awọn obi awọn ọmọ ile iwe Chibok fikun un wi pe ipa awọn ti pi. Bakan naa ni ijọba ti gbiyanju amọ ko tii si ọna abayo, amọ awọn gba Ọlọrun gbọ nitori yoo gbọ adura awọn ati wi pe awọn ọmọ naa yoo pada wale layọ ati alaafia. JAMB 2019: A ó fagi lé ìdànwò ẹni tó bá ṣe aṣemáṣe Lara awọn to lo si ilu Eko fun adura lọdọ pasitọ T.B. Joshua ni alagbatọ Leah Sharibu to jẹ ọmọ ọdun mẹrinla to wa ni panpẹ Boko Haram lati oṣu keji, ọdun to kọja lasiko ti wọn ji eniyan to ju ọgọrun un gbe lo nile iwe rẹ ni ilu Dapchi, ni ipinlẹ Yobe. Kíni ìdí tí àwọn ẹbí àwọn ọmọ Chibok fi ń tọ woli lọ? Awọn ikọ Boko Haram ko lati fi Leah Sharibu silẹ lẹyin ti wọn yọnda awọn iyoku rẹ nitori ọmọ naa kọ lati fi ẹsin Kristẹni silẹ fun ẹsin musulumi ki wọn le tu silẹ lahamọ. Bring back our girls: Obi àwọn ọmọ Chibok 34 ló kú ní ọdún márùn ún Lasiko ayajọ ọdun karun un awọn ọmọ Chibok naa ni ijọba Aarẹ Muhammadu Buhari ṣalaye pe oun n sa ipa rẹ lati rii wi pe awọn to wa ni panpẹ Boko Haram naa gba itusilẹ laipẹ. Wo bí o ṣe lè kọ́ ọmọ rẹ lẹ́kọ̀ọ́ ìbálòpọ̀ Ọ̀dọ́kùnrin tó kọ́kọ́ ṣe ẹ̀rọ tó ń tu ìyẹ́ lára adìyẹ Obi àwọn ọmọdebinrin Chibok ṣi ni igbagbọ ninu Olọrun pe lọjọ kan ni awọn yoo foju kan awọn ọmọ awọn ti wọn jẹ mejilelaadọfa (112) laipẹ. Ko pẹ lẹyin ti wọn ji awọn ọmọ yii gbe ni awọn obinrin kan ko ara wọn jọ pẹlu akọle ""ẹ da ọmọbinrin wa pada: Bring back our girls). Bí o ṣe lè fí òǹkà, ọ̀mọ̀ ìka tàbí ìkúùkù wọn oúnjẹ́",0,yoruba "Alabojuto gbogbogbo fun ijọ Redeemed Christian Church of God, RCCG, Pasitọ Enoch Adeboye ti sọ pe owo Naira yoo si tun pada niyi lawujọ awọn owo orilẹ-ede to gbe pẹẹli julọ lagbaye. Adeboye lo sọ ọrọ naa laarọ ọjọ Abamẹta nibi ipade adura Holy Ghost Congress to maa n waye lọdọdun ni Olu ijọ naa to wa lọna marosẹ Eko si Ibadan. Ẹni ọdun mejidinlaadọrin ọhun gbadura pe ki Ọlọrun da si eto iṣuna Naijiria, ko si tun yi ọkan awọn alaṣẹ to n mọọmọ ṣe awọn eto to n pa owo Naira lara pada. Adeboye sọ itan kan fun awọn eeyan to wa nibi ipade adura naa pe, ni ọpọ ọdun ṣeyin, oun nilo ẹgbẹrun marun un naira pere lẹyin ti oun pe ọpọ ero sibi ipade adura pẹlu ileri pe oun yoo gbọ bukata jijẹ ati mimu wọn. Bo tilẹ jẹ pe ko ni owo naa lọwọ, o ni Ọlọrun pese owo ọhun lọna iyanu. Pasitọ naa ni ""owo Naira niye lori lọdun naa lọhun, yoo si tun niye lori lẹẹkan sii."" ""Gbogbo awọn to n mọọmọ rẹ owo naira silẹ, Ọlọrun yoo da si ọrọ wọn ki ilẹ ọla to mọ."" Ọpọ ọmọ Naijiria to ti n lọgun pe owo naira ko niyi mọ lati nkan bi ọdun diẹ sẹyin, paapaa lẹyin ti owo dollar kan parada di ẹẹdẹgbẹta naira. Awọn to maa n ṣẹ owo ilẹ okere, Bureau De Change, sọ pe idi ti owo naira ṣe n lọ soke silẹ ko ṣẹyin awọn eeyan kan. Ẹwẹ, banki apapọ Naijiria, CBN, ni owo dollar kan ko to irinwo naira, gẹgẹ bi iṣiro to wa loju opo wọn lori ayelujara. Gomina ipinlẹ Edo, Godwin Obaseki ti ṣalaye pe, oludari ijọ Redeemed Christian Church of God, Enoch Adeboye gbadura foun, o si tun sọ asọtẹlẹ pe oun yoo wọle ibo gomina ipinlẹ Edo fun saa keji. Gomina Obaseki sọrọ yii lasiko to n jẹri nibi akanṣe eto ọlọdọọdun ijọ Redeem, RCCG Holy Ghost Congress ti ọdun 2020 yii lọjọ Ẹti. Obaseki ni ''nigba ti ogun gbona giri giri, emi ati iyawo mi ṣabẹwo si Daddy G.O. ni ipagọ ijọ Redeem to wa lopopona ilu Eko si Ibadan. ''Lẹyin ti mo ṣalaye ipenija mi lagbo oṣelu tan, pasitọ Adeboye sọ pe ''ọmọ mi, ma foya, iwọ ni yoo bori, wa si wọle ibo gomina lẹẹkeji,'' Obaseki lo sọ bẹẹ. Gomina ni oun pada lọ ri alufaa Adeboye nigba ti idibo gomina ọhun ku diẹ, o si tun sọ foun pe gbogbo rẹ maa dara lẹyin ''to gbadura fun mi tan.'' Ẹgbẹ oṣelu APC lo gbe Obaseki wọle fun saa kinni gẹgẹ bi gomina ipinlẹ Edo. Ṣugbọn ẹgbẹ APC ko fun un lanfaani lati jẹ oludije ẹgbẹ ọhun ninu idibo ọdun 2020, lẹyin rogbodiyan to ṣẹlẹ pẹlu alaga gbogbo-gboo ẹgbẹ oṣelu naa tẹlẹ, Adam Oshiomole. Pasitọ Osagie Eze-Iyamu ni APC fun lanfaani lati dije fun ipo gomina, labẹ asia ẹgbẹ oṣelu naa dipo Obaseki. Eyi lo mu ki Obaseki lọ sinu ẹgbẹ oṣelu PDP, nibi to wọle ibo gomina ipinlẹ lẹẹkeji.",0,yoruba Ǹjẹ́ẹ̀wọ́ mọ̀ pé Ẹ̀gbá pín sí ìṣọ̀rí-ìsọ̀rí? Apá kan ni Ẹ̀gbá-Owódé; Ẹ̀gbá-Imọ́; Ẹ̀gbá-Ìgbèìn; Ẹ̀gbá-Ìgbórè. 1842 l'Ẹ̀gbáa Sàró dé. #Yoruba,0,yoruba àṣẹ ni ti oyin àlááfíà fún,0,yoruba "Oni, ọjọ kejidinlọgbọn, oṣu Kẹsan-an, ọdun 2022, ni eto ipolongo ibo fun awọn ẹgbẹ osẹlu bẹrẹ, ni imurasilẹ fun idibo gbogbo gbo ọdun 2023. Ipolongo ibo naa yoo waye fun oṣu maarun-un gbako titi si oṣu Keji ọdun 2023, ti idibo yoo waye. Igba akọkọ niyii ti eto ipolongo ṣaaju ọjọ idibo, wọ oṣu maarun-un ninu itan idibo ni Naijiria. Ṣaaju asiko yii, kii ju bi oṣu mẹta lọ. Bi oludije kọọkan ati ẹgbẹ oṣelu wọn yoo ṣe ma a lọ kaakiri lati fa awọn oludibo loju mọra, ajọ INEC ti fi awọn ilana ti wọn gbọdọ tẹle sita. Awọn ilana ati ofin naa ko yọ awọn alatilẹyin wọn naa silẹ. Awọn ilana naa lo wa ni ibamu pẹlu ofin idibo ọdun 2022. Bẹrẹ lati ọjọ kejidinlọgbọn oṣu kẹsan an ọdun 2022, awọn ẹgbẹ oṣelu at’awọn ololufẹ wọn yoo lanfani ati bẹrẹ ipolongo ita gbangba fun idibo to n bọ lọdun 2023 lorilẹede Naijiria. Lati le rii daju pe gbogbo nnkan lọ ni mẹlọmẹlọ, ajọ eleto idibo lorilẹede Naijiria, INEC ti ṣalaye gbogbo ofin makan ti awọn oludije, ẹgbẹ oṣelu won, at’awọn ololufẹ wọn gbodo tẹle. Igba akọkọ si niyi latigba ti Naijiria ti n seto idibo, ti wọn yoo maa la aadọjọ ọjọ tabi oṣu marun un silẹ fun ipolongo ibo ni ibamu pẹlu abala kẹrinlelaadọrun iwe ofin idibo tọdu. 2022. Abala yii tun laa kalẹ pe gbogbo eto ipolongo gbọdọ pari nigba to ba ku wakati mẹrinlelogun si ọjọ ibo gangan. Abala naa ṣalaye pe ẹgbẹ oṣelu tabi ololufẹ rẹ yoowu to ba dagunla gbedeke wakati mẹrinlelogun si ọjọ yiilati dẹkun ipolongo ibo wọn yoo san owo itanranto to ẹgbẹrun lọna ẹdẹgbẹta naira. Bo ba si jẹ ileeṣẹ iroyin lo tapa si ofin yii, miliọnu kan naira lowo itanran rẹ Yatọ si ofin to de akoko ipolongo, ki lawọn ohun miran to yẹ k’awọn eeyan mọ niyii. Ko gbọdọ ṣi ọrọ alufansa tabi eebu gẹgẹ bi abala ikejilelogun iwe ofin idiboNaiiria tọdun 2022 ṣe sọ. Ko gbọdọ si ilo ọrọ to lee fa wahala, rukerudo tabi yanponyanri lasiko ipolongo ibo naa. Awọn agbegbe kan wa ti ofin ko tilẹ fi aye rẹ silẹ fun ẹnikẹni lati ṣe ipolongo idibo tabi ipade ipolongo ita gbangba. Ipin kẹta abala kẹtalelaadorun iwe ofin idibo Naijiria ṣalaye pe tokan sí awọn agbegbe naa gẹgẹ bí ile ijọsin, agọ ọlọpaa atawon ọfiisi ijọba gbogbo. Gbogbo ẹgbẹ oṣelu lo lẹtọ lati seto ipolongo ibo Ofin naa fun gbogbo ẹgbẹ oṣelu at’awọn oludije wọn ni anfani lati seto ipongo nigbakugba to ba wu wọn. O lodi si ofin idibo Naijiria fun ẹnikẹni tabi ẹgbẹkẹgbẹ lati kọlu ẹgbẹ oṣelu kankan tabi eto ati ilana ti wọn sinmi le. Nitori eyi, ko gbọdọ si ẹgbẹ oṣelu tabi oludije kankan to gbọdọ lo egungun fun ipolongo idibo. Bakanna lo tako ofin lati ko awọn agbero tabi januku jọ lati kọ wọn, tabi ko ohun ija oloro le wọn lọwọ nitori oṣelu. Awọn alamojuto ibo ni agbekalẹ ijiya to yẹ fun ẹgbẹ oṣelu yoowu tabi oludije yoowu to ba tẹ oju ofin mọlẹ nipa did awọn miran lọwọ siseto ipolongo wọn nirọwọrọsẹ. Owo itanran milionu kan naira tabi fi ẹwọn oṣu mejila oludije to ba ṣe eyi yoo fi jora. Bo ba si jẹ ẹgbẹ oseluni, miliọnu meji naira ni fun igba akọkọ, milionu kan naira ni yoo maa san lẹyin eyi. Bo ba si jẹ pe nṣe lonitọhun n ṣe agbodegba fun iwa itapasofin yii, ẹẹdẹg ẹta ẹgbẹrun naira ni yoo fi jora tabi ẹwọn ọdun meta tabi mejeeji gan. Bi o ba lo iwa ipalati fi mu ki eeyan kan ti ẹgbẹ oṣelu kan lẹyin, ẹsẹ nla leyi labẹ ofin idibo Naijiria, bi o ba jẹ oludije kan ni tabi ọpọ eeyan ni, miliọnu kan naira ni ọwọ itanran wọn. Bi o ba wa jẹ egbe oṣelu lo ṣe eyi, miliọnu meji naira ni owo itanran rẹ, bi won ba si tun sẹ ẹṣẹ yii, okare Ọrọ abo jeyo labẹ iwe ofin idibo Naijiria, ọdun 2022. Gbogbo ẹgbẹ oṣelu lo l’asẹ ati ẹtọ si abo agbofin. Bẹẹni awọn kọmiṣọna olopaa fun ipinlẹ kọọkan ati olu iLu Nàìjíríà lo sí gbọdọ fun won. Ipin keji abala ofin naa sọ pe agbofinro ti wọn ko ba ran lọ si ibudo ipolongo ibi ko gbọdọ si ni sakani ibẹ. Bakanna ni ipin kẹta abala kọkanlelaadọrun iwe ofin idibo Naijiria tun fa awọn ọlọpaa at’awọn agbofinro yoku leti pe, bi o ti wu ki agbara ti awọn abala iwe ofin mirqn fun wọn ṣe le pọ to, ojuṣe kan ṣoṣo tí wọn ni nibudo ipolongo  ni kiwon o mojuto alaafia nibẹ. Ko si oludije tabi ẹgbẹ oṣelu to laṣẹ lati lo dukua ilu – ninu eyi ti ileeṣẹ iroyin wa, fun anfani ara rẹ laifun awọn oludije miran niru a fani bẹẹ. Gbogbo awon ileesẹ iroyin ti ijọba ati aladani gbọdọ ya iye akoko tabi aye kan naa si ọtọ fun gbogbo oludije tabi ẹgbẹ oṣelu niwọn igba ti wọn ba ti san owo to yẹ ki wọn san. Bi ileeṣẹ iroyin kan ba tapa si ofin yii, owo itanran miliọnu meji ni yoo san fun ìgbà àkọkọ. To ba run tapa si ofin tii lẹyin eyi, miliọnu marun un naira ni yoo maa san. Awọn lọgalọga nileese iroyin bẹẹ yoo si tun fi miliọnu kan nairan owo itanran jura tabi ẹwọn oṣu mẹfa. Lakotan, ofin yii ko fi aye silẹ fun ẹnikẹni tabi ẹgbẹ oṣelu kankan lati fi ẹsin, ẹya tabi ohun ẹya kan polongo tako ẹgbẹ oṣelu kankan. Bi o ba jẹ eeyan kan lo rufin yii, owo itanran miliọnu kan naira ni tabi ẹwọn oṣu mejila, o si lee fi mejeeji jora.",0,yoruba àkókò kò dúró de ẹnìkan time waits for no one make hay while the sun shines promptly exploit opportunities,0,yoruba kan. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa aráyé: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa òkè: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde.,0,yoruba "Ifẹsẹwọnsẹ ọlọọrẹsọọrẹ to waye laarin ikọ agbabọọlu Naijiria ati Brazil lo pari si ọmi. Ikọ Supper Eagles Nigeria lo kọkọ sọ bọọlu sinu awọn ilẹ Brazil, nigba ti Joe Aribo to n gba bọọlu fun Glasgow Rangers nilẹ Gẹẹsi ṣo ayo kan wọle, ni igabti idije naa wọ iṣẹju marundinlogoji. Sugbọn lẹyin ọpọlọ akitiyan ninu abala keji idije ọhun ni ikọ Brazil da bọọlu naa pada si awọn ikọ Naijiria, ni igba ti Casemiro to n gba bọọlu fun ikọ Real Madrid sọ ayo tiẹ wọle. Ọmi ti wọn ta yii tunmọ si pe, ikọ ilẹ Brazil ti kuna lati bori ninu idije mẹrin ti wọn ti gba sẹyin. Ẹgbẹ agbabọọlu Naijiria, Super Eagles ti ṣetan lati gbena woju ikọ agbabọọlu ilẹ Brazil lọjọ Aiku lorilẹede Singapore. Ikọ agbabọọlu Brazil ti kọkọ ta ọmi alayo kọọkan pẹlu Senegal l'Ọjọ ọsẹ to lọ nibu ifẹsẹwọnsẹ ọlọọrẹsọọrẹ. Ọdun 2003 ni Naijiria ati Brazil jọ koju ara wọn kẹyin ninu ere bọọlu ọlọọrẹsọọrẹ. Ni papa iṣere orilẹede Naijiria to wa l'Abuja ni Brazil ti lu Super Eagles lalu bolẹ pẹlu ami ayo mẹta sodo. Akọnimọọgba Supe Eagles Gernot Rohr ti sọ pe ẹgbẹ agbabọọlu Naijiria ti ṣetan lati jẹwọ ara wọn fun Brazil ninu ere bọọlu lorilẹede Singapore. Bakan naa, minisita fun ere idaraya ati idagbasoke ọrọọdun, Sundare Dare ni awọn agbabọọlu Naijiria fi da oun loju pe didun lọsan yoo so fun Naijiria ninu ifẹsẹwọnsẹ pẹlu Brazil. Minisita ṣalaye pe bo tilẹ jẹ wi pe ifẹsẹwọnsẹ ọlọọrẹsọọrẹ ni, awọn agbabọọlu Naijiria yoo fi taratara sii.",0,yoruba "Eyi ni ibeere to gba ẹnu ọpọ awọn eeyan to gbọ si iṣẹlẹ buruku naa eyi to waye lọjọbọ ọjọ kẹrindinlọgbọn oṣu kọkanla ọdun 2020. Iroyin ti a n gbọ ni pe olukọ naa ti wọn pe orukọ rẹ ni Ọgbẹni Emma ti fi ẹsẹ fẹ, awọn alaṣẹ ipinlẹ Eko ṣi n wa a titi di bi a ṣe n sọrọ yii. Ọgbẹni Emma ni iroyin sọ pe o lu Ọgbẹni Boluwatifẹ Omelaja nileewe aladani to n lọ nitori pe ko lee dahun ibeere iṣiro kan to bi i. Gẹgẹ bi a ṣe gbọ, aburo Boluwatifẹ, Lateef ti oun pẹlu jẹ akẹkọọ nileewe naa lo wa ṣilẹkun ọrọ fun awọn obi rẹ pe olukọ rẹ lo lu u pa. Ohun ti awọn alaṣẹ ileewe naa ṣe lalaye fun awọn obi rẹ gẹgẹ bi a ṣe gbọ ni pe, o fo ṣanlẹ ku ni kilaasi rẹ ni. Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi Koda wọn ni olukọ to lu u pa naa wa lara awọn to gbe oku rẹ wa ba awọn obi rẹ nile, laimọ pe oun gan lo wa ni idi ọrọ naa. Ohun ti a gbọ ni pe ẹka to n ri si imunadoko ati ijageere eto ẹkọ ni ipinlẹ Eko, Office of Education Quality Assurance ti bẹrẹ iwadii lori rẹ. Amọṣa titi di bi a ṣe n sọrọ yii, ọjọ mẹrin lẹyin ti iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ, ko si ẹni to tii kofiri olukọni to ṣiṣẹ laabi naa. Kí ló ṣekú pa Bolu, akẹ́kọ̀ọ́ ọmọ ọdún mẹ́rìnlá tó fò ṣánlẹ̀ kù nílé ẹ̀kọ́ ni Ikorodu? Awọn mọlẹbi ti ọmọ wọn ṣadede fo sanlẹ ku nileewe rẹ,Elihans Schools,ni Iṣawo Agric, Ikorodu ti sọ fun BBC pe awọn ko ro pe amuwa Ọlọrun ni iku rẹ jẹ. Boluwatife Omeleja akẹkọọ ọmọ ọdun merinla ni iroyin gbode loju opo ayelujara pe wọn gbe oku rẹ wale lati ileewe lỌjọbọ to kọja. Ridwan Oyewumi to sọ fun BBC pe oun ni ẹgbọn Bola fidi ọrọ mulẹ pe lootọ ni wọn gbe oku Boluwatife wa lati ileewe rẹ, Elihans College Ikorodu lọjọbọ. Ọkùnrin tó fẹ́ fipábámilòpọ̀ fín ǹkan sí mi lójú ló ṣe rọ́nà wọlé sí mi lára O ni ko pẹ si igba ti wọn gbe oku Bolu wa ni awọn ti sare lọ sin ni ibamu pẹlu ilana isinku musulumi. Ridwan ṣalaye pe baba awọn sọ pe awọn ko ni ṣẹjọ lori iku Bolu ṣugbọn awọn ni lati mọ ohun to ṣeku pa Bolu. Bawo ni Bolu ti ṣe ku? Alaye ti BBC gbọ ninu ọrọ ti Ridwan kọ si oju opo rẹ ni Twitter ati eleyi to sọ fun wa ni pe ẹni to nileewe ti Bolu n lọ lo ṣadede pe baba oun lọjọbọ. O ni wọn sọ fun wọn ki wọn tete maa bo wa nitori Bolu ti daku nileewe. ''Nigba ti Daddy wa gbọ, niṣe ni wọn gbera lati maa lọ si ileewe rẹ. Amọ loju ọna ni wọn ti pade olukọ ati ẹni to nileewe ti wọn gbe Bolu bọwa ninu ọkọ'' Ìyá Darasimi: Ọlọ́run fi ìbejì rẹ̀ mí lẹ́kún, lẹ́yìn ikú Darasimi tó mu sódà Ridwan ni Daddy awọn ri pe Bolu ko ṣọrọ ti wn si sare gbe lọ si bi ile iwosan meji ki o to di pe awọn dokita sọ pe Bolu ti ku. Alaye ti Ridwan sọ pe ọrẹ Daddy awọn to ni ileewe sọ fawọn ni pe olukọ beere ibeere lọwọ Bolu to si ni ko wa ṣalaye niwaju patako fawọn iyoku rẹ. ''O lọ siwaju kilasi ti wọn si fun ni ẹfun ko kọ alaye soju patako.Ibẹ ni Bolu ti daku.Nkan ti wọn sọ fun wa niyẹn'' O tun sọ pe ko pẹ si igba ti wọn ri pe Bolu ku ni ọrẹ Daddy(ẹni to ni ileewe) gba wa ni imọran lati wa ilẹ lọ sin Bolu si. ''Awọn ni wọn ra aṣọ, awọn ni wọn san owo fun awọn to gbẹ ilẹ.A pada sin oku rẹ si ilẹ Daddy wa ti o w ani toosi'' Ki lo wa mu awuyewuye wa lori iku Bolu Ọrọ gbọna mii yọ gẹgẹ bi Ridwan ṣe sọ nigba ti ẹgbọn Bolu to wa ni ileẹkọ kan naa de lati ileewe ni irọlẹ. Ridwan ni ẹgbọn rẹ, Lateef sọ pe olukọ kan(Mr Emma) lo lu Bolu ni kilasi to fi pada wa daku. ''Igba t i ẹgbọn rẹ sọ ọrọ yi fun wa lasiri pada wa tu pe ohun ti wọn sọ fun wa pe Bolu daku kii ṣe ootọ'' Ridwan ni awọn to jẹ ẹgbọn fun oun wa olukọ ti wọn pe orukọ rẹ ni Mr Emma lọ si ile rẹ lọjọbọ ṣugbọn wọn ko ba ni ile. O ni awọn tun wa lọ lọjọ Ẹti naa ti awọn ko si mọ ibi to gba lọ. ''Daddy wa lawọn ko ni ṣẹjọ lori ọrọ yi ṣugbọn wọn ni ti awọn akọroyin ba wa beere ọrọ nipa iku Bolu awọn yoo ṣalaye fun wọn'' ''Nkan ti awa mọlẹbi kan fẹ ni pe ki a mọ Boya iku amuwa lati ọdọ Ọlọrun ni iku Bolu tabi eeyan lo wa nidi rẹ'' Ki ni ileewe Bolu sọ BBC Yoruba pe nọmba ẹni to nileewe naa Oduwole GA ti awọn mọlẹbi Bolu fi ranṣẹ siwa. Amọ ẹni to gbe ago naa ṣalaye pe agọ ọlọpaa lawọn wa nitori naa awọn ko ni le da wa lohun lasiko taa pe. Bakan naa ni BBC pe ọga ọlọpaa(DPO) Ikorodu lori ago to si ni oun ko mọ nipa iṣẹlẹ naa. Iku ọmọdekunrin yi jẹ eleyi ti a o maa tọ pinpin rẹ lati mọ ohun to ṣẹlẹ wa si eti igbọ yin. Ṣugbọn bayi, mọlẹbi ti sin Bolu, ileewe ko ti fesi ti a ko si le sọ ni pato ibi ti olukọ ti wọn fẹsun kan pe o lu Bolu to fi daku wa.",0,yoruba Diwali yìí máa ń mú mi rántí àtùpà elépo wa. #IseseLagba https://t.co/Ls4Tpru82r,0,yoruba RT @user: @user babalawo je eniyan to ma se ise onisegun ni awon abule wa. E si le ri won ni gbogbo ilu omo yoba te ba de #Yor…,0,yoruba "@user nitori omo eta nii koko ta ki omo eranko too ta, tilu bata ba yo loke ijo ni teru tomo fii pade e. Iyi ni tiwa lojoojumo",0,yoruba ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o lẹ.,0,yoruba "RT @user: Màlúù tí ò ní ìrù, Ọlọ́run ni í lé eṣinṣin fún un. / God, Himself, is the one who fends off flies for a cow that has n…",0,yoruba "VPN, FG suspends Twitter: Pásítọ̀ Enoch Adeboye sọ̀rọ̀ lórí bí ìjọba ṣe gbégilé ojú òpó Twitter",0,yoruba bí o bá wà ní wá fún ìdánilẹ́kọ̀ọ́ lórí odù mẹ́rìndílógún ní brooklyn lọ́jọ́ karùndínlógún oṣù yìí,0,yoruba "RT @user: Ibi a ni ki gbegbe ma gbe, i be lon gbe.. Ibi a ni ki tete ma te i be lon te.. Ate pe le se n tena.. Ayun lo yun bo lowo yu ...",0,yoruba "Gbajugbaja oṣere tiata Yoruba, Laide Bakare ti ṣiṣọ loju eegun bo ṣe n gbe lọdọ eeyan ri, ti ẹni naa le jade ko to di onile mẹrin ọtọtọ niluu Eko. Ninu atẹjade kan to kọ loju Instagram rẹ, Laide kan sara si ara rẹ lọjọ ayajọ awọn obinrin lagbaye. Nigba to sọrọ lori bo ṣe jẹ ẹni ti ko nile lori ati bo ṣe di onile mẹrin. Kini osere naa wi? Oṣere naa to n ṣi ile rẹ kẹrin sọ pe ẹni ti oun ti figba kan ṣe oore fun pada le oun jade nile rẹ lakoko kan sẹyin, amọ ọpọn oun ti sun bayii. Laide ni ""Ẹni ti mo ran lọwọ lati jẹ eeyan laye sọ fun mi pe 'jade kuro ninu ile mi' amọ lonii yii mo ti di onile to le ni mẹrin laarin ilu Eko."" Ṣaaju ni oṣere naa ti kọkọ ṣafihan maluu atawọn owo ti awọn kan fi ranṣẹ si fun iṣile ọhun. O ni ọkan lara awọn ọrẹ oun lo fi maluu naa ranṣẹ ko to kede pe ọrẹ rẹ miran fi owo iṣile ranṣẹ si. Lẹyin to gba owo ati maluu naa tan lo sọ loju opo Instagram rẹ pe ""Ẹ jọmi loju gidi gan fun owo ti ẹ fi ranṣẹ simi, inu mi gidi lati jẹ ọrẹ yin."" Ta ni Laide Bakare? Laide Bakare jẹ ọkan gboogi lara awọn arẹwa obinrin ti irawọn rẹ tan nidi iṣẹ tiata Yoruba ni Naijiria. Wọn bi Laide Bakare lọjọ keje, oṣu Kẹwaa, ọdun 1980 niluu Eko. Irawọ rẹ bẹrẹ si n tan nigba to kopa ninu ere ""Mi O Foworola"" ti wọn gbe jade lọdun 2003 ati ere ""Love You Forever"" to jade lọdun 2005. Lara awọn ere mii to ti Laide Bakare ti kopa ni Ofin kokanla, Mafi Wonmi, Èsè, Atelewo eda, Ebo isinmi, Femi Oko Mummy, Royal Battle, ati bẹẹ bẹẹ lọ.",0,yoruba "@user Ma se ole oremi mura si ise, ise le gbe ee de ibi giga, Egbon eku in metta. #TweetinYoruba",0,yoruba "Nígbà tí Ìyá fè mú, Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.",0,yoruba ẹkọ́ ṣẹlẹ ni Ibadan ti gbogbo eniyan sọ o dara. (1998),0,yoruba Ọ̀bẹ ni ó fi gé e Ọtí ni a fi kì í Epo ni a fi dín in Sáré kí o bá a Gbe é fún un kí ó jẹ ẹ́ Pò ó pọ̀ kí ó se é mu #Ami #Yoruba #LearnYoruba,0,yoruba ọ̀gbọ́n. Alàji lo ni àṣà yorubá eyti o gbe lori ọ̀run dídì.,0,yoruba "Ó dà bíi wípé àwọn ọmọo wa ńta bíọ́bíọ́, pẹ̀lú ariwo yìí #nigeria",0,yoruba "Ìròyìn fi yéni pé àwọn ọmọ ogun lábẹ́ Operation Mesa gbé Abuibakar ni ọjọ ajé. Àwọn ọmọ ogun sọ lọ́jọ́bọ pé nínú ẹrọ ìléwọ rẹ̀ ni àwọn ti kọ́kọ́ ri níbi ti o ti gbé ìbọn AK-47 kọ́rùn to sì n jó. Ìròyìn fi yéni pé àwọn ọmọ ogun lábẹ́ Operation Mesa gbé Abubakar ni ọjọ Ajé. Saani: Gbogbo egungun Tiamiyu ló kán lẹ́yìn tí wọ́n tì í jábọ́ nínú ọkọ̀ Alábojutol ètò ìròyìn àti ọ̀rọ̀ to n lọ nilé iṣẹ́ ológun Ọgagun Aminu IIiyasu, to fìdí ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀ fún àwọn oníròyìn sọ pé àwọn ti mú ọmọbinrin to gbé ibọn kọ́run to si n jó ni bi ayẹyẹ kan. Ikọ kan náà lo tun ṣe alabapade, àwọn kan ni abule Kirsa nijọba ibilẹ Anka ni Zamfara nibi ti ọkùnrin kan ti gbe ọmọbinrin kan sùgbọ́n ni kété to ri àwọn ọmọologun lo fi ọkada rẹ àti ọmọbinrin náà silẹ to si sa wọ igbó lọ, sùgbọ́n ọmọ ogun bá ibọn AK-47 ti o si ni ọta bi ọgbọ̀n ninu.",0,yoruba lọ yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba "Kí a ṣe àjọyọ̀ àbí kí á máà ṣe é , ìbéèrè ni ìyẹn .",0,yoruba RT @user: Koje ki aye o gun https://t.co/cbeXNj4ZIB,0,yoruba owo ṣẹlẹ ni Eko ti gbogbo eniyan sọ o dara. (2012),0,yoruba Baàlè mú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba "Gbajugbaja akọrin ẹmi, Sola Allyson ti darapọ mọ awọn ọmọ Naijiria to n ṣe idaro iku ọkọ Bimbo Oshin, iyẹn Ola Ibironke, ti ọpọ eeyan mọ si Dudu Heritage. Ninu atẹjade kan to fi lede loju opo Instagram rẹ lo ti ṣedaro oloogbe ọhun. Sola sọ pe ọpẹlọpẹ Dudu Heritage ninu aye oun, ko ba si ẹni to n jẹ Sola Allyson lonii. Akọrin ẹmi naa ṣalaye pe Dudu Heriage lo sọ ohun di gbajumọ lẹyin to gbe awo orin oun, ""Eji Ewuro"" jade lọdun naa lọhun. O ni ""Lẹyin ti mo wo ẹyin wo, o han gbangba pe eto Ọlọrun ni bi mo ṣe pade oloogbe naa."" ""Lootọ ni mo ti n kọrin nigba naa fun nnkan bii ọdun marundinlogun, ṣugbọn aye ti su mi, nitori nnkan ko lọ bo ṣe yẹ ko maa lọ."" ""Mo pade Lanre to n ṣiṣẹ fun oloogbe nigba naa ninu ọkọ akero lati agbegbe Obalende si Ogba... wọn si fun ni iṣẹ lati kọ orin to wa ninu fiimu agbelewo Eji Ewuro, eyi ti Bimbo Oshin gbe jade."" Lootọ o wu mi ki n kopa ninu fiimu naa gẹgẹ bii oṣere, ṣugbọn wọn ni orin ni mo maa kọ. Lẹyin ti mo kọ orin naa, ni Dudu Heritage sọ pe mo gbọdọ ṣe orin ọhun sinu awo ti awọn eeyan yoo maa gbọ laaye ara wọn. Lati igba naa wa ni irawọ mi ti tan."" Sola sọ siwaju si pe, bo tilẹ jẹ pe awọn alabaṣiṣẹ Dudu Heritage ko fọwọ si igbesẹ naa, ṣugbọn o kọ si wọn lẹnu, o si ti oun lẹyin titi ti oun fi di ẹni ti aye n gbọ lonii. Gẹgẹ bii ohun ti Sola sọ, ọpọ awọn to gbiyanju lati ran oun lọwọ lasiko naa lo n fi ilọkulọ lọ oun, ṣugbọn ti Dudu Hertiage yatọ. O ni ""Ẹyin nikan ni ko fi ilọkulọ lọ mi bi awọn akẹgbẹ yin miran ṣe n ṣe, eyi to mu ki n yago fun wọn, eyi si jẹ ki n bu iyi fun yin pupọ."" ""Ọlọrun lo yin lati jẹ ki irawọ mi buyọ, ti ọpọ eeyan si mọ mi si Sola Allyson, Eji Owuro lonii... mi o le gbagbe yin lailai."" Sola Allyson pari idaro naa pẹlu adura pe, ki Ọlọrun jẹ ki oloogbe naa ri aanu gba, lẹyin naa lo ni oun ko ni gbagbe oore ti Dudu Heritage se ninu aye oun titi lai.",0,yoruba "Ko so gbon ta le da, ko si iwa ta lewu ti a le fi te araye lorun #tweetinyoruba",0,yoruba "Ní nígbà àkerekere, Ọba ri A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà. ti Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..",0,yoruba "Sísíwín àwọn olóṣèlú tí ó fẹ́ kú sórí ipò ààrẹ yìí ti ń pọ̀ jù Amoulanfe — Cheikh Fall ™ ( @ cypher007 ) ọjọ́ 14 , oṣù Ọ̀wàrà 2019",0,yoruba Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó ṣe pàtàkì. (Item 72),0,yoruba "Buhari ni awọn ẹka ti oun ko ti ni tẹti ni ipese eto aabo to yanranti, ọrọ aje to duro re, ipese isẹ oojọ, igbogun tiwa ajẹbanu ati ipese awọn ohuneelo amayedẹrun to duro re. Aarẹ Buhari jẹjẹ yii lasiko to n gbalejo awọn asaaju ẹgbẹ Arẹwa to wa se ẹ ku oriire si nile ijọba nilu Abuja. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Aarẹ Buhari ni oun ko ni ja awọn ọmọ Naijiria to ni igbẹkẹle ninu oun kulẹ ni saa keji yii pẹlu afikun pe gbogbo ipa ni oun yoo sa lati tẹ awọn araalu lọrun. Atẹjade kan ti amugbalẹgbẹ fun aarẹ lori eto irofin, Garba Shehu fisita ni aarẹ wa dupẹ pupọ lọwọ awọn agbaagba Arẹwa fun apọnle ti wọn fun oun ati atilẹyin wọn. ""Igbesẹ to kẹyin fun mi ni eyi jẹ. Ma sa gbogbo ipa mi lati sisẹ kara ju bi mo ti se tẹlẹ lọ, ti n ko si ni ja yin kulẹ rara."" Àwọn lọbalọba labẹ ẹgbẹ National Council of Traditional Rulers lọ kí Ààrẹ ní Abuja lẹ́yìn tó jáwé olúborí nínú ìdìbò sípò Ààrẹ. Ẹ̀yin ọba alayé ló mọ ọ̀daràn, ẹ ti mí lẹ́yìn láti wá wọn rí - Buhari Aarẹ Muhammadu Buhari ti kesi awọn ọba lorilẹede Naijiria lati fọwọsowọpọ pẹlu ijọba lati gbogun ti iwa ibajẹ lorilẹede Naijiria. Aarẹ Buhari sọ eyi lasiko to n gbalejo awọn ọba ni ile aarẹ ni ilu Abuja, lasiko to n ki wọn kaabọ si saa keji rẹ gẹgẹbi aarẹ orilẹede Naijiria. Seyi Makinde: Màá fẹ́ káwọn aráàlú mọ ìpa ìjọba mi lára sí rere O fikun wi pe, oun yoo pada si ile oun ni Daura ni ipinlẹ Katsina lẹyin saa keji oun gẹgẹ bi aarẹ. Aarẹ orilẹede Naijiria ni, lọpọ igba awọn ọba mọ awọn idile ti awọn ọdaran wa, nitori naa ni wọn se nilo awọn ọba ti wọn yoo soju awọn eniyan lọna to lamilaaka. Sultan ti ilu Sokoto, Alhaji Muhammad Sa'ad Abubakar III lo saaju awọn ọba naa lọ si ile aarẹ.",0,yoruba "Àwọn olólùfẹ́ẹ orin Soca ṣe àkíyèsí àròyé ọ̀tẹ̀ láàárín - in akọrin méjèèjì nígbà tí George gbé orin àkọ́ṣe ọdún 2019 jáde , “ Ìwọ́de Ojúná Bacchanal 2 ″ .",0,yoruba Iṣọ́ẹ̀ ìṣẹ́ ni a ní láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba se ife tomati ni sa iran yoruba kan feran alaafia ati irepo ju ohunkohun lo ni,0,yoruba "ẹ̀kó. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba lọ yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Alàji lo tun se joko.,0,yoruba kii a fii ori koo ori o san juu kii a fii ori gba ori loo dun nii ede,0,yoruba Àrídájú ìyọkúrò pánẹ́ẹ̀lì,0,yoruba ní ègé olóótọ fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa àwọn ènìyàn: ti o nuni ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo.,0,yoruba idẹ = brass idẹ ni a fi ṣe ère yìí we used brass to make this statue,0,yoruba "Iṣẹ̀lẹ̀ náà tó kan ẹlikọ́pítà Bell 206B lll pẹlu nọ́mba ìdánimọ 5N-BQW tí ilé iṣẹ́ ọkọ̀ òfurufú Quorum Aviation Limited ni wọ́n ti sàlàyè gbogbo ǹkan tó fa ìṣẹ̀ll ńlá ibi náà. Ìwádìí fi han pé ẹlikọ́pítà náà ni ìwé to pé pérépéré ti o si yẹ láti má a rin lójú òfurufú ti o si múlẹ̀ títí di ọjọ́ kẹfa ọsù kẹjọ ọdún 2020. Bákan náà ni kò si ẹ̀rí láti fi hàn pé ilé iṣẹ́ ẹlikọ́pítà náà kọ ìwé fún àjọ NCAA lati yọnda ọkọ ọ̀hun fún ìrìnàjò lẹ́yìn ti àsìkò to le rìn ti parí. Kò tún sí ààyè epo tó tó fún ọkọ òfurufú ọ̀hun. ""Àbájáde ìwádìí náà lọ báyìí, pé "" Wọ́n rọ epo kúnú ọkọ òfurufú náà lọ́jọ́ kẹtàdínlógún, oṣù kẹjọ, ọdún, 2020, wọ́n ẹnjínì rẹ̀ ṣiṣẹ́ fún ìṣẹ́jú mẹ́wàá fún àyẹ̀wò, bákan náà ni wọ́n tún wàá wò fún ogún ìṣẹ́jú ní ìlú Port Harcourt"" Abule Ado explosion: Irọ́ ńlá ní NNPC pa lórí ìbúghbàmù Abule Ado níbí tí ẹ̀mí èèyàn 23 Wákàtí mẹ́tà àti ìṣẹ́ju mẹ́ẹ̀dógún ni ẹlikapítà náà le farada iṣẹ́ mọ, sùgbọ́n ó ìrìnàjò wákàti méjì àti iṣẹ́jú mọ́runlélógójì ni wọn rán. Wọ́n taná si ẹ́njìnì rẹ̀ ní ààgo mẹ́sàn kọjá ìṣẹ́ju mẹ́ẹ̀dógún, ó sì gbéra ni aago mẹ́sàn kọjá ogún ìṣẹ́jú. Ó já ni aago méjìlá kọ́já ìṣẹ́jú mẹ́rìnlá. "" Ko si epo kankan ninu ọkọ náà ńgbà ti ìṣẹ̀lẹ̀ yìí ṣe, bákan náà ni abẹ̀bẹ̀ orí rẹ̀ dúró déédé lásìkò àbẹ̀wò lẹ́yìn ìṣẹ̀lẹ̀ ọ̀hún. Helicopter crash in Lagos: Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti bẹ̀rẹ̀ àtúnkọ́ ilé tí bàlúù agbéra pá tó jábọ́ bàjẹ́ ní Eko Ijọba ipinlẹ Eko ti bẹrẹ atunkọ agbegbe Opebi ti ọkọ baalu ẹlikọpita jabọ si ni ọsẹ to kọja. Oluranlọwọ pataki fun gomina ipinlẹ Eko, Gboyega Akosile fi lede ni ori opo ikansiraẹni Twitter wọn. Ninu atẹjade to fi lede naa sọ wi pe Gomina Sanwo Olu gbe igbesẹ naa lẹyin wakati mejidinlaadọta to jẹjẹ lati tun agbegbe Opebi ti baalu naa jabọ ṣe pada. Aarin ile ni agbegbe Salvation road ni Opebi naa ni ọkọ ofurufu hẹlikọpita wo si, to si ṣe ọpọlọpọ ipalara fun awọn to wa ni agbegbe naa. Eniyan mẹtẹẹta to wa ninu ọkọ baluu naa lo ti ku bayii, amọ eniyan meji lo kọkọ ku lẹsẹkẹsẹ ti iṣẹlẹ naa waye. Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo Olu jẹjẹ lati ri wi pe awọn ogiri to wo naa di titun kọ pada. Bakan naa lo ba awọn ẹbi ati ara ti ajalu naa ṣẹlẹ si kẹdun, pẹlu adura wi pe wọn ko ni rogun ibanujẹ mọ, ati wi pe Olorun yoo tu wọn ninu. Helicopter crash in Lagos: Gbogbo arìnrìnàjò inú ẹlíkọ́pítà tó já ní Opebi ti tẹ́rí gbaṣọ! Ìṣẹ́jú méjì péré tó máa fi bàlẹ̀ ni pápákọ̀ òfurufú ni ẹlikọ́pítà Quarom aviation já lulẹ̀ ní Opebi, Ikeja Arinrinajo kẹta to wa ninu ẹlikọpita to ja lulẹ ni Opebi, Ikeja niluu Eko ko pada ye e, o ti rekọja s'alakeji. Ajọ LASEMA ati agbẹnusọ ajọ to maa n wadii ọrọ to ni ṣe pẹlu ijamba lorilẹede Naijiria, Accident Investigation Bureau lo fidi ọrọ naa mulẹ. Bakan naa, iroyin ti a ri ko jọ ni pe iṣẹju meji pere lo ku ki ẹlikọpita naa balẹ ni papakọ ofurufu Murtala Muhammed ti Eko lo di wọ̀ọ̀ nilẹ̀. Nibayii, o tumọ si pe gbogbo awọn mẹtẹẹta to wa ninu ẹlikọpita naa lo ti ku. Ajọ to ma n wadii ijamba ni Naijiria lo ṣawari apoti dudu, to wa ninu ẹlikọpita, to ja lulẹ ni agbegbe Ikeja, nipinlẹ Eko. Awọn oṣiṣẹ ajọ AIB sọ pe ni nkan bi aago mẹta ọsan ni wọn ri apoti naa. 'Tíátà ọ́mọdé tí wọ́n ń kọ́ wa ní Bariga ti mú mi lọ Germany, Switzerland, Amsterdam...' Alukoro ajọ naa, Tunji Oketunbi, sọ pe awọn ti bẹrẹ iwadii ohun to fa ijamba naa. Ẹlikọpita naa, Bell 206, to ni nọmba idanimọ 5N BQW, jẹ ti ileeṣẹ Quorum Aviation lo ja lulẹ lati inu ofurufu wọ inu ogiri to la ile meji ni nọmba 16A Salvation Road, Opebi Ikeja ni Eko ni nkan bii agogo mejila abọ ọsan ọjọ ẹti. Ilu Port Harcourt, nipinlẹ Rivers, lo ti gbera, to si n bọ nipinlẹ Eko. Awakọ baalu kan, oṣiṣẹ baalu kan, ati ero kan lo wa ninu rẹ. Oludari ajọ apapọ to n mojuto iṣẹlẹ pajawiri ni Naijiria, Ibrahim Farinloye, sọ fun BBC pe lati ibi idanilẹkọ kan nilu Port Harcourt ni ẹlikọpita naa ti n bọ. Bakan naa lo sọ pe awọn olugbe inu ile ti ẹlikọpita naa ja lulẹ si, ti pada sile wọn. Agbẹnusọ Ileeṣẹ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri ni ipinlẹ naa, LASEMA, Nosa Okubo sọ fun BBC pe eeyan meji lo ba iṣẹlẹ naa lọ ti ẹnikan si farapa. Iṣẹlẹ ọhun waye lọsan ọjọ Ẹti ni ile to wa ni nọmba 16, Salvation, ni Opebi to wa ni Ikeja. Kọmiṣọna ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko, Hakeem Odumosu sọ fun BBC lojuko iṣẹlẹ ọhun pe ni kete ti iroyin naa tẹ awón ọlọpaa leti ni awọn oṣiṣẹ rẹ tẹkọ leti lọ sojuko ọhun. LASEMA sọ pe ọkunrin ni gbogbo awọn eeyan to ninu ọkọ ofurufu ọhun to jẹ ti ileeṣẹ Quorun Aviation ni ilu Eko. Ẹni ti ọrọ naa ṣoju rẹ, Olusunmade Olubunmi Damola sọ pe ""iṣẹlẹ yii ṣẹlẹ ni dede aago mejila kọja iṣẹju mẹrinla, a gbọ ariwo nla kan ninu ọfiisi wa to dun bi iro ibugbamu."" ""Igba ti a sa jade ni a to ri pe ọkọ ofurufu ẹlikọpita lo ja lulẹ."" Damola sọ pe oun atawọn ti wọn jọ n ṣiṣẹ yọ eeyan meji jade ninu ọkọ ofuru naa ṣugbọ ko ri aye yọ ẹnikan to ku tititi awọn adoola ẹmi fi de. Awọn asọju ileeṣẹ ijọba ijọba to n ri si iṣẹlẹ pajawiri to wa lojuko ti iṣẹlẹ naa ti waye ni iwadii ti bẹrẹ lati ohun gan pato to fa iṣẹlẹ'naa. Wọn ni wọn ko tii le sọ ibi ti ọkọ ofurufu na ti n bọ tabgi ibi to n lọ, ṣugbọn gbogbo eyii ni yoo di mimọ lẹyin iwadii.",0,yoruba lo ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó jáde nìlẹ̀̀ní sáàrí ti nípa ìtànká àti ire ènìyàn.,0,yoruba "Premier League final day: Aston Villa fọ́ Chelsea lẹ́nu, àmọ́ Tottenham daṣọ àṣírí bò wọ́n",0,yoruba "kún jú, àwọn ènìyàn ni ó pa Ọba lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa òkè: ti o tẹ.",0,yoruba eku dede asiko yi ajinde ara yio ma je,0,yoruba "nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Yàtọ̀ sí irun dídì àti kíkó, irun bíbà pàápàá ò gbẹ́yìn. Àsìkòo pàjáwìrì ni àwọn ìyáa wa ma ń ba irun wọ́n bí wọn kò dìí. #AwaLaNiIrun",0,yoruba "RT @user: @user :ko si 'soro,oplolopo jije mimu wa ni repete loni**erin muse",0,yoruba "ènìyàn yì í tún ṣe àwọn iṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba nípa ẹkọ́: ti o nuni ti o dara.,0,yoruba fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tó gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ àti ìbi tí wọn wà.,0,yoruba "ÌṢẸ̀DÁLẸ̀ ÌLÚ ILÉṢÀ Gẹ́gẹ́ bíi ìtàn àtẹnudẹ́nu Iléṣà, ọmọba Ifẹ̀, tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Ajíbógun (tí a sì mọ̀ sí Òbòkun), ni ó tẹ Iléṣà dòó. Nígbà tí ojú ń yọ Odùduwà lẹ́nu, Ifá ní kí wọ́n wá omi òkun wá. Ajíbógun ló fi ara rẹ̀ sílẹ̀, láti fi omi òkun náà",0,yoruba Ènìyan ti nilo oṣiṣu fun ìwà tabi ìkalo.,0,yoruba Àwòrán Òde .,0,yoruba emi awon eni eleni ti won fi sofo nko boya won o ni ife si polio o toju su enia o se odaa ki eniy,0,yoruba "Omoluabi wa ni ìwé orisirisi lo je ti ibile. Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.. A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..",0,yoruba "Ìgbéyàwó Ọmọọba Ìlẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì Harry àti ìyàwó rẹ̀ yóò wáyé lọ́la Bí ìmúrasílẹ̀ ìgbéyàwó náà ṣe n kásẹ̀ nlẹ̀ di ọjọ́ Àbámẹ́ta báyìí, kò tíì sí ẹni tí yóò dúró gẹ́gẹ́bíi bàbá ìyàwó ni ibi àyẹyẹ náà, tí yóò wáyé ni ilé ìjọsìn St. George. Ìyawó ọ̀la, Meghan Markl,e gbé àtẹ̀jáde kan síta ní Ọjọ́bọ pe bàbá òun, Thomas Markle, kò ní lè wá sí ibi ìgbéyàwó náà, kó bàá lè tọ́jú ara reẹ̀. A gbọ́ pé ìyá ìyàwó Doria Ragland, yóò lọ kí Ọbabìnrin Elizabeth fún ìgbá kínní lónìí. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ní báyìí ná, wọ́n ti gbé fọ́tò àkàrà òyìnbó tí ọgọ́rùń mẹ́fà àwọn àlejò Ọmọọba ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì, Harry àti ìyàwó rẹ̀, Meghan Markle yóò jẹ, ní ibi ìgbéyàwó wọn ti yóò wáyé lọ́la jáde báyìí. Claire Ptak ń ṣiṣẹ́ lórí àkàrà òyìnbó náà Fọ́tò náà ṣe àfihan Claire Ptak, tó ń ṣiṣẹ́ lórí àkàrà òyìnbó náà nínú ilé ìdáná ààfin Ọbabìnrin Elizabeth, ti a mọ̀ sí Buckingham Palace ni ọjọ́ Ọjọ́bọ. Ọjọ́ márùń ni la gbọ́ pe Ptak àti àwọn òṣìṣẹ́ rẹ̀ mẹ́fà ti ń ṣiṣẹ́ lórí àkàrà òyìnbó náà. The cake is being decorated with a white, elderflower Swiss meringue buttercream",0,yoruba "Ile ẹjọ da Olorin Small Doctor silẹ lẹyin ti wọn mu u lopopona kan l'Eko to n fi ibọn dẹru ba awọn ọlọpaa to da ọkọ rẹ duro. Wọn fi ẹsun pe o ni ohun ija oloro lọna aitọ. Iroyin to n tẹwa leti ni wi pe wọn da a silẹ pẹlu ikilọ pe ko ma ṣe kopa ninu iwa ipa kankan titi ọdun kan gbako. Ẹwẹ, ninu ifọrọwanilẹnuwo BBC Yoruba pẹlu agbnu sọ rẹ, o fi aridaju han pe wn ti daa silẹ sugbọn ohun ko ni le sọrọ pupọ fun oniroyin lasiko ti a ko iroyin yii jọ. A ò fẹ àwáwí, owó wa ni ẹ san - àwọn òṣìṣẹ́ ilé aṣòfin Amosun lẹ́tọ̀ọ́ láti gbè lẹ́yìn oludíje tó bá wù ú - APC Ahamọ ẹka ọtẹlẹmuyẹ ileeṣẹ ọlọpaa Ipinlẹ Eko (SCID) ni olorin takasufe Small Doctor ti orukọ rẹ gangan n jẹ Michael Owusu Addo, sùn lati ọjọ Aje tí àwọn ọlọ́paa ti mu. Kọmiṣọna ọlọpaa nipinlẹ Eko, Edgal Imohimi lo fi afunrasi olorin naa han awọn oniroyin ni ọjọ Aje lori ẹsun nini ibọn lọwọ lai bá òfinmu ati gbigbimọran lati yinbọn lu ọlọpaa. Ni ọjọ Isegun ni agbẹnusọ fún ileeṣẹ ọlọpaa ni Eko Chike Oti sọ fun akoroyin BBC Yoruba wipe, oun kò tíì mọ ọjọ́ tí olorin naa yoo foju ba ile ẹjọ. Small Doctor bẹ BBC Yoruba wo ni oṣu keje nibi to ti sọrọ nipa igbesi aye rẹ Small Doctor: Mo kórira igbó, ọtí àti sìgá nítorí màmá mi lòdì si Oti ṣalaye pe wọn ba ibọn lọwọ gbajugbaja olorin naa ti iwadi si ti bẹrẹ lori ẹsun naa ati pe ni kete ti ọrọ ba yanju, wọn yoo gbe lọ si ile ẹjọ. Iroyin sọ pe ọlọpaa aṣọna kan ti o n ṣiṣẹ rẹ lagbegbe Oshodi ni ilu Eko ni Small Doctor yọ ibọn si. Kọmíṣọ́nà ọlọ́pàá ní ìpínlẹ̀ Eko ní èyí kìí ṣe ìgbà àkọ́kọ́ tí wọn yóò mú Small Doctor fún ẹ̀sùn tó níí ṣe pẹ̀lú ìbọn "" Wọn ni awọn ọkunrin mẹrin kan ninu ọkọ ti wọn ko gba nọmba idanimọ si fa ibọn kan yọ ti wọn si leri ati yiiin in ms ọlọpaa naa bi ko ba kuro ni oju ọna fun wọn."" Pẹlu ero pe adigunjale ni awọn eeyan wọnyii ni mo fi ni ki awọn ọlọpaa o gba tẹle wọn ti wọn si mu wọn."" Ibọn gigun kan ati ọta ibọn ni wọn ba lọwọ awọn eeyan naa ninu eyi ti wọn ni olorin naa, Small Doctor wa. Gẹgẹ bi ọga ọlọpaa naa ti ṣe wi, olorin naa ti wa ninu irufẹ ẹsun yii ri ti wọn ni o yin ibọn eyi to ṣe awọn eeyan mẹrin lẹṣe ti wọn si di ero ileewosan. Small Doctor wà lára àwọn ọ̀dọ́ olókìkí tí ileeṣẹ ọlọpaa yàn gẹgẹ bii awokọṣe nilu Eko. Akẹgbẹ rẹ to jẹ olorin takasufe Korede Bello naa wa lara awọn ti ileeṣẹ ọlọpaa yan gẹgẹ bii awokọṣẹ ati aṣoju laarin awọn ọdọ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Ìyá Tíṣà lòdì sí kí n mutí, fagbó tàbí sìgá' Tọkọ-taya Aràrá: Àwọn èèyàn máa ń wò wá, ta bá fa ọwọ́ ara wa ní títì .",0,yoruba sí ìbàdandun láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Bẹ́ẹ̀.,0,yoruba Ìwọ̀n àtòjọ fèrèsé tó kéré jù,0,yoruba ó wáyé.. A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà.,0,yoruba "Photo:'Tinubu, Akande with Kwankwaso: on a condolence visit to Kano' Condolence pelu Erin ati ajoyo Eyi O gbayi ra ra http://t.co/rElleK45S4",0,yoruba "fi. Nitori eyi, ara eni lo ni ọ̀gbọ́n.",0,yoruba "RT @user: If, male - Baba ọkọ Female - Iya ọkọ. #Yoruba https://t.co/2RflAgXcsv",0,yoruba nípa ẹkọ́: ti o nuni ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó ga.,0,yoruba T'ọmọ aròbó tí obìnrin nì ń gbé lọ síbi ìṣekúṣe ẹ̀gbẹ́ ògiri ni ò sunwọ̀n. Ẹ̀rù ọ̀la ọmọ yẹn ń bà mí bí ìyá rẹ̀ bá ń báa lọ bẹ́ẹ̀. #KoDerun,0,yoruba "RT @user: Oye ke? """"""""""""""""@user: A kú afẹ́rẹ́ ọyẹ́ t'ó ń fẹ́ yẹ yìí o, á tù wá lára o! #Yoruba""""""""""""""""",0,yoruba ní wúlò. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Alàji lo ojú odò.,0,yoruba "Ìjọba Nàìjíríà: Ọ̀rọ̀ ẹ̀yìn ni ọ̀rọ̀ Trump nípa Ààrẹ Buhari Ijọba apapọ orilẹede Naijiria ni pẹlu gulegule iroyin ayederu to n waye bayii lorilẹede Naijiria ati kaakiri agbaye, o yẹ ki eniyan ṣọra fun irufẹ iroyin bayi paapaa julọ lati ẹnu aarẹ orilẹede bii ti Amẹrika. Minisita feto iroyin lorilẹede Naijiria, Alhaji Lai Muhammed to gbẹnusọ fun ijọba apapọ orilẹede Naijiria ṣalaye fun BBC Yoruba pe to ba jẹ pe lootọ ni Aarẹ Donald Trump sọ ọrọ yii jade, o ku diẹ kaato; paapaajulọ bi o ṣe jẹ pe niwaju gbogbo agbaye ni aarẹ Trump ti sọrọ to si gboṣuba fun aarẹ Buhari pe o kun oju iwọn lati kogoja gẹgẹ bii adari orilẹede Naijiria. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọ̀rọ̀ Trump àti Russia kò yàtọ̀ pé àhesọ lásán ni èyí jẹ́ Ni owurọ ọjọ aje ni okiki kan nipa iroyin kan ti iwe iroyin Financial times gbe jade nipa ohun ti wọn ni aarẹ Trump sọ pe Buhari ko dun un ba rin pọ atipe oun ko gbadura ki oun pade irufẹ eeyan bii rẹ mọ laye oun. Buhari kò ṣe é bá ṣe pọ̀ Lẹyin ipade naa ni aarẹ orilẹ-ede Amẹrika, Trump ṣalaye pe oun ko fẹ pade 'ẹni ti ko dun-un ba ṣe pọ' bii Buhari mọ laye oun Aarẹ orilẹ-ede Amẹrika, Donald Trump, ṣe apejuwe aarẹ orilẹ-ede Naijiria, Muhammadu Buhari, gẹgẹ bii 'ẹni ti ko dun-un ba ṣe pọ' ni kete ti wọn ṣe ipade tan ni ọgbọn ọjọ, oṣu kẹrin, ọdun 2018. Ninu agbejade rẹ ninu iwe iroyin Financial Times ti ọjọ́ Aje ló ti sọ eyi di mimọ. Buhari ni Aarẹ akọkọ lati ilẹ Afirika ti yoo ba Trump joko ṣepade pọ lẹyin ti wọn bura fun un gẹgẹ bii aarẹ karundinlaadọta fun orilẹ-ede Amẹrika. Lẹyin ipade ni aarẹ orilẹede Amẹrika,Trump ṣalaye pe oun ko fẹ pade 'ẹni ti ko dun-un ba ṣe pọ' bii Buhari mọ laye oun O ba Trump sọrọ lasiko ipade naa lori ajọṣepọ okoowo laarin orilẹ-ede mejeeji. Lẹyin ipade naa ni aarẹ orilẹ-ede Amẹrika, Trump ṣalaye pe oun ko fẹ pade 'ẹni ti ko dun-un ba ṣe pọ' bii Buhari mọ laye oun. Lọwọ yii, ijọba Amẹrika ati Naijiria ko tii fesi lori iroyin yii paapaa bi o ṣe jẹ ọjọ́ kan naa ti aarẹ orilẹ-ede Kenya, Uhuru Kenyatta yoo ma ṣepade pẹlu aarẹ Donald Trump ni ile funfun balau White house. Eyi yatọ gedegbe si ohun ti Aarẹ Trump sọ sita faraye gbọ lasiko ti ipade naa waye. Buhari ati Trump ṣe ipade lori ajọṣepọ owo ni oṣu kẹrin ọdun 2018 Kini Trump sọ? Trump ni oun ni igbagbọ to kuna ninu Buharai lati gbogun ti ""obitibiti iwa ijẹkujẹ"" to wa lorilẹ-ede Naijiria. Gẹgẹ bii ọrọ kan ti eeyan kan ti iwe iroyin Financial Times fi orukọ bo laṣiri sugbọn to n ṣe alarinna laarin orilẹ-ede Amẹrika ati Kenya sọ, ""Afirika ko figba kan ri wa ni ara ohun to ṣe koko fun aarẹ Trump ṣugbọn bi o ba fẹran rẹ yoo wa ọna lati rii pe nnkan rere waye laarin ẹyin mejeeji."" Wọ́n rò pé mo ya wèrè ni Saudi lẹ́yìn ikú ọkọ mi",0,yoruba "kọ. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.",0,yoruba ènìyàn a yi yi ti o nuni ti o nuni ti o tẹ.,0,yoruba "ní ìgbà kan, a ri ọ̀rọ̀ ìlú lo je ti ibile.",0,yoruba Ìfẹ̀hónúhàn ní Luanda ( ọjọ́ kẹrin oṣù Èrèlé ) .,0,yoruba ìṣẹ́ ni a ní nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn aláìì lẹ̀.,0,yoruba Àkóbì níjó òní nípa àbá èwe lo je ti ibile.,0,yoruba ri pe lẹ ìkòkò wey ti o pẹ jú nìlọ̀ ni ọ̀nà tí ẹ̀ọ́ kan máa ń.,0,yoruba ojú àwọn adigunjalè tó kó ẹrù benin ní rè é pẹ̀lú ẹrù olè tí wọ́n jí,0,yoruba "Iroyin sọ pe ija lo waye laarin Emmanuel ati ololufẹ rẹti wọn jọ n gbe, Patricia Ogunshola, ni ile wọn to wa ni Araromi, Morogbo nipinlẹ Eko. Ẹni ọdun mẹtadinlaadọta ni wọn pe Emmanuel, ti Patricia si jẹ ẹni ọdun mẹtadinlogoji. Gẹgẹ bi a se gbọ, ede aiyede na da lori iwa agbere, eyi to yọri si kiko ẹṣẹ bo ara ẹni. A gbọ pe lasiko ija naa ni Emmanuel binu mu ọbẹ, to si fi gun Patricia ni itan, ko to o di pe Patricia raaye sa jade. Lẹyin naa ni Emmanuel fi ọbẹ naa gun ara rẹ ni ikùn. Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Eko sọ pe, ariwo ti ọmọ Patricia pa, lo jẹ ki awọn alajọgbele wọn o mọ nipa nkan to ṣẹlẹ. Oku Emmanuel si ni awọn ọlọpaa ba nilẹ pẹlu ọbẹ naa nigba ti wọn pe wọn sibi isẹlẹ ọhun. Iroyin ọhun tẹsiwaju pe, wọn gbe Patricia lọ sile iwosan fun itọju, ti wọn si ti gbe oku Emmanuel lọ sile igboku si. Iru iṣẹlẹ bayii ko ṣẹṣẹ ma a waye l'orilẹ-ede Naijiria laarin ololufẹ. A kò mọ ẹni tó pa ọlọ́pàá Ondo àti ìyàwó rẹ̀, òun kọ́ ló pa ara rẹ̀- ọlọ́pàá Saaju la ti sọ fun yin pe irọ ni iroyin kan to sọ pe ọlọpaa kan ti wọn pe orukọ ni Tolulọpe pa iyawọ ati ara rẹ lori ẹsun pe iyawo naa n ṣe agbere. Ọjọ kejila, oṣu Kẹta, ọdun 2020 ni iṣẹlẹ naa waye nilu Akungba-Akoko. Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa fidi rẹ mulẹ fun BBC Yoruba, Ọgbẹni Tee-Leo Ikolo wi pe pẹlu ayọ ati idunnu ni ọlọpaa naa fi kuro nibi iṣẹ rẹ to wa ni Akungba Akoko, oun pẹlu aya ati awọn ọmọ wọn. Ọgbẹni Ikolo ni ṣa deedee lawọn lawọn gbọ iro ibọn lati ile ọlọpaa ọun eyi to kọju si ago ọlọpaa to ti n ṣiṣẹ niluu Akungba Akoko Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni nigba tawọn de ibẹ lawọn ba oku ọlọpaa naa ati iyawo rẹ nilẹ. O ṣalaye pe iwadii si n lọ lọwọ lati mọ ohun to ṣe okunfa iku awọn mejeeji gan an. Ọgbẹni Ikolo ni ileeṣẹ ọlọpaa ti gbe ọmọ ọwọ ati ọmọ ọdun meji ti iyawo naa n gbe lọwọ to fi ku fun mama iyawo naa. Ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn yoo ṣalaye fun araalu ohun to fa iku awọn mejeeji ti iwadii ba ti pari.",0,yoruba "ẹ̀kó. Nitori eyi, ara eni lo je ti ibile.",0,yoruba wúlò. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọba lo joko.,0,yoruba oro ni yen ki awon odo wa gbo lo ku,0,yoruba "RT @user: """"""""""""""""@user @user : Igbakeji Are ana; Atiku ko iwe si egbe Oloburela lori ai kopa re to ni nu egbe. http://…",0,yoruba àwọn ọmọbìnrin wa yìí dà,0,yoruba "ìbadandun. Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba obìnrin a yi fi ti o pẹ jú nìlọ̀ ni ọ̀nà tí ẹ̀ọ́ kan máa ń gbé ìyẹ̀ alẹ́.,0,yoruba "Májèlé ni àdín àgbọn Ọ̀jọ̀gbọ́n náà, nígba tó ń fèsì sí fọ́rán ìdínilẹ́kọ̀ọ́ kan tó ń sọ àwọn àǹfàní tó wà lára òróró àgbọn lórí Youtube. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn èèyàn àti awakọ̀ ké igbe ìrora bí àwọn ọkọ̀ ńlá ṣe dí ọ̀nà mọ́rosẹ̀ Apapa-Oshodi pa Bákan náà ni àwọn ẹgbẹ́ àwọn tó ń rí sí ìlera ọkan l'Amerika, rọ̀ àwọn ènìyàn láti yàgò fún àdín àgbọn nínú ìwé ìròyìn Business Insider ti Deutschland. Ọ̀jọ̀gbọ́n Karen ni adarí dídènà iṣan wíwú lọ́nà ti kò dára ní Fasiti Freiburg àti Ọ̀jọ̀gbọ́n Harvard TH Chan nílé ẹ̀kọ́ ilera. Nínu ìkọ́ni rẹ̀, Michel sàlàyé ìrú òunjẹ tó yẹ kí ènìyàn máà jẹ, tó sì fí kún-un pé àdín àgbọn kò dára rárá fún mimu tabi jijẹ.",0,yoruba "Ṣebí ó ní ohun t'ó ṣe ẹja tí ẹja fi kákò, a kò ṣòpò ṣe ìwádìí kọjá èyí tí a mọ̀. #EdeAbinibi #Yoruba",0,yoruba Ìròyìn tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó wáyé..,0,yoruba "eni lo ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba @user Ọlọ́run Ọba á wà pẹ̀lú #PatienceJonathan o. Àmín!!,0,yoruba àsa. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó wáyé.,0,yoruba Coronavirus: Àwíjàre ọlọ́pàá ni pé dókítà múra bíi onínàbì láago mẹ́wàá alẹ́,0,yoruba "Láti orígun mẹ́rẹ̀ẹ̀rin àgbáyé , igbe ńlá ni ó gba àwọn akọbúlọ́ọ̀gù Zone9 sílẹ̀ lọ́wọ́ ìjọba ilẹ̀ Ethiopia .",0,yoruba "🔵Ọlẹ̀ á sọ nínúu gbogbo obìnrin tó ń w'ọ́mọ 🔵Bàbá ra ẹran abàmú - Ọmọ inú ọmọ ènìyàn ni 'ọlẹ̀', ọmọ inú ẹranko tàbí ọmọ ẹyẹ ni à ń pè ní 'àmú'. #InYoruba #Yoruba #LearnYoruba #Language https://t.co/YbTIJOyZJH",0,yoruba "Nnkan yan lalẹ ọjọ Satide, ọjọ kejila oṣu kejila ọdun 2020 nigba ti awọn akanṣẹjẹun meji, Anthony Joshua ti ilẹ Gẹẹsi ati Kubrat Pulev ọmọ Bulgaria. Lẹyin o rẹyin Anthony Joshua lo bori nigba to fi ẹṣẹ ja Pulev bs bi apo irẹsi nigba ti ija wọn wọ ipele kẹsan. Pẹlu abajade ija ẹṣẹ kikan naa, Anthony Joshua ṣi ni agba ọjọ akanṣẹ to di bẹliti ẹyẹ WBO, WBA ati IBF mu bayii. Ija naa ti wọn ja lati aṣalẹ ọjọ Satide wọ kuutkutu owurọ ọjọ Aiku ni igba kejilelogun ti Joshua yoo fi ẹṣẹ ja akanṣẹjẹun miran bọ ni apo irẹsi, iyẹn Knockout lati igba to ti bẹrẹ si ni kan ẹṣẹ jẹun, eyi si ni igba keji ti Pulev yoo kuna lati igba to ti n ja ẹṣẹ jẹun.",0,yoruba ìyẹ̀ alẹ́. Èyí ni òun tí a ní láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó wáyé..,0,yoruba ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò.,0,yoruba Ìbẹ̀rẹ̀ vidíò yorubá tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba "kan. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "E ma je ki a tori Ede ba eede je nitori bi a ba de lati Ede, eede la o pada si #OroAmoye",0,yoruba obirin yorùbátv ẹgbẹ ọmọ olúwa bí gbogbo àgbáyé ojú òpó ìkànsíraẹni yoruba tv,0,yoruba "Eyi ni ero onimọ kan nipa ihuwasi ẹda ati imọ sayẹnsi nipa ọpọlọ, Matthew Walker, to wa lsgba fasiti California. Awọn onimọ ni oorun ni oogun to jẹ ọfẹ julọ, eyi to lee fun ara rẹ ni ilera to peye julọ, lẹyin iwadi imọ ijinlẹ to le ni aadọta ọdun, wọn ko lee beere mọ nipa awọn ohun ti oorun sisun lee mu wa fun wa, bikose pe ka beere pe, n jẹ nkankan wa ti oorun sisun ko lee se fun wa? Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Iwadi ti wa fidi rẹ mulẹ pe, aisun maa n ni ipa to buru julọ lori ọpọlọ ati ẹya ara wa. Gbogbo awn aisan bii jẹjẹrẹ, aisan ọkan, ara asanju, atọgbẹ, ironu ati iwa gbigba ẹmi ara ẹni, to maa n tete ran awọn eeyan sọrun ni awọn orilẹede to ti goke agba lagbaye, lo ni nkan se pẹlu oorun sisun. Aṣọ òkè: Alákọ̀wé ní ọ̀nà láti wá oúnjẹ fáwọn tó ń ṣe aṣọ òkè ló ṣún òun débẹ̀ Amọ, oorun yii gbọdọ wa funra rẹ ni, kii se afioogun pe, eyi to lee sokunfa aisan jẹjẹrẹ, kokoro ti a ko lee fi oju ri ati iku aitọjọ. Oorun sisun kii se ka gbe ori le irọri nikan, tori kii se ọpọ eeyan lo lee tete sun lati ipasẹ eyi nikan Sugbọn awọn onimọ ni ta ba lee mu ayipada ba awọn iwa kan to ti di baraku fun wa, a maa sun bo se yẹ Bawo la se fẹ ri oorun gidi sun ni alẹ: To ba lee maa ji, ko si maa sun ni akoko kan naa lojoojumọ, eyi too ran ọ lọwọ lati maa mọ iye wakati to fi n sun, ti oorun yoo si maa kun ọ, ti akoko to yẹ ko sun ba ti ko. A nilo lati wa ninu okunkun, ki ara si balẹ, ki omoonu kan, ti wọn n pe ni Release Melatonin, to n fa oorun sisun, lee sisẹ rẹ. Sugbọn ọpọ wa la n gbe ni ayika ti imọlẹ ti yi wa ka, sugbọ o le seranwọ fun ara rẹ nipa mimu adinku ba imọlẹ to wa ni ayika rẹ, nigba to ba ku wakati kan to fẹ sun. Jẹ ki ibusun rẹ sun nipa ko ma yi kaakiri tabi maa ba irọri rẹ ja",0,yoruba "RT @user: """"""""""""""""""""""""""""""""@user: ♫ Orí mi tètè là kórí ọlọ́rọ̀ má pè ẹ́ rán níṣe ♫ @user"""""""""""""""""""""""""""""""" Ire o!",0,yoruba "RT @user: “@user: @user Egbon, ori yin wa nibe ju ju ju. Ajanaku koja mo ri n ka n firi. #ourchangeishere” Taa ba rerin ka …",0,yoruba ni òun tí a kọ eḳọ nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o nuni ti o dara.,0,yoruba ìṣẹ́ ni ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba Bàbá lo ni ìgbà mi owó àkokò eyti o gbe lori àìmọ́.,0,yoruba "Jìjìn ọ̀pọ́lọ̀ ni ìbàdandun àtọ́wọ́dá, àwọn oníṣẹ́ ìṣẹ́ ni a ní láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o nuni ti o pataki.,0,yoruba Àwọn ọlọ́pàá ṣe ọ̀kan lára àwọn olórí ìbílẹ̀ tí í ṣe alágbèékalẹ̀ ìyíde náà ṣìbáṣìbo .,0,yoruba "ìbàdandun láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìwà: ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba ìjọba wa yìí oadarí aṣojú àti aṣòfin wa gbogbo ọdún titun la wà ẹ fi ìfẹ́ bá wa ṣe pọ̀,0,yoruba Ènìyan ti nilo oṣiṣu fun ilera tabi ibini.,0,yoruba ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba ni ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba "èwe. Nitori eyi, ara eni lo ni ẹ̀ká àwẹ eyti o gbe lori ọ̀run dídì.",0,yoruba Ojoojúmọ́ ni ọkọ̀ òfuurufú ńjá ní #Nigeria. Kí ló ńṣẹlẹ̀ gan an? #Agagu #Akure #PlaneCrash #Plane #AssociatedAirlineCrash,0,yoruba Yẹ ohun-èlò ápúlẹ́ẹ̀tì wò,0,yoruba Àwòrán 1 : Túwíìtì irọ́ ti Festus Keyamo,0,yoruba Baby starts menstruating at four months: Ọmọ ìkókó bẹ̀rẹ̀ ǹkan oṣù l'ọ́mọ oṣù mẹ́rin,0,yoruba "Ọrọ pọ ninu iwe kọbọ Njẹ ẹ mọ pe kii ṣe ilu Ibadan nìkan ni orúkọ ẹgbẹ janduku, One Million Boys, ti gbajúmọ? Ìtàn tilẹ sọ pe adugbo Ajegunle nilu Eko ni awọn ọdọmọkunrin kan ti bẹrẹ ẹgbẹ naa lọdun diẹ sẹyin. Wọn ni afojusun àwọn ni lati ma a gbéjà àwọn alailagbara láwùjọ. Sugbọn, ẹgbẹ naa tun gbajúmọ̀ fun ole jíjà, ipaniyan, ati ifipabanilopọ ni Eko. Sinima àgbéléwò Yoruba kan ti wọn pe orúkọ rẹ ni One Million Boyz ti ẹ jade lọdun 2014, eyi to safihan ihuwasi wọn. Lọdun 2012, ọwọ ọlọpaa tẹ awọn bi aadoje to jẹ ọmọ ẹgbẹ naa ni adugbo Apapa ati Ajegunle. Orúkọ wọn tun jẹ jade lasiko isede coronavirus laarin oṣu Kẹrin si oṣu Karun un, ọdun 2020, fun pe wọn n ka àwọn eeyan mọ́lé lati ja wọn lólè nipinlẹ Eko. Ẹ wo adúrú ǹkan tí Softface ma ń tò pọ̀ láti sín àwọn òṣèré, gbajúgbajà jẹ One Million Boys ni Ibadan Adugbo Kudeti nitosi Molete nilu Ibadan ni a le pe ni ibùba tabi ibùdó àwọn ọmọ ẹgbẹ 'One Million Boys' nilu Ibadan. Adugbo Kudeti kii ṣe ibi to pamọ rara. Koda, àwọn oloṣelu nla bi i oloogbe Adelabu Adegoke 'Penkelemesi' fi ṣe ibugbe nigba aye rẹ, ile rẹ ṣi wa nibẹ titi di oni. Awọn akọsilẹ kan ti ẹ sọ pe ko jina si opopona Adebipon, ti awọn ọmọ ẹgbẹ naa ti kọkọ fa wahala. Iwaju ile ijọsin nla Cathedral Church of Saint David, ni Kudeti, ni awọn janduku naa ti fa rogbodiyan kan to waye lọjọ kọkandinlogun, oṣu Kejila, ọdun 2016. Kii ṣe igba akọkọ niyẹn ti ẹgbẹ naa ati awọn orogún wọn fa wahala ni agbegbe naa. Ni nkan bi aago mẹjọ alẹ ni ìró ìbọn bẹrẹ si ni i dún, eyi to mu ki ọpọ eeyan o fi ile, sọọbu wọn silẹ, koda awọn kan fi ara pa. Iroyin sọ nigba naa pe ọkọ ayọkẹlẹ, kẹẹkẹ 'maruwa', ati ọkada ni awọn janduku naa gùn wọ adugbo ni alẹ ọjọ buruku, eṣu gbomi mu ọhun. Iṣẹlẹ naa mu ẹ̀mí awọn ara adugbo kan lọ. Wọn tun dana sun awọn ile itaja kan ni adugbo naa. Awọn iroyin kan tilẹ sọ pe búrẹ́dì ni awọn janduku naa rẹ ni epo bẹtiro, ti wọn si n ju sinu sọọbu, ki wọn o to sọ ina si i. Nkan to fà iṣẹlẹ buruku to sọ awọn idile kan sinu ibanujẹ ko ṣe e sọ ni pato. Awọn iroyin kan sọ pe ija naa waye nitori pe awọn ọmọ ẹgbẹ million boys mú ọmọ ẹgbẹ alatako, 'indomie' kan, to ji ẹ̀rọ ibanisọrọ, ti wọn si 'ba a wi'. Eyi lo fa a ti olori ẹgbẹ naa, Indomie, fi ko awọn ọmọ ẹgbẹ rẹ, ti wọn si lọ ọ doju ogun kọ Abiola 'Ebila' , to jẹ olori ẹgbẹ one million boys. Abala kejì ija wọn lo waye ni alẹ ọjọ ti a n sọ yii. Ko fi bẹẹ si akọsilẹ nipa rẹ, sugbọn a le sọ pe ọdun 2014 ni orúkọ rẹ kọkọ jade sita lasiko ti àṣírí ibuba awọn ajinigbe kan tú ni agbegbe Soka niluu Ibadan. Oun la gbọ pe o siwaju awọn eeyan kan lati wa ọrẹ rẹ to di awati, ki asiri ibùba naa to o tu. A ti ẹ gbọ pe ileewe girama St. Lukes, to wa ni Molete lo lọ. To si di gbajumo janduku lẹyin to pada silu Ibadan lẹyin irinajo rẹ si Eko. Awọn kan ti ẹ tun sọ pe pupọ lara awọn ọmọ ẹyin rẹ lo jẹ àwọn ti ko rikan-sekan lẹyin ti gbajugbaja oloṣelu nilu Ibadan, Lamidi Adedibu, di oloogbe. Awọn janduku maa n jẹ lọdọ Adedibu nigba aye rẹ. Ile rẹ ko to wa ni Molete ko si jina si Kudeti, ti one million boys fi ṣe ibujoko. Àmọ́ o, kii ṣe adugbo Kudeti nikan ni awọn ọmọ ẹgbẹ yii wa. Wọn tun ni ẹka si awọn adugbo bi i Beere, Mapo, Born Photo, Idi-Aro, Isale Asaka, Idi-Arere, Odinjo, Modina, ati bẹẹ bẹẹ lọ. Oṣu Karun, ọdun 2020, ni ileesẹ ọlọpaa ti n wa Ebila, fun ipa to ko ninu iku to pa olori ẹgbẹ janduku miran, Moshood Oladokun 'Ekugbemi' l'oṣu Kẹrin. Ki oun naa o to kagbako iku lasiko ti ija waye laarin one million boys ati orogún wọn kan lọjọ Aiku, ọjọ kejila, oṣu Keje ni adugbo Olomi. Gbajugbaja janduku ni Ekugbemi nigba aye rẹ, ti awọn iroyin kan si sọ pe olori ẹgbẹ okunkun kan, to n da wahala silẹ nilu Ibadan ni. Ko pẹ ti wọn fi Ekugbemi silẹ ni ọgbà ẹ̀wọ̀n Agodi nilu Ibadan, ni wọn pa a. A ko le e sọ ọmọ ẹgbẹ ti Ekugbemi jẹ́ ninu one million boys, Indomie, ati Abe igi Boys. Awọn ẹgbẹ mẹtẹẹta ni orúkọ wọn ma n jẹ jade lasiko ti wahala bá waye ni awọn adugbo to wa ni aarin gbùngbùn Ibadan. A gbọ pe awọn janduku naa ma n kopa ninu gbígba ilẹ̀ onílẹ̀, ija àgbà, eyi to ma n yọrí sí iku, ati òfò dukia. Lọjọ ti wọn pa Ekugbemi, iroyin sọ pe awọn ọmọ ẹgbẹ Biola Ebila lo kọlu u, lasiko ti wọn fẹ ẹ gba owó ọmọ onílẹ̀ , lọwọ ẹnikan to n fi paanu bo ilé rẹ ni agbegbe Olunde, nitosi ile Ekugbemi. Ada ni wọn fi ṣá a yanna-yanna. Ileesẹ BBC ti ẹ gbọ nigba naa pe wọn sare gbe e lọ si ìdí òrìṣà ni agboole wọn ni adugbo Born Photo, lẹyin ti wọn ṣá. Sugbọn o kú nitori pe o padanu ẹ̀jẹ̀ to pọ. Iroyin ti ẹ sọ pe o jíǹde lẹyin ti wọn ṣe àwọn ètùtù kan, ko to o tun pada kú. Titi di oni, iyalẹnu lo ni iku rẹ si n jẹ fun ọpọlọpọ to gbagbọ pe ko yẹ ki ada o ran an, nitori agbara ibilẹ to ni.",0,yoruba "Wahala to tẹyin idibo naa pọ debi wi pe awọn eeyan koribijade lo si ibi'ṣẹ Ninu abajade iwadi igbimọ ti wọn ṣe agbekalẹ rẹ sọ, awọn ọmọ ileeṣẹ ologun kan ati awọn janduku to yabo ibudo ti wọn ti n ko esi ibo jọ ni o da eto idibo naa ru. Wahala to bẹ silẹ lasiko idibo Gomina naa ni o mu ki Inec so idibo si ipo Gomina ati ti ile aṣofin rọ lọjọ kẹwa Oṣu kẹta ọdun 2019 . Atẹjade Inec Amọ ṣa ajọ naa ni awọn yoo ṣi yi ba awọn oṣiṣẹ alabo ilu gbogbo jiroro lori bi awọn eeyan wọn ko ṣe ni ma ṣegbe lasiko idibo. Gẹgẹ bi ohun ti a ri ka ninu atẹjade kan tioludari eto ifọrọto ara ilu leti ati idanilẹkọ awọn oludibo Festus Okoye buwọlu,Inec ni awọn fi idi ọrọ mulẹ pe idibo waye ni pupọ ninu awọn agọ idibo ti awọn si kede esi wọn. Ninu ẹka asoju mejilelọgbọn Inec ni awọn kede esi dibo to waye ni aaye idibo mọkanlelogun. Atẹjade Inec Ajọ Inec ni awọn ko ni ko irẹwẹsi ọkan lati pari eto idibo nibi ti awọn ti kede esi ibo. Okoye wa salaye pe awọn yoo pawọpọ pẹlu gbogbo awọn ajọ to ba yẹlati ri wi pe eto idibo nipinlẹ naa ni iyanju. O so pe Ogunjọ osu kẹta ni wọn yoo sọ igba ti idibo naa yoo pada waye ati gbogbo ilana ti awọn yoo fi ṣeto naa.",0,yoruba ẹ̀ká ojú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "Awó ṣe ìrúbọ, wọ́n sì ṣe ọṣẹ Ifá fún yèrèpè kí ó máa fi wẹ̀. #WerepeNinuIfa #Yoruba",0,yoruba iṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba ẹkọ́ ṣẹlẹ ni Ibadan ti gbogbo eniyan sọ o ṣe pataki. (2021),0,yoruba Premiership league: Liverpool fẹ́rẹ̀ ẹ́ forígbá níwájú Southampton ṣùgbọ́n orí kó o yọ,0,yoruba "Waris kò fi àkókò sòfò rara ní kété tí ààrẹ Faranse de ibùdó ìgbafẹ́ Afrika Shrine ti olóògbé Fela tó wà nílu Eko, láàrin wákàtí kan sí méjì péré ló ti yà àwòran Macron. Waris náà jokoo fẹ̀gbẹ́-kẹ̀gbẹ́ pẹ̀lú Gómìnà Akinwunmi Ambọde àti gbaju-gbaja olorin nni, Banky W, lati ya foto nibi toti n gbe aworan naa kalẹ fun Emmanuel Macron. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:",0,yoruba "ọ̀gbọ́n. Ìyá lo ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.",0,yoruba Àrẹ̀mọ ọba tí ó ti gun orí ìtẹ́ bàbá rẹ̀ ò mọ níye. #AbobakuOoni #Yoruba,0,yoruba vidíò yorubá tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé.,0,yoruba Baàlè mú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò.,0,yoruba oruko mi ni oluwatobi adisa won bi mi si ibadan nile oluyole nilu ogunmola olodogbo keri loju ogun ibadan omo ajorosun,0,yoruba Kí ni ìtumọ̀ 'ẹja ni nbí akàn'? #Ibeere #Yorùbá #YorubaQnA,0,yoruba "Koko ohun to fa sababi aawọ naa ko se lẹyin eto idibo aarẹ to n bọ lọdun 2023 ninu eyi ti awọn eeyan kan n sọ kiri pe oloselu naa fẹ kopa ninu rẹ. Ẹgbẹ oselu APC lo gbe ọrọ atawọn aworan eroja ipolongo ibo fun Asiwaju Bola Tinubu soju opo Twitter rẹ, eyi ti wọn kọ 'Africana Jagaban' si lara. 'Ẹ kálọ sí ìlú mi'... Ètò ńlá tó bẹ̀ sílẹ̀ kìjà lórí BBC Yorùbá Olori ẹbi ati Dawodu Fela, Femi Kuti ti wa pariwo si oju opo Twitter rẹ pe oun ri awọn eroja ipolongo ibo naa ti ẹgbẹ APC gbe sita bii T-Shirt, ti wọn lo orukọ idamọ awọn. Femi ni lara awọn eroja ipolongo ibo naa ni wọn ti ri ọrọ 'Africana Jagaban', bẹẹ si ni orukọ Africana yii ọpọ eeyan mọ Fela Anikulapo mọ. Femi Kuti wa n ke si awọn ọmọ ẹgbẹ oselu APC ati Asiwaju Tinubu funra rẹ pe ki wọn yọ orukọ Africana naa kuro lara eroja ipolongo ibo ti wọn n pin kiri. O salaye pe orukọ idamọ ẹbi Fela ni Africana naa, ẹgbẹ oselu APC si n tẹ ẹtọ awọn mọlẹ nipa lilo orukọ nnaa lai gba asẹ lọdọ ẹbi awọn. Gbajumọ akọrin Afro Beats naa ni yoo dara ki ẹgbẹ oselu APC tete pa awọn ohun to kọ ati aworan to gbe soju opo Twitter rẹ rẹ ko to di nnkan mii. ""Ẹbi wa ko fara mọ ẹgbẹ oselu kankan lorilẹede Naijiria tabi loke okun. A n se ayẹwo bi nnkan yii se n lọ finnifinni. Irú ẹ̀dá wo ni Fẹla Jẹ́? Tẹ ba si kuna lati tẹle ibeere wa, a jẹ pe a ko ni nnkan miran ta se ju pe ka tẹle ilana ofin to wa larọwọ to wa. Amọ lọwọlọwọ bayii, ẹgbẹ oselu APC ti gbọ imọran ti Femi Kuti gba wọn, to si ti gbe awọn aworan eroja ipolongo ibo naa kuro loju opo Twitter rẹ.",0,yoruba ìwòrìwò ni àgbàdo ń wọlẹ̀ igba aṣo ní í mú jáde | gbogbo àdáwọ́lé mi á yọrí sí rere lọ́lá alálẹ́ yìí,0,yoruba "Amọ, ijọba ilẹ Paraguay si fi ofin de e wi pe ko gbọdọ jade nile. Lọjọ kẹfa oṣu kẹta to lọ ni wọn mu Ronaldinho ati arakunrin rẹ, Roberto Assis lori ẹsun pe wọn lo ayederu iwe irina wọn orilẹede Paraguay. Awọn mejeeji gbọdọ wa ni igbele bayii titi di igba ti igbẹjọ wọn yoo fi bẹrẹ. Ṣugbọn Ronaldinho ati arakunrin rẹ sọ pe awọn ko jẹbi ẹsun ti wọn fi kan awọn. Agbẹjọro wọn tiẹ ṣapejuwe igbesẹ ijọba naa lati fi wọn si ahamọ iwa ta ni yoo mu mi eleyi to lodi si ofin. Adajọ Gustavo Amarilla ara gbedeke to wa ninu beeli awọn mejeeji ni pe wọn ko gbọdọ sa lọ. Ronaldinho rinrin ajo lọ si orilẹede Paraguay tẹlẹ lati ṣe ifilọlẹ iwe rẹ ati ipolongo fawọn ọmọ ti obi wọn ko ri ọwọ họri. Ronaldinho to gba ife ẹyẹ agbaye pẹlu Brazil lọdun 2002 gba bọọlu fun Paris St-Germain, Barcelona ati AC Milan ilẹ Yuropu ko to fẹhinti lẹyin to ṣoju Fluminense fun igba diẹ ni Brazil.",0,yoruba "Àkóbì níjó òní nípa ìya ìlú. Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.. Eyi ni adetokun ninu ilu.",0,yoruba ni ìwájú. Ọmọ lo ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "Ní ní àìlẹ̀, Ìyá ri Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.",0,yoruba "àsà tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìṣẹ́ ọ̀pọ́lọ̀.",0,yoruba "se, Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa aráyé: ti o ní wúlò.",0,yoruba "Emir Sanusi korò ojú sí ìwà àílákàsí àwọn alásẹ tí ọ̀rọ̀ ìdókówò náà kàn ní Nàíjíríà Ètò náà, tí wọn pè ní ìpàdé ìdókówò láàrin Amẹ́ríkà àti Nàíjíríà, ni iléesẹ́ asojú Nàíjíríà tó wà ní Amẹ́ríkà sètò pẹ̀lú léesẹ́ aládàání kan. Àfojúsùn ìpàdé náà ni láti kó àwọn alásẹ ní Nàíjíríà àti ní Amẹ́ríkà sábẹ́ òrùlé kan pẹ̀lú àwọn oníléesẹ́ aládàáni, olùdókòwò, àtàwọn ọ̀gá àgbà iléesẹ́ ńláńlá. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Obinrin Akansẹ: Ẹsẹ kiku bi ojo kọ mi lati di alagbara Lásìkò tó ń bá àwọn akọ̀ròyìn sọ̀rọ̀, Emir Sanusi korò ojú sí ìwà àílákàsí àwọn alásẹ tí ọ̀rọ̀ ìdókówò náà kàn ní Nàíjíríà. Kò sí ẹnikẹ́ni nínú wọn tó tíì dé lásìkò tó yẹ kí ìkọ̀ọ̀kan wọn sọ̀rọ̀ Ní ibi ìpàdé náà ni wọ́n ti ń retí igbákejì ààrẹ, Yẹmí Ọsìnbájò, mínísítà fún ètò ẹ̀náwó, àti akẹẹgbẹ́ rẹ̀ ní ẹ̀ka epo rọ̀bì, ètò ọ̀gbìn, ètò ìròyìn, ìmọ̀ sáyẹ́ńsì,ohun àlùmọ́ọ́ní ilẹ̀ àti mínísítà fétò okoòwò, sùgbọ́n kò sí ẹnikẹ́ni nínú wọn tó tíì dé lásìkò tó yẹ kí ìkọ̀ọ̀kan wọn sọ̀rọ̀.",0,yoruba "Alakoso awọn oṣiṣẹ aṣọbode l'Apapa, Muhammed Abba Kura ṣalaye pe, awọn oogun Tramadol ọhun to ọgọta miliọnu Naira. O fikun ọrọ rẹ pe, ninu ọkọ itọju alaisan pajawiri taa mọ si ambulance lawọn afurasi meji ọhun kọkọ ko oogun naa si. Lẹyin ti ọwọ tẹ wọn tan, ni awọn oṣiṣẹ aṣọbode tun rii wi pe oogun Tramadol tun kun inu agolo ikẹru si, ti wọn n pe ni ''container'' bamu. Awakọ ati oṣiṣẹ ile iṣẹ kan lawọn afurasi meji ọhun tọwọ sinkun ofin ti ba bayii. Awọn oṣiṣẹ aṣọde ni iwadii ṣi n lọ lọwọ lori iṣẹlẹ naa.",0,yoruba "Ní kété tí àjọ elétò ìdìbò Nàìjíríà kédé ọ̀jsgban Kayode Fayemi gẹ́gẹ́ bí eni tó jáwé olú borí ni àwọn ará ìlú ti bó sí ìgborláti dáwọ̀ọ́ ìdùnú. Aago mẹjọ̀ owurọ ni awọn oludibo ti jade lati yẹ orukọ wo ati iforukọsilẹ. Awọn arugbo to lọwọọwọ lati yan eni ti wọn fẹ ko jẹ gomina wọn ni Ekiti. Ẹgbẹ oselu marundinlogoji lo dije du ipo fun gomina ipinlẹ Ekiti ni ọdun 2018. Ajo INEC leyin idibo naa sọ wi pe idibo naa lọ ni irọwọrọsẹ laisi si ifarapa. PDP sọ wi pẹ idibo naa ko lọ ni irọwọrọsẹ atiwipe wọn ji ibo gbe ni awọn agbeegbe kan. Witi witi ni awọn eniyan pe jọ lati gbọ esi idibo ni wọọdu ati ekun idibo wọn. John ọmọ Fayẹmi sin ilẹ Naijiria ilẹ baba rẹ̀ gẹgẹ bii olukọni ni Police College to wa ni Ṣokoto lapa ariwa Naijiria. Ile ti mọ, ta lo jawe olubori ni ibeere awọn eniyan ni owurọ kuto ọjọ keji idibo. Ilú àdó Ekìtì ní àwọn ará ìlú ti gbòdé láti fi ìdúnú wọn han lóri èsì ìbò. Kayode Fayemi ti ṣe gomina ipinlẹ Ekiti ri laarin Ọjọ kẹrindinlogun, osu kẹwaa, ọdun 2010 si ọjọ kẹẹdogun, osu kẹwaa, ọdun 2014. Ní kété tí àjọ elétò ìdìbò Nàìjíríà kédé ọ̀jsgban Kayode Fayemi gẹ́gẹ́ bí eni tó jáwé olú borí ni àwọn ará ìlú ti bó sí ìgborláti dáwọ̀ọ́ ìdùnú. Awọn eekan ninu ẹgbẹ oselu APC ni wọn ki Fayemi ku orire. Awọn aworan naa wa lati ileesẹ BBC.",0,yoruba "“ Ikú rẹ̀ jẹ́ àdánù ńlá fún ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ , orílẹ̀ èdè Nàíjíríà àti àgbáyé lápapọ̀ , nítorí ó jẹ́ asíwájú rere tí se ọmọ bíbí ilẹ̀ Ìbàdàn ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ , tí kò fi ẹlẹ́yàmẹ̀yà sé , tó fi ọjọ́ ayé rẹ̀ sin orílẹ̀ èdè Nàíjíríà pẹ̀lú agbára rẹ̀ “ Gómìnà wá fi àsìkò ọ̀hún bá àwọn ọmọ olóògbé náà tó",0,yoruba nípa òkè: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba lọ. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.,0,yoruba _Áíkànnù:,0,yoruba "Ṣe ìwádìí orí alátagbà, mo nǹkan tí àwọn èèyàn ní ìfẹ́ sí, tàbí tí wọ́n fẹ́, kí o tó gbé ọjà jáde. #smwPolling @user @user",0,yoruba "Genotype test: Ilé aṣòfin kàn án nípá fáwọn tó fẹ́ ṣèyàwó láti ṣàyẹ̀wò ẹ̀jẹ̀ Ni bayii, o ti di didan fawọn ọdọkunrin ati ọdọbinrin ti wọn ba fẹ ṣegbeyawo lati ṣe ayẹwo ẹjẹ ki wọn to lọ sori pẹpẹ. Ile igbimọ aṣoju-ṣofin Naijiria lo kan an nipa fawọn obinrin atawọn ọkunrin to ba fẹ fẹ ara wọn ni Naijiria ninu apero wọn l'Ọjọbọ. Awọn aṣofin ti wa kepe awọn ẹka ijọba to n ṣe eto igbeyawo, awọn ṣọọṣi atawọn mọṣalaaṣi wi pe ki wọn maa beere esi iyẹjẹwo ki wọn to so ẹnikẹni pọ. Ile igbimọ aṣoju-ṣofin ni igbesẹ yii ṣe pataki lati dena aarun arunmọleegun ni Naijiria. Gbogbo ile lo tẹwọgba aba naa ti aṣofin Umar Sarki to gbe e wa pe akori rẹ ni ''Kepe ile iṣẹ ijọba to n ri si ọrọ ilera lati wa ọna ati dẹkun aarun arunmọleegun ni Naijiria.'' Divorcee: Ó sàn kí wọ́n yàgò fúnra wọn ju ki wọ́n ṣe ara wọn léṣe- Fisayo Awọn aṣofin tun kepe ẹka ijọba to n ri si eto ilera lati pese iwosan ọfẹ fawọn to laarun arunmọleegun. Ni afikun, wọn rọ ijọba lati sọ fawọn ile ijọsin ati ẹka idajọ lati maa lo esi ayẹwo ẹjẹ gẹgẹ ọkan lara amuyẹ fun igbeyawo. Ile igbimọ aṣoju-ṣofiun tun rọ ijọba lati fi idanilẹkọọ lori aarun arunmọleegun sinu eto ẹkọ ile iwe alakọbẹrẹ ati ti girama ni Naijiria. Ile paa laṣẹ fun igbimọ to n ri si eto ilera, iroyin, ọrọ ilanilọyẹ ati ọrọ lati rii pe igbesẹ yii di imuṣẹ. Ninu ọrọ rẹ, aṣofin to gbe aba naa silẹ, Ọgbẹni Sarki ni iwadii fihan pe aarun arunmọleegun ti wa nilẹ Afirika fun bi ẹgbẹrun un mejila ọdun, eleyi ti ilẹ Adulawọ ko si tii ṣe nnkan gbogi lati dẹkun rẹ. Tọkọ-taya Aràrá: Àwọn èèyàn máa ń wò wá, ta bá fa ọwọ́ ara wa ní títì Iwadii fihan pe Naijiria lawọn to larun arunmọleegun ti pọju lagbaaye pẹlu miliọnu mẹta aabọ eeyan o le diẹ to larun naa. Bakan naa ni iwadii fihan pe aadọjọ ọmọ ikoko ninu ọọdunrun tawọn eeyan n bi lagbayee lọdọọdun lo wa lati Naijiria. World Diabetes Day: Ọdún kọkandinlogun ti mo ti wà lẹ́nu itọ ṣúgà nìyí",0,yoruba "'Àwa Ebira tí wà ní Owo fún ""Donkey years"" ẹ má na ìka àbùkù sí wa lórí ìkọlù Kátólíìkì Owo'",0,yoruba Ọpẹ́ ló yẹ Ọlọ́run Ọba tó jí mi sáyé. Ọba Alágbára lórí oun gbogbo. Ají tòní ná ti ẹlẹ́gàn ló kù.,0,yoruba "Ipa kékeré kọ́ ni àlọ́, ìtàn àti ìṣẹ̀lẹ̀ àtẹ̀yìnwá nínú àṣà. Ka bí àwọn oníṣẹ́ ìwádìí kan ní Asia ṣe lo àlọ́ àti ìtàn ìbílẹ̀ fún ìpolongo ìtọ́jú àyíká. #OhunAgbaye https://t.co/bkPDirrbfT",0,yoruba "ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba Joenia Wapichana níbi tí ó ti ń gbè lẹ́yìn ọ̀rọ̀ ìbílẹ̀ kan ní ilé - ẹjọ́ gíga jùlọ .,0,yoruba Ọ̀pọ̀lọpọ̀ akọ̀ròyìn lló júbà ehoro tí àwọn mìíràn bíi Esdras Ndikumana jẹ mo - yó - ìyà,0,yoruba concise version olóòpá njé olè fúmi ní ìséjú méfà láti so òótó òrò fú o láti so òótó òrò táwon òjèlú àwon afúni lóko ìdi òpero àwon òránmo lómo nísé dé tòru tòru tí wón perawon ní ìjoba òfé jékí omò,0,yoruba igi àáyán nípọn gidi ganan ni tó jẹ́ wípé ó máa ba ẹnu àáké jẹ́ èyí ló dífá fún òwe nì àáyán kò gba àáké,0,yoruba "Aarẹ buhari atawọn adari agbaye Minisita tẹlẹ ri fun ọrọ katakara ati idokoowo, Okechukwu Enelamah ṣi oju BBC Yoruba si bi Naijiria ṣe pa a ti wọn kun un ti wọn fi ṣe daadaa loju tirẹ pe wọn kọkọ wale wa ronu si i ki wọn to tọwọ bọ ọ. Aarẹ Naijiria Muhamadu Buhari ṣẹṣẹ fọwọ si adehun okoowo kan naa yii ni nibi ipade apero ajọ iṣọkan ilẹ Afrika to waye ni orilẹede Niger lọjọ Aiku. Gẹgẹ bi Enelamah ṣe sọ ọ, o jẹ igbesẹ ti yoo ko ipa pataki ti yoo si ṣe atunto nilẹ Afirika fun odidi ọgọrun ọdun si isisiyii tabi ko tilẹ ju bẹẹ lọ. O ni ipa ribiribi si ni Naijiria ko ninu iduna dura adehun ọhun. Naijiria to wa ṣe eyi gan lo wa ni awọn fẹ rii daju pe awọn pe ipade awọn tọrọ kan na labẹle ki wọn to le tọwọ bọ iwe adehun naa. Ọpọ awọn onwoye lo n beere pe ṣe erongba ibudo okoowo ilẹ Afrika ọhun ko ni foriṣanpọn bayii, nigba ti orilẹede Naijiria to ni eto ọrọ aje to tobi ju lọ ni Afrika, to tun jẹ olori ẹkun Afrika yọwọ kuro ninu rẹ nigba ti awọn to ku n dara pọ mọ ọ. Fulani Kidnapping: Owó púpọ̀ la san kí wọ́n tó fi mi sílẹ̀ Awọn tọrọ kan ti aarẹ Buhari pe si ọrọ yii ni bii ẹgbẹ awọn to n pese ọja lorilẹede Naijiria, ẹgbẹ awọn oniṣowo, to fi mọ awọn ijọba ipinlẹ gan lati rii pe wọn ṣe iṣẹ to yẹ ki wọn ṣe na lori igbesẹ pataki yii ki wn to gbe e. Naijiria kọ lati ṣe bi awọn orilẹede Afirika to ku ṣe ṣe nipa pe awọn kọkọ tọwọ bọwe adehun ki wọn to lọ sile lọ ro o. Naijiria kọkọ ṣalaye iwulo rẹ, anfani rẹ wọn si gbọ latẹnu awọn tọrọ ọhun kan. Enelamah ni pẹlu igbesẹ ti Naijiria gbe yii ti wọn jẹ ki araalu mọ ohun ti wọn fẹ ṣe, o fi han pe ijọba awa ara wa fẹsẹ mulẹ daadaa ni Naijiria. Odidi ọdun kan ni Naijiria fi ṣe eyi ki wọn to wa pinu lati dara pọ. Awọn Iroyin ti ẹ le nifẹ si Bawo lo ṣe kan araalu lasan ni Naijiria? Okechukwu Enelamah ṣalaye fun akọroyin BBC pe kii kan kii ṣe fun awọn alagbara ilu nikan, oniruuru ọna lo fi le kan ọmọ Naijiria kọọkan. Lori kiko ọja wọle lọna aitọ, Enelamah ni ko tọ naa ni bi apejuwe rẹ ṣugbọn kii ṣe pe tori rẹ kii ṣe pe ki a dawọ pipese ounjẹ fun apẹrẹ irẹsi duro. Dipo ki o ko ba ọrọ aje, enelamah ni kiko ọja ilẹ okere wọle lọna aitọ gan la gbudọ mu kuro lọna.",0,yoruba "àkerekere, Olùwo ri Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Amin e po, ola a san wa oooo #yoruba #yorubamovies #yorubamovie eniolaafeez @user @user Osogbo https://t.co/g5omhjyql2",0,yoruba ṣebí láyé awólọ́wọ̀ bí ìwé tí o kà ni búrẹ́dì rẹ yóò ṣe tóbi tó a gbéwèé sórí tán a bẹ̀rẹ̀ sí ní fi ẹsẹ̀ fọ́n ìgboro kiri,0,yoruba RT @user: @user nigbogbo ona oluwa loye kama fi ope fun nitori nipa ife ree lafi wa laye,0,yoruba bbc news yorùbá zainab habib arábìnrin wà ní àhámọ́ ní saudi lórí ẹsùn tí kò mọ,0,yoruba Bàbá aláwo yóò wá ihò kan nílẹ̀ tàbí lẹ́ẹ̀gbẹ́ ògiri níbẹ̀ ni yó fi ẹyin yìí pamọ́ sí. #Yoruba #science #Ideyun,0,yoruba "Sugbọn kii ṣe Sowore nikan ni ijọba ti fi iru ẹsun bayii kan, ti wọn si ti dero atimọle latari ọrọ naa. Ẹjẹ ka wo diẹ ninu wọn. Anthony Eromosele Enahoro Irawọ Oloye Anthony Enahoro tan lọdun 1944, nigba to di ọga akọroyin fun ileeṣẹ Nigerian Defender ni ọmọ ọdun mọkanlelogun, eleyi to mu ko jẹ ọga akoroyin to kere julọ ninu itan orilẹede Naijiria. O mura si iṣe akọroyin to bẹẹ gẹ, ti wọn fi ran an lẹwọn ọdun marundinlogun lori ẹsun igbimọdite lọdun 1963, lẹyin ti wọn fi ẹsun ifipa gbajọba kan igbimọ ẹgbẹ oṣelu rẹ, Action Group. Ọpọ igba ni ijọba apapọ sọ Enahoro si atimọle lati ọdun 1945 lori oriṣiiriṣii ẹsun. Enahoro papopda lọjọ kẹwa oṣu kejila ọdun 2010. Kunle Ajibade Ijọba ologun labẹ ọgagun oloogbe Sani Abacha lo fi ṣikun ọba mu Ajibade, to si fi ẹsun igbimọditẹ kan an. Iṣẹlẹ yii lo waye lẹyin ti orukọ rẹ jade ninu atyẹjade kan ti iwe iroyin 'TheNews' gbe jade, ni ibi to ti jẹ ọga akọroyin. Wọn fi ẹsun kan an pe o gbe iroyin jade, eleyi ti wọn ni o le di eto ipẹjọ awọn to fẹ ditẹgbajọbalọwọ lọwọ. Ijọba tun ni Ajibade n ṣi awọn ara ilu lọna, eleyi ti wọn ni o mu ko jẹ ọkan lara awọn aditẹgbajọba lọjọ naa lọhun. Ijiya ẹsun naa ni ẹwọn gbere. George Mbah George Mbah jẹ oṣisẹẹ ileeṣẹ akọroyin Tell. Ni ọjọ karun un oṣun karun un ọdun 1995, lẹyin ọdun kan to kuro ni ile iwosan latari ijamba ọkọ ni wọn fi panpẹ ọba mu nilu Eko pẹlu awọn akọroyin miran. Bi o tilẹ jẹ pe ko si idi kan pato ti wọn fi mu, yatọ si iditẹgbajọ ti awọn kan se si ijọba akoko naa. Ijọba ran Mbah lẹwọn ọdun marundinlogun. Toll Gate: Ó ṣe pàtàkì kí ìjọba kọ́kọ́ tún ojú popo ṣe naa- Awakọ̀ Chris Anyanwu Chris Anyanwu jẹ akọrin, ounkọwe, oloṣelu ati oṣiṣẹ ileeṣẹ The Sunday Magazine. Anyanwu ṣẹwọn laarin ọdun 1995 si 1998 fun igbimọditẹ lẹyin to kọroyin nipa iditẹgbajọba to kuna ti wọn gbiyanju rẹ si ijọba Sani Abacha. Ijọba ran lẹwọn gbere, sugbọn lẹyin akitiyan awọn eeyan ati awọn kan ẹgbẹ lorilẹ-ede agbaye, wọn din ẹwọn naa ku si ọdun marundinlogun. Lẹyin iku ọgagun Sanni Abacha ni ijọba ọgagun Abdulsalam Abibabkar tu sile, latari ailera to n ba fira. Ben Obi to jẹ oṣiṣẹ The Weekend Classic, Chris Anyawu ati Kunloe Ajibade ni ijọba ko ṣẹkẹṣẹkẹ si lọwọ nigba kan naa. Omoyele Sowore Sowore jẹ gbajugbaja akọroyin ati oludije sipo aarẹ orilẹ-ede Naijiria labẹ asia ẹgbẹ African Action Congress lọdun 2019. Ni ọjọ kẹrin oṣu kẹjọ ni ajọ ọtẹlẹmuye ko ṣẹkẹṣẹkẹ si lọwọ lori ẹsun igbimọditẹ ati pe o n gbimọ ifẹhonuhan tako ijọba. Lẹyin akitiyan awọn agbẹjọro rẹ ni ile ẹjọ kan gba beeli rẹ pẹlu ọgọrun miliọnu naira. Agba Jalingo Jalingo ni oludasilẹ iwe iroyin Cross River Watch. Lọwọ yii, Jalingo n jẹjọ ẹsun iṣẹrubalu, igbimọditẹ ati ẹsun pe o fẹ doju ijọba ipinlẹ Rivers bolẹ. Bi o tilẹ jẹ pe o ni oun ko jẹbi ẹsun naa ti wọn fi kan, ile ejọ kọ lati jẹ ki awọn agbẹjọro rẹ gba beeli rẹ. Ọpọlọpọ iwọde ni awọn ololufẹ rẹ ti ṣe latari pe wọn ni awọn agbofinro mu lọna ti ko ba ofin mu. Imam tó ṣí Mọ́ṣálásì fáwọn Krístẹ́nì sọ ìdí tí kò fi lè ta wọ́n nù",0,yoruba RT @user: Ketekete ti pada te 🏃🏃🏃🏃 #voiceover #yoruba 18+ https://t.co/vXX8SJQzxX,0,yoruba vidíò yorubá tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó wáyé..,0,yoruba "Ìkíni ayẹyẹ, ọ̀fọ̀ yàtọ̀ sí ìkíni ojú ọjọ́ ati ìgbà àt'àkókò. Ìyálẹ̀ta la wà yìí, bí mo fẹ́ kíi yín, máa ní """"""""""""""""""""""""""""""""ẹ kú ìyálẹ̀ta o"""""""""""""""""""""""""""""""". #ikini https://t.co/5sMj2Q15Zi",0,yoruba Wàyí o! Kí ni ẹran iléyá pípa? Ìrúbọ ni iléyà tàbí ìrúbọ kọ́? Kí ni abájọ tí a fi ń pa àgbó fún Allah? Kíni Id-al-Adh-ha? #Asairubo #Yoruba,0,yoruba pe nilo ayẹwo wey ti o nuni ti o nuni ti o ní wúlò.,0,yoruba "@user: @user Aku ojumo oni o. Oni a san wa ju ana lo lase Edumare.""""""""""""""""Àṣẹ o! :) #yoruba",0,yoruba "Ẹgbẹ́ òṣèlú APC ní àwọn kábámọ̀ ìdójútì ńlá tí àwọn jàǹdùkú náà kó bá Ààrẹ Buhari Okiki kan ni ọjọ Aje nipa ipolongo idibo ti aarẹ Muhammadu Buhari pẹlu ẹgbẹ oṣelu rẹ, iyẹn APC ṣe ni ilu Abẹokuta. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Okiki to kan kii ṣe tori pe aarẹ lọ ṣe ipade ipolongo ibo nibẹ nitori omilẹgbẹ irufẹ eto ipolongo ni aarẹ ti gbe ṣe lati igba ti o ti bẹrẹ ilepa fun saa keji gẹgẹ bii aarẹ orilẹede Naijiria. Amọṣa ohun to mu ki eyi ṣaraọtọ ni ti yanpọnyanrin to waye, iyẹn bi awọn kan ṣe bẹrẹ si ni ju oko atawọn nnkan miran ti ọwọ wọn ba ba, lu awọn aṣaaju ẹgbẹ oṣelu naa ninu eyi ti aarẹ paapaa ko gbẹyin nibẹ. BBC Nigeria 2019: Lekan Kingkong ní a kò fẹ́ ìtàsílẹ̀ àti ikú ọ̀dọ́ lásìkò ìbò Eleyii ti ko tii ṣẹlẹ rii lati igba ti aarẹ ti bẹrẹ ipolongo rẹ kaakiri orilẹede Naijiria. Ibeere ti ọpọ n beere bayii ni pe, niwọn igba to jẹ pe gomina Amosun to ni aawọ pẹlawọn eekan ẹgbẹ oṣelu naa kan, lawọn eeyan n tọka si gẹgẹ bii eku ẹda to da rukerudo naa silẹ, ṣe ẹgbẹ yoo da sẹria fun? APC ni sẹria to tọ yoo wa fun Amosun Ninu atẹjade kan ti alukoro ẹgbẹ oṣelu APC, Lanre Issa-Onilu fi sita ni ọjọ Iṣẹgun, ẹgbẹ oṣelu APC ""yoo gbe iwa aṣemaṣe naa yẹwo lati gbe igbesẹ to ba yẹ ni kete ti idibo ba pari"". O ni ẹgbẹ APC kabamọ iwa naa, eleyii to ni gomina Amosun ṣe agbatẹru rẹ atipe, ko si aniani kan lori agbara ẹgbẹ oṣelu ati iwa ọmọluabi gẹgẹ bii iwe ofin ẹgbẹ oṣelu APC ti ṣe laa kalẹ fun gbogbo ọmọ ẹgbẹ lai yọ ẹnikẹni silẹ.",0,yoruba "Eyi lo mu ki awọn asaaju ẹgbẹ awakọ meji nipinlẹ Ọyọ, Alhaji Lateef Akinsọla, ti gbogbo eeyan mọ si Tokyo, ati igbakeji rẹ lasiko to fi jẹ alaga, Alhaji Lamidi Mukaila, to tun n jẹ Auxillary, fi foju rinju lẹyin ọdun mẹwa ti wọn fi n bara wọn ja. Gẹgẹ bi iwe iroyin Nigerian Tribune se gbe sita, Tokyo lo kọkọ pe Auxillary lori aago lẹyin ọdun mẹwa ti igbakeji rẹ naa, ti yẹ aga mọ nidi, ti Lateef Salakọ Eleweọmọ si di alaga. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Iroyin naa ni deede aago marun kọja isẹju meje ni irọlẹ ọjọ Aiku, ni Auxillary ati ikọ rẹ gunlẹ si ile Tokyo, ti wọn si ki wọn kaabọ tilu tifọn, ki awọn mejeeji to wọle lọ se ipade bonkẹlẹ alatilẹkun mọri se. Amọ ki wọn to gbe ilẹkun ti, ni Auxillary ti sọ fun ọga rẹ atijọ pebaba ni baba rẹ yoo maa jẹ lọjọkọjọ, tori Tokyo si ni baba awọn ọmọ ẹgbẹ ọlọk ero nipinl Ọyọ. Aṣọ òkè: Alákọ̀wé ní ọ̀nà láti wá oúnjẹ fáwọn tó ń ṣe aṣọ òkè ló ṣún òun débẹ̀ ""Inu ile yii ni gbogbo ọmọ ẹgbẹ ọlọkọ ero, boya alaaye ni abi oku ti bẹrẹ, ko sẹni to lee sẹ lori eyi. Inu mi si dun pupọ nigba ti ẹ pe mi lana ọjọ Satide."" ""Emi ko ni ohunkohun kankan lati fi tako yin, dipo bẹẹ, mo ri gbogbo ohun to ti sẹlẹ lati ẹyin wa gẹgẹ bii irubọ ti a gbọdọ se lati mu ki ẹgbẹ wa lọ siwaju. Abẹyin la ti bẹrẹ, mo si fẹ́ fun yin ni ọwọ rẹ.""",0,yoruba òní.. Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "lòdì Òyó. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba "Nígbà tó kún jú, àwọn ènìyàn ni ó pa Bàbá lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.",0,yoruba Ìlú Ọ̀yọ́ jẹ́ ilẹ̀ agbègbè tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò.,0,yoruba Mason Greenwood: Ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Man U dá Greenwood dúró lẹ́yìn tí ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ sọ pé ó lu òun,0,yoruba "Ọmọ Nàìjíríà lápapọ̀, ẹ bá jẹ́ kí a mú tiwa tí ó dáwà gedegbe gbàngbà sí àṣà ilé ayé mìíràn lò kí ìlọsíwájú tòótọ́ ba dé bá wa. #OmiInira57",0,yoruba Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó ṣe pàtàkì. (Item 16),0,yoruba "Nítorí wípé ọ̀pọ̀ òjò ló ti rọ̀, tílẹ̀ ti fà mu. Ọ̀pọ̀ omi ló sì ti gba abẹ́ afárá kọjá. Àwọn kan lọ wọn ò padà wọlé. Òṣùbà rẹ Ọlọ́run.",0,yoruba kí lárúbáwá àti ọ̀rẹ́ rẹ̀ ìgbàgbọ́ tóó dé ni olúwa ọlọ́runọlọ́hun elédùmarè ti wà pẹ̀lú wa èèbó kọ́ ló kó ọ̀rọ̀ wọ̀nyí wá o,0,yoruba sùgbón a tún le so wípé wèrè la fi ń wo wèrè,0,yoruba "ti o nuni ti o nuni ti o nuni ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Nitori eyi, ara eni ni nfàn ojú kakaaki.",0,yoruba "a ní láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba ayin. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa iṣẹ́: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba "àwọn ọmọ lẹ́yìn rẹ̀. Ìdí èyí ni láti fi àjùlọ Ṣàǹgó hàn, nínú ìjọba Ọ̀yọ́. ẸNI ỌJÀ àti ÌYÁ ILÉ MÒDE kéré nínú ipò sí, ÌYÁ ILÉ ORÍ àti ÌYÁ MỌLÉ.",0,yoruba "àìlẹ̀, Ọba ri A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..",0,yoruba "Legiiti ni, confam! 'Bí mo ṣe rí orúkọ mi ‘MC Remote’ rèé o!'",0,yoruba "ìlú. Nitori eyi, ara eni ni nfàn ojú kakaaki.",0,yoruba "Ni ilu ibi Wolii Temitope Joshua to di oloogbe ti wọn si n ṣe eto isinku rẹ lọwọ, awọn ara ile rẹ kan ṣi n sọ pe ko dun mọ awọn bi wọn ko ṣe wa sin oku rẹ sile. Awọn iyawo ile tilẹ ni awọn gbera lọ si Eko lati lọ bere pe bawo ni eto yoo ṣe jẹ ṣugbọn wọn ko jẹ ki awọn ri iyawo Wolii Joshua. Àdánù láéláé ni fún wa tí wọn kò bá sin òkú T.B Joshua sí ìlú abinibí rẹ̀ - Ọba Arigidi-Akoko Àwòrán bí ó ṣe ńlọ rèé níbi ìsìnkú TB Joshua lónìí Wo àwọn gbajúmọ̀, òṣèré tó lọ sí ibi ètò ìsìnkú Temitope Joshua Ìtàn ayé TB Joshua tó lo ọdún kan àti oṣù mẹ́ta nínú ìyà rẹ̀ Arigidi-Akoko kan gógó torí ikú TB Joshua 'Ẹ má jẹ́ kí òkú ọmọ mi ráre o ìjọba! Ẹ gbée fún mi kí n lọ sin ín - Ìyá ọmọ ti wọ́n pa ní ìwọ́de Yoruba Nation Amọṣa wọn o ri inu bi, wọn ṣi gbagbọ wipe bi wọn ṣi sin in si ilu eko, bo ba to ọgọrun ọdun, wọn yoo si gbe e wa sile ni ilu ibi rẹ tii ṣe Arigidi-Akoko. 'Ẹ má sọ pé lọ́balọ́ba kó sọ̀rọ̀ lórí ìkọlù Sunday Igboho, Inú wa kò dún sí ìjọba' Mò ń rán “suit” tó ta lẹ́nu wọ́n sì gba tèmi àti ìyàwó mi gidi nínú iṣẹ télọ - Odi ọkọ àtìyàwó A ti ń rán ọ̀pọ̀ ọ̀daràn lọ sọ́dọ̀ Ọlọ́run láti lọ jẹ́jọ́ ẹ̀ṣẹ̀ wọn - Ólórí iléèṣẹ́ ológun tuntun",0,yoruba IFA ORISHA NLA... 🙏👌 👏👏👏 👍❤️ 💯💗💗💗💗 ifaokan.fashola #ifá #orisha #orunmila #oshun #historia #black #yoruba #oduduwa #followmee #followus #follownow #likeforlikeandfollow #likeme #likeplease #liketolike 👍👍💯💗👌 https://t.co/uui4rjKntG,0,yoruba ìṣẹ̀ṣe ló bí ọ̀làjú àti àṣà ìgbàlódé olórí ẹyẹ mà rè é ẹyẹ ògòǹgò ara ìṣẹ̀ṣẹ làṣà ìgbàlódé òní ti yọ,0,yoruba "Omo @user Sade fe ki @user so ijoba Nijeria di OyeIdile, O fariga pe @user o pin ipo kan Iya oloja https://t.co/dnLtCg0uCo",0,yoruba Alfa Sule: Ọmọdé tí mò kọ́ ní lẹ́sìnì ló fún mi ní ìmísí àgbékalẹ̀ eré oníjó,0,yoruba Ìyá mú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa òkè: ti o ní wúlò.,0,yoruba Àwòrán : Àwòrán tí wọ́n yà nínú fídíò YouTube ilé - ẹjọ́ gíga jùlọ ti Brazil .,0,yoruba ooré níwọ̀n àánú lérè,0,yoruba àwọn yorùbá a máa ní ìkọ́ kan kì í kọ́ bálá ìkọ́ kan kì í kọ́ bàlà ìkọ́ kan kì í kọ́ ọmọ ejò lẹ́sẹ̀ ǹjẹ́ ó lè sọ ohun tí à ń pè ní bálá àti bàlà,0,yoruba Kizito Mihigo: Akọrin tó fẹ́ lọ darapọ̀ mọ́ ìkọ̀ ajìjàgbara gbẹ̀mí ará rẹ̀ làhàmọ́,0,yoruba yi gbe ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò.,0,yoruba "Bàbálòrìṣà ti pa ewúrẹ́ sí Yemọja. Ó ku ẹyẹlé, ekuru àti ègbo. #YemojaFestival https://t.co/g76aQmjNWH",0,yoruba oníṣẹ́ ìṣẹ́ ni a ní nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ àti ìbi tí wọn wà.,0,yoruba a ji ire bi iba akoda iba aseda iba awon to ni aye o,0,yoruba "Òyó. Nitori eyi, ara eni lo ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba "RT @user: Alakikanju, ọlọ́pọlọ pípé àti olódodo ọ̀dọ́mọdé ni Yẹmí jẹ́ nínú ìtàn àròsọ yìí tí Kọ́lá Àkínlàdé kọ. Kíni ojú rẹ̀ rí nípa…",0,yoruba ọkunrin a yi fi ti o nuni ti o dara.,0,yoruba Ibi-ìkọ̀kọ̀,0,yoruba iléésẹ́ radio nigeria sèlérí ìdàgbàsókè bá àwùjọ,0,yoruba àwọn oníṣẹ́ ìṣẹ́ ni ohun tí ó wáyé.,0,yoruba "Ní 1795, ìdá mẹ́ta ọkọ̀ ojú omi t'ó ńbẹ ní Liverpool ní ń kó ẹrú. #OIANUK",0,yoruba Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọmọ lo ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "Àti ìmupara àti àmupara, kò sí'yàtọ̀. Ì & À; here is state of drinking to stupor; ì-mu-pa-ara | à-mu-pa-ara (stoned/drunk) @user",0,yoruba "Nitori eyi, ara eni lo ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba "Inú wa dùn púpọ̀ láti gba ẹ̀bùn ìwé yìí láti ọ̀dọ̀ @user, ẹni tó jẹ́ Director, Yorùbá Language Proficiency Programme ni EACOED l'Ọ́yọ̀ọ́. Gbédègbẹyọ̀ jẹ́ iṣẹ́ àtàtà, ò sì wú ni l'órí jọjọ. #Atelewo #Gbedegbeyo #Yoruba https://t.co/DBci6DBY9U",0,yoruba "Eto tuntun ti BBC Yorùbá já lójú loni ni a pè ni: Ìròyìn Kàyééfì ti BBC Yorùbá. Eto yii ni a o fi maa gbe àwọn iṣẹlẹ to gbẹnután, to ka ni láyà, to yanílẹnú wo káàkiri agbaye bẹrẹ lati Naijiria. Lọsẹ yii, ìlú Igbódìgò ni Okiti Pupa nipinlẹ̀ Ondo ni BBC Yoruba ti ri Kayeefi yii o. Nibẹ ni a ti ri Deji Adenuga ti awọn agbofinro n gbe lọ sile ẹjọ fún pe o dáná sun ọmọ meje ati iyawo rẹ ati ọkọ ẹgbọn iyawo rẹ mọle. Àníyàn ìfẹ́ laarin Deji Williams Adenuga ati Titi Sanumi lo gba ẹ̀mí ọmọ Titi kan, ọmọ Jumọkẹ, to jẹ ẹgbọn Titi mẹfa ati ọkọ Jumọke. Lẹyin ti Titi ko sinu ilé Deji tan lo gbọ pe Deji ti pa iyawo akọkọ rẹ nitori #450, 000 tẹlẹ. Nigba ti BBC bi Deji leere o ni oun ṣeeṣi gún ìyàwó oun àkọ́kọ́ pa nítorí #450,000 ni. Eyi lo mu Titi maa fẹ fi ọgbọn já Deji silẹ. Ni Deji ba fọnmu pe oun ko gba. Ti ọrọ fi ba ẹyin yọ ti Deji lọ sun gbogbo ẹbi mọle. BBC Yoruba ṣe iṣẹ iwadii iroyin yii de gongo ti a fi ba ọpọlọpọ ero to nii ṣe pẹlu iṣẹlẹ yii sọrọ. Deji Adenuga funra rẹ, Iya Titi, Jumọkẹ, ẹgbọn Titi, Dokita to n tọju Titi, Oga ọlọpaa ti ẹjọ naa wa lọdọ rẹ, Oba ilu Igbodigo, Oba ilu Deji to ti sẹ̀ wá, àwọn ara ilu ati alafojuri ti ọrọ naa ṣoju wọn atawọn mii ni a ba sọrọ tan ki a le fidi okodoro ọrọ yii mulẹ. A fi ki Olorun maa ṣo wa nibi ogun ni iṣẹlẹ yii jẹ. Ọpọlọpọ lo n gba imọran pe asiko ti to ki a pada sidi awọn aṣa Yoruba to fini lọkan balẹ, bii ti iwadii ṣaaju igbeyawo ti ẹbi afẹsọna maa n ṣe. Pataki igbesẹ iwadii ninu igbeyawo iran Yoruba ni ki obi ọkọ ati iyawo ṣe iwadii lẹyin ifojusode ati iṣẹ alarinna. Iwadii yii lo maa fihan ẹbi iyawo awọn nkan to yẹ ki wọn mọ nipa ọdọmọkunrin to fẹ fẹ ọmọ wọn ati iru ẹbi to ti jade wa.",0,yoruba "àwọn iṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba lọ. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìṣẹ̀: ti o ní wúlò.,0,yoruba RT @user: @user ojumo AYO ati idunnu lo mo wa loni. Ire Ojo oni yio je ti gbogbo wa o. Amin.,0,yoruba "Àjọ̀dún àwọn òṣìṣẹ́ : Abẹnugan ilé - ìgbìmọ̀ asojú rọ òṣìṣẹ́ láti tẹramọ́ isẹ́ Abẹnugan ilé - ìgbìmọ̀ asojú lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà , Femi Gbajabiamila , ti gbósùbà fún àwọn òṣìṣẹ́ orílẹ̀ èdè yìí bí wọ́n ṣe ń darapọ̀ mọ́ àwọn akẹgbẹ́ wọn láti sàmìsí ayẹyẹ àjọ̀dún àwọn òsìsẹ́ lágbàáyé .",0,yoruba "Eniyan 330 Millionu lo n lo oju opo ikansiraẹni Twitter Jack Dorsey to jẹ ọga ile iṣẹ naa ni o yẹ ki awọn eeyan ṣiṣẹ tọ ki wọn lee dii ilumọọka sọ pe yatọ si bi wọn ti ṣe n fowo ra idanimọ pẹlu ipolongo ti wọn n san owo fun. ""Ipolowo loju opo ayelujara lagbara gaan ti a si maa mu anfaani wa fawọn to n polowo ọja ṣugbọn iru agbara bẹẹ le ṣakoba fun iṣe oṣelu'' Ikede fifofin de ipolowo yii ti n mu iwoye ọtọọtọ wa paapa julọ fawọn to fẹ kopa ninu idibo aarẹ ilẹ Amẹrika to n bọ lọdun 2020. Brad Parscale, to jẹ oludari ipolongo aarẹ Donald Trump ni ọna a ti pa awọn alatilẹyin aarẹ Trump lẹnu mọ ni igbesẹ yii. Ṣugbọn Bill Russo to n gbẹnusọ fun ipolongo oludije Joe Biden ti ẹgbẹ Democrat sọ pe ''Bi a ba n wa owo lọ taa pade iyi lọna, owo ko le bori'' Ofin to de ipolongo yi yoo fẹsẹ mulẹ lọjọ kejilelogun oṣu Kọkanla ọdun 2019 ti wọn yoo si fi ẹkunrẹrẹ iroyin nipa rẹ sita lọjọ kẹẹdogun oṣu Kọkanla. Ipa wo ni yoo ni lagbo oṣelu Naijiria? Kayode Ogundamisi to jẹ onwoye nipa oṣelu Naijiria ṣalaye fun BBC pe igbeṣẹ yi bojumu lati le koju iroyin ofege eleyi tawọn oloṣelu a maa saba lo lasiko ipolongo idibo. ''Bi a ko ba gbagbe pe aṣiri tu laipẹ bi ile iṣẹ Cambridge Analytica ṣe n ṣagbatẹru ipolongo iroyin ofege lasiko idibo eleyi ti o fẹ ṣakoba fun idibo Naijiria lọdun 2015'' Wo ọna ti o le gba lati fi daabo bo ara rẹ lori Facebook. O tẹsiwaju pe ''Ti a ko ba dẹkun iru iwa bayi, awọn kan yoo kan maa pawo ipolongo lalai bikita ipa ti yoo ni lori ara ilu. Kayode ni ""Inu mi dun si oun ti Twitter fẹ ṣe yi'' Ẹwẹ oju opo kan lara awọn to n figagbaga pẹlu Twitter, Facebook naa ti kede pe awọn yoo fofin de ipolongo to ni ṣe pẹlu oṣelu loju opo ti wọn naa. Àwọn ọkùnrin tó wà nínú ayé wa gbúdọ̀ bọ̀wọ̀ fún wa - Adarí FIN Mark Zuckerberg to jẹ ọga ileeṣẹ Facebook lo sọ ọrọ yi fawọn oniroyin. O ni oun o lero pe o yẹ ki awọn ileeṣẹ aladani maa tọ pinpin iroyin oṣelu tawọn eeyan n gbọ nitori owo. Àṣà àti ìgbàgbọ́ Yorùbá ni pé òbí wọn máa ń padà wá sáyé",0,yoruba ìdílé. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa àwọn ènìyàn: ti o lẹ.,0,yoruba ọdún shakespeare nlọ lọ́wọ́ ni àwọn eré orí ìtàgé mẹ́tàdínlógójì ní èdè mẹ́tàdínlógójì ni wọ́n gbé wá,0,yoruba "Aarẹ ile aṣofin agba Naijiria nibi to ti joko ti awọn ọkunrin meji lara awọn to lowo julọ ni Naijiria,Aliko Dangote ati Jim Ovia. Ajọ ẹlẹyinju anu ilẹ Gẹẹsi ni Oxfam Charity lo fi abajade yii sita lọjọ Iṣẹgun. Ninu iwadi naa, wọn ni owo to wa lọwọ awọn ọkunrin mẹta to lowo julọ ni ilẹ Afrika, kọja ti awọn ẹgbẹta le ni aadọta miliọnu alaini to wa nilẹ naa. Abajade iwadi naa, ti wọn pe orukọ rẹ ni ''A Tale of Two Continents'' ṣafihan bi iṣẹ ṣe n lọ soke ni Naijiria ati ilẹ ni Afrika, ti aiṣedeede ọrọ aje si tun n da kun iṣoro kikoju aini nilẹ naa. Bakannaa ni esi iwadi Oxfam tun tọka si bi ọrọ awọn to lowo julọ ni Afrika ṣe n pọ si, ti iṣẹ oun aini si n lọ si oke laarin awọn alaini. ''Ilẹ Afrika n lewaju laarin awọn ilẹ agbaye gẹgẹ bi ibi ti oṣi oun iṣẹ ti n peleke. Bi iye awọn eeyan to n na owo ti ko to dọla meji lojumọ ṣe n dinku ni ilẹ Asia, bẹẹ lo n pọ si ni Afrika'' Ọga agba ni Oxfam, Winnie Byanyima ni ''Afrika ṣetan lati dagbasoke ṣugbọn ko le ṣeeṣe ti awọn olori ko ba lẹmi lati gbaruku ti awọn to fẹ ṣiṣẹ mu agbega ba araalu dipo awọn olowo'' Esi iwadi naa ṣe agbekalẹ ohun ti awọn orileede Afrika n ṣe lati mu opin ba iṣẹ oun oṣi. Awọn aworan to ṣafihan aini bayi pọ kaakiri awọn ilẹ Afrika Orileede South Afrika ati Namibia lewaju ninu ilakaka yii, ti Naijiria si ru póò nilẹ Afrika ati lori akasọ agbaye. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Awọn nnkan miran ti iwadi naa sọ ni pe:",0,yoruba àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa iṣẹ́: ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó jáde.,0,yoruba "tí a kọ eḳọ nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Nitori eyi, ara eni lo ni.",0,yoruba Bobrisky: Ìrora iṣẹ́ abẹ ìdí náà pọ̀ àmọ́ n kò kábàámọ̀ pé mo ṣe é,0,yoruba Iṣẹ́ àtúnṣe bẹ̀rẹ̀ ní 2014 .,0,yoruba "ó pa Ọmọ lo ni ìgbà mi owó àkokò, Baàlè ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé.",0,yoruba "Iṣẹlẹ naa ṣẹ ni agbegbe Oshodi Oke ni Ogijo nibi ti Shukurat ti lu Azeem Olufowobi ọmọ dun marun un pa. Ọwọ ọlọpaa tẹ afurasi yii ni nkan bii ago mejila abọ oru ọjọ aiku tii ṣe ọjọ keji oṣu keji ọdun 2020 lẹyin ti awọn ara adugbo kan ta awọn ọlọpa ẹkun ti Ogijo lolobo pe Shukurat gba nkankan mọ ọmọ naa lori. Eyi jẹ ki ọmọ naa ni ọgbẹ lori to si pada fa iku rẹ. Iroyin taa gbọ ni pe kiakia ni arabinrin naa ati ọkọ yara gbe oku ọmọ naa lọ si Ajah nilu Eko nibi ti wọn yọlẹ bo o mọlẹ si. Kete ti ọrọ naa de agọ Ọlọpaa ni DPO Suleman Baba Muhammad ti ko awọn ikọ ọtẹlẹmuyẹ rẹ jọ lati lọ si ile to ti ṣẹlẹ ti wọn si ri i pe awọn tọkọtaya naa ti n ko ẹru wn kuro ni adugbo ọhun ni wọn ba tete mo irin si wọn lọwọ. Iwadii to ti waye ṣaaju fi han pe o ti pẹ ti arabinrin naa ti n fiya jẹ ọmọ yii tipẹ, iya to bi i ti fi baba rẹ silẹ lori aigbraẹniye. Sugbọn lọjọ buruku eṣu gbomi mu yii, nkan to wuwo ni arabinrin naa jan mọ ọmọ ọhun lori eyi to si fọ ori ọmọ ttti to fi fa iku rẹ. Arabinrin naa ati ọrẹ rẹ sare bẹ nọọsi to kọkọ ṣetọju alaisan naa to si sọ ohun to ṣẹlẹ fun ọkọ ati iyawo ọhun pe ko parọ m nkan mii nipa ohun to fa iku oloogbe naa ṣugbọn o kọ tori pe o ni o lodi si ofin iṣẹ oun. Ọkọ atiyawo naa Ayuba ati Shukurat Olufowobi ti wa ni agọ Ọlọpaa bayii ti wọn n fi ọrọ wa wọn lẹnu wo. Ẹwẹ, kọmisana ọlọpaa Keneth Ebrimson ti paṣẹ pe ki wn tete gbe ẹjọ awọn afurasi mejeji lọ si ẹka to n ri si ipaniyan ni ẹka iṣewadii ati ọtẹlẹmuyẹ fun iwadi kikun ati fifi wọn jofin.",0,yoruba "Ìjọba bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ àtúntò ọlọ̀pàá Olúbádámọran lórí ètò ààbò Babangida Munguno ló sísọ lójú ọ̀rọ̀ náà lẹ́yìn ìpàdé àwọn aláṣẹ ìjọba, èyí ti adele ààrẹ ọjọ̀gbọ́n Yemi Osinbanjo ní ile ààrẹ l'Abuja lónìí. Mungono sàlàyé pé Ìbrahim Idris tó jẹ́ ọgá àgbà ọlọ́pàá, ní yóò jẹ́ alága ìgbìmọ tí àwọn asojú ẹkùn mẹfẹ̀fà yóò wà níbẹ̀. Ó tọ́ka síi pé Nàìjíríà ń koju àwọn ǹkan to lòdí pàápàá jùlọ lórí ètò ààbọ. Olùbádàmọ̀ràn pàtàkì fún ààrẹ tún fi kún pé ìjọba àpapọ̀ ń mójú to àwọn ìpèníjà míràn tó ń jẹyọ láti ẹ̀yìn odi orílẹ̀-èdè yìí. Gẹ́gẹ́ bó ṣe sọ, àwọn ìdojúkọ ètò ààbò yìí ní gbogbo ilé iṣẹ́ elétò ààbò ń ṣe àtòpọ̀ rẹ̀, o fi kún pé àwọn ìgbìmọ míràn yòó tún dìde láti máa ṣe àbẹwò láti rẹyin gbpogbo ìdojukọ lori ààbo Ìdìbò 2019: INEC fẹ́ ná N6bn lórí ounjẹ fún àwọn ọlọ́pàá Àjọ́ eleto idibo INEC ni awọn yoo na N6bn sori ounjẹ ti awọn ọlọpàá ti yoo kopa ninu eto idibo gbogboogbo 2019 a jẹ. Alaga INEC, ọjọgbọn Mahmoud Yakubu ni o sọ bẹẹ nigba ti o gbe eto iṣuna idibo 2019 ti ajọ naa gbé siwaju ile igbimo aṣojuṣofin ni Abuja l'Ọjọru. Awọn aṣofin naa ti iye owo ọhun ko ba lara mu ti ni ajọ naa gbọdọ ṣalaye bi yoo ṣe na owo naa. Awọn gomina na N2trn ni ọdun mẹwaa Bakan naa, igbimọ awọn gomina Naijiria ti ni awọn gomina ipinlẹ mẹrindinlogoji orilẹ-ede yii na N2trn ni aarin ọdun mẹwaa lati ṣe iranlọwọ for ileeṣẹ ọlọpaa. Eto idibo 2019 ti n kan ilẹkun Agbẹnusọ igbimọ naa, Abdulrazaque Barkindo, lo sọ bẹẹ ni Abuja ni ọjọ Iṣẹgun, nibi to ti ṣalaye pe iwadii ẹka igbimọ naa lo fi ọju iye owo naa lede. O ni, ""Ni ọdun 2015, Ipinlẹ Eko nikan, labẹ iṣakoso Gomina Akinwunmi Ambode, na N4.765bn lati ran ileeṣẹ ọlọpaa lọwọ."" 'Ọ̀lọ́wọ́ òsì kọ́ndọ́rọ́' INEC yoo sun miliọnu meje kaadi idibo",0,yoruba "RT @user: Ori ni, Ota wa rope Ogun.. Eni oluwa ba tele, bi ensote enyorayin leenu..@user @user",0,yoruba pa Ọba lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó ga.,0,yoruba dídì. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí.,0,yoruba "ÌKÓMỌ JÁDE Lẹ́hìn ọjọ́ mẹ́sàán tí a bá bímọ ọkùnrin, ni a má sọọ́ lórúkọ. Lẹ́hìn ọjọ́ méje tí a bá bí ọmọ obìnrin, ni a ma sọọ́ lórúkọ. Ìbejì tí ó jẹ́ akọ àti abo, ọjọ́ mẹ́jọ tí wọ́n bá bí wọn, ní wọ́n ma sọ wọ́n lórúkọ.",0,yoruba Ìbàdandun ni ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn. (Item 80),0,yoruba A rọ àwọn ọ̀dọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú náà láti kún fún ìṣọ́ra ní ojúu pópó .,0,yoruba "@user Èèyàn mi, mo wà jàre. A kú ìgbélé náà, Èdùmàrè á kó wa yọ",0,yoruba "nípa àlùfáà. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Nitori eyi, ara eni ni nfàn ojú kakaaki.",0,yoruba nilo ayẹwo wey ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ àti ìbi tí wọn wà.,0,yoruba Ọ̀pọ̀lọpọ̀ aṣàtìpó to sá kuro torí ogun Rohingya lo ṣì ń gbé nínú ìbànújẹ́ àti ẹ̀rù báyìí tó jẹ́ ọdún kan lẹyin iṣẹlẹ naa. Ọmọ ọdun mẹẹdogun yii sọ ohun ti oju rẹ n ri pẹlu ẹ̀rù to n baa lori oyun to ni fun baba arúgbó to fẹ ẹ nibudo aṣatipo.,0,yoruba àṣà tó lọ kóbá wa láìmọye ọ̀nà,0,yoruba "Omoluabi wa ni èkó ìyálóde lo je ti ibile. Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.. Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìwà: ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Bàbá lo ni ẹ̀ká àwẹ eyti o gbe lori iwa rere.,0,yoruba "Ninu iwe asẹ kan ti ajọ naa fi sita lorukọ alaga wọn, Yakubu Mahmood, wọn ni igbesẹ lilo ilana yii lati fi gba fọọmu pada jẹ ọna lati mu adinku ba ewu itankalẹ arun Covid-19. Bẹẹ naa ni ilana yi yoo kan titọ pinpin iye owo ti awọn ẹgbẹ oselu ba naa fi se ipolongo, ati iye ti wọn na lati fi orukọ awọn alamojuto eto idibo, ati iwe orukọ awọn asoju ẹgbẹ ransẹ. Ajọ naa tun sọ pe awọn yoo mu adinku ba iye awọn ti yoo mojuto eto idibo nipasẹ wiwo awọn to sẹ iṣẹ to munadoko ninu eto idibo ti wọn ti se kọja. ''Gbogbo ilana yi wa lati mu adinku ba fifi ara kan ara ẹni, eyi to le mu ki awọn eeyan ko arun Covid-19'' Ba kan naa ni awọn oludibo ati awọn miran to n kopa ninu idibo naa gbọdọ wọ ibomu ti wọn yoo si ya ẹnikẹni to ba safihan apẹẹrẹ Covid- 19 sọtọ. Ẹwẹ, ajọ naa ti la ilana kalẹ fun eto idibo gomina ni ipinlẹ Edo ati Ondo to fi mọ idibo awọn asojuile asofin. Agbẹnusọ ajọ naa, Aliyu Bello ni idibo awọn ipinlẹ naa yoo waye ni osu Kẹsan ati osu Kẹwa. ''Ki idibo to bẹrẹ awọn eeyan ni lati jinasirawọn lati le fi dẹkun itankalẹ arun naa. Bakan naa ni ajọ wa yoo pese eroja ipawọ 'hand sanitizer', ti ijiya yoo si wa fawọn oludibo to ba tapa si ilana yi.'' Àjọ INEC ti yọ orúkọ ẹgbẹ́ òṣèlú 74 kúrò l'ágbo òṣèlú Nàìjíríà Ajọ eleto idibo Naijiria, National Electoral Commission (INEC), ti yọ orukọ ẹgbẹ oṣelu mẹrinlelaadọrin kuro ni Naijiria. Ọga agba INEC ati awọn miran nibi ipade ti ikede naa ti waye. INEC kede pe marundinlọgọrin ni awọn ẹgbẹ oṣelu ti ko koju oṣuwọn, ṣugbọn ẹyọkan lara wọn, Action People Party (APP) gbe ajọ naa lọ si ile ẹjọ, to si gba aṣẹ to ka INE lọwọ ko lati yọ orukọ rẹ. Alaga ajọ naa, Mahmood Yakubu to kede igbesẹ naa fun awọn akọroyin nilu Abuja sọ pe yiyọ ti wọn yọ orukọ wọn kuro wa ni ibamu pẹlu ofin Naijiria. Awọn ẹgbẹ oṣelu ti ko si l'agbo mọ ni wọn yii: Orukọ awọn ẹgbẹ oṣelu to wa bayii ni yii: O sọ pe awọn ẹgbẹ oṣelu naa ko koju oṣuwọn to, wọn ko si ni gbogbo nkan ti ajọ naa n beere lọwọ wọn. Pẹlu igbesẹ ti INEc gbe yii, ẹgbẹ oṣelu mejidinlogun pere lo ku. Kini awọn nkan ti INEC n fẹ, ti wọn ko ni? Ṣaaju eto idibo gbogboogbo ọdun 2019, ẹgbẹ osẹlu mọkanlelaadọwa (191) lo wa ni Naijiria. Ẹyọkan tun darapọ mọ wọn lẹyin eto idibo na, eyi to sọ ọ di mejilelaadọwa (192). Ofin Naijiria fun ajọ INEC ni agbara lati yọ orukọ ẹgbẹ oṣelu yoowu kuro l'agbo oṣelu, ti wọn ko ba ni awọn amuyẹ wọnyii: Ṣugbọn ṣa, idibo sipo gomina ni ipinlẹ Ondo ni INEC kede pe yoo waye ni ọjọ kẹwa, oṣu Kẹwaa, ọdun 2020. Bakan naa ni ti ipinlẹ Edo yoo waye ni ọjọ kọkandinlogun, oṣu Kẹsan, ọdun 2020. Awọn atundi ibo kan yoo waye ni ẹkun idibo mẹta nitori iku awọn aṣofin kan ni ipinlẹ Niger, Kwara ati Sokoto. Ọkọ kẹrinla, oṣu Kẹta, ọdun 2020 ni gbogbo atundi ibo naa yoo waye.",0,yoruba "Olojoibi@user kiogbo, kioto yiye ni ye eyele riro nii ro adaba lorun, towo tomo tire gbogbo ko fi Ile re se ibugbe. Igba odun odun kan",0,yoruba lẹ̀ẹ̀ní nípa iṣẹ́: ti o ní wúlò fún gbogbo.,0,yoruba "Yoruba ni eeyan kii daradara ko ma ku sibi kan, bẹẹ si ni a kii waye, ka ma ni arun kan lara. Bẹẹ lọrọ fẹ ẹ ri pẹlu abẹrẹ ajẹsara Oxford AstraZeneca to wa lati dena arun Coronavirus, eyi ti wọn ti ko wọ orilẹede Naijiria bayii. Lọwọ lọwọ bayii, ko din ni eeyan ẹgbẹrun mẹjọ to ti gba abẹrẹ ajẹsara naa nilẹ wa, gẹgẹ bi igbimọ amusẹya lori arun Coronavirus se wi. Amọ sa, ajọ naa ni ipinlẹ Kogi nikan ni ẹnikẹni ko ti gba abẹrẹ naa nitori bi isẹ atunse se n lọ lọwọ lori ẹrọ amunkan tutu rẹ, ti wsn yoo ko abẹrẹ naa pamọ si. Amọ nibayii, Kọmisana feto ilera nipinlẹ Eko, Akin Abayomi ti sisọ loju rẹ pe awọn ewu kan wa to rọ mọ gbigba abẹrẹ ajẹsara AstraZeneca naa. Dokita Abayomi ni lootọ ko si ohunkohun to se oun ni ọjọ akọkọ ti oun gba abẹrẹ ajẹsara naa amọ lọjọ keji ni ori n fọ oun, ti ara si tun n ro oun pẹlu. ""Lọjọ keji ni otutu n mu mi, ara n ro mi, ti oju ibi ti mo ti gba abẹrẹ naa si n dun mi amọ mo lo oogun ara riro, mo sere idaraya, ti mo si lọ sun. Nigba ti mo taji, se ni ara mi le koko, ti mo si wa daada."" Kaakiri agbaye, awọn orilẹede kan ti n fofin de gbigba abẹrẹ ajẹsara naa nitori abajade rẹ lara awọn eeyan kan ti wọn lo n mu ki ẹjẹ wọn di. Lọwọ lọwọ, orilẹede Spain, Germany, France, Italy ati Holland naa ti darapọ mọ awọn orilẹede to ti dawọ duro lori fifun awọn eeyan wọn ni abẹrẹ naa. Ohun ti wọn lo sokunfa igbesẹ wọn ọhun ni bi ẹjẹ awọn eeyan kan se n di. Amọ ajọ eleto ilera lagbaye WHO ti kede pe kawọn eeyan mase dẹkun gbigba abẹrẹ ajẹsara naa nitori ko si ewu ninu rẹ. WHO ni ko si ẹri kankan to daju nipa aleebu ti wọn ni abẹrẹ ajẹsara naa ni, eyi to ni se pẹlu ewu ẹjẹ didi. Nibayii, ijọba apapọ ti fọwọ gbaya fawọn araalu pe ko si ewu kankan nidi gbigba abẹrẹ naa. Dokita Shuaib Faisal, tii se akọwe apapọ fun ajọ eleto ilera alabọde ni Naijiria lo fọwọ gbaya bẹẹ pẹlu afikun pe, tori abẹrẹ ajẹsara Oxford AstraZeneca jẹ olowo pọọku, ko tumọ si pe ko pegede to.",0,yoruba iṣẹ́ ṣẹlẹ ni Lagos ti gbogbo eniyan sọ o ṣe pataki. (2008),0,yoruba "àìmọ́. Nitori eyi, ara eni lo ni ọ̀gbọ́n.",0,yoruba Ìlú yorubá lo ni àṣà ìdílé lo je ti ibile.,0,yoruba Ọba fi. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba "Tiwa pẹlu awọn onigbọwọ Ilumọọka olorin nni, Tiwa Savage ni iroyin sọ pe oun ni obinrin akọkọ to ti gba ami ẹyẹ MTV EMA fun olorin ilẹ Afirika to dara ju. #Bum bum war:Yemi Alade tọrọ àforíjìn lọ́wọ́ Tiwa Savage Davido, Falz, Tiwa Savage tàn bí oòrùn ní AFRIMA Bakan naa, o ti ba awọn gbajugba olorin to lokiki kọrin kaakiri agbaye. Tiwa jẹ ọkan lara awọn obinrin ilẹ Afirika to ni ọpọlọpọ ololufẹ orin rẹ to fẹrẹẹ́ to miliọnu meje lori itakun ayelujara. Tiwa Savage Oluwo: Mo lè jẹ Ọba ní Ile Ife Tiwa ni ""afojusun mi to ga ju ni lati fi ilẹ Afirika yangan, nitori naa, inu mi dun gidi gan si ajọṣepọ yii mo si dupẹ lọwọ ẹbi tuntun ti mo wọ yii, UMG. Tiwa ti di olorin to gbayii gan loke okun. Ninu oṣu kejila dun to kọja olorin Chris Martin yan an lati jọ kọrin pọ pẹlu gbajugbaja olorin Beyonce, Ed Sheeran ati Jay Z ni ilu Johannesburgh, South Africa niwaju ero to to miliọnu lọna aadọrin nigba ti wọn ṣe ayẹyẹ iranti ọjọ ibi oloogbe Nelson Mandella O ti wa di ọ̀kan lara awọn agba akọrin Afrobeat l'Afirika pẹlu eyi to ti fun ara rẹ niyi lẹnu iṣẹ to yan laayo ati nilẹ Afirika gẹgẹ bi olorin, oniṣowo, akọni ati iyaleele. Adam Granite to n bojuto ẹka idagbasoke katakara fun ajọ UMG, ni ""a n foju sọna lati ni ajọṣepọ pẹlu Tiwa ati ikọ rẹ lati ran iṣẹ orin kikọ rẹ lọwọ ki o le tan ka gbogbo agbaye tori a rii pe Tiwa ni afojusun to dara"". A kò mọ́ pé wọ́n kẹ́ òògùn olóró sí àbúrò mi l'ọ́rùn Universal Music Group jẹ aṣaaju ninu oniruuru iṣẹ to rọ mọ orin kikọ. Latorii gbigbe orin sita, ṣiṣe alagbata orin kaakiri orilẹede to le lọgọta. Oriṣiriṣi ẹya orin ni wọn ma fi yan olorin ti wn yoo si baa gbe orin sita titi ti wọn yoo fi ṣe agbata rẹ kaakiri agbaye ati lati jẹ ki awọn to fẹran orin wọn tun ni iriri ọtun nipa wọn.",0,yoruba Ó yá ta ń mọ̀ ọ́ o! #Ibeere #Yoruba,0,yoruba modupe temi o mo she ope temi,0,yoruba @user Ẹ ó jèrè iṣẹ́ o. Ẹ kò ní ṣiṣẹ́ dànù lásán.,0,yoruba olùparapọ̀ ri pe jẹ́ pàtàkì wey ti o wulo.,0,yoruba "fi. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Cardi B àti Offset ṣeré pọ̀ lọ́jọ́ Àìkú tó jẹ́ ọgbọ̀n ọjọ́ oṣù kọọ̀kànlá. Obirin naa to jẹ iya ọmọ kan sọ pe yoo pẹ diẹ ki wọn to pin ya pata-pata nitori pe wọn jọ bimọ pọ. End of Instagram post, 1 Lọjọru ni Cardi B sọ eleyi di mimọ lori Instagram to si sọ wi pe oun yoo maa nifẹ olorin Migos oun lailai. Awọn akọrin mejeeji naa jọ kọrin pọ lọjọ Aiku ni ode kan. Ọrọ naa ka awọn eeyan lara lagbaye titi ti orukọ awọn mejeji naa si jẹ eyi ti awọn eeyan n sọ niparẹ ju lori ero ayelujara.",0,yoruba "Ori lo mọ isẹ asela, ibi ti ori wa si n lọ, agba adura ni pe ki ẹsẹ sin wa de ibẹ. Bẹẹ lo ri fun gbajumọ osere tiata kan, Murphy Afolabi Olawale, ẹni ti isẹ tiata ti wu lati kekere, ti kii si se ayaba fun. Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Murphy Afolabi ni oun ko lọ sile ẹkọ girama amọ oun kẹkọọ jade nile ẹkọ fasiti Eko bi o tilẹ jẹ pe awọn onijibiti ti gba oun kọja sisọ ninu iyanju oun lati wọ awọn fasiti kan tẹlẹ. Osere tiata naa ni Araba awo tilu Osogbo, oloye Ifayemi Elebuibon, tii se baba fun oun lo se koriya fun oun lati yan isẹ tiata laayo. Nigba to n sọ awọn ipenija to ni nidi isẹ tiata, Murphy Afolabi Olawale ni oun gbe apoti asọ baba oun fun ọga oun lati sere tiata ni ogun ba de. O wa salaye pe kii dun oun tawọn eeyan ba n fi oun se yẹyẹ pe oun maa n sọ ede ilu oke, ti oun si n fi si pe ṣi. Gbajumọ osere naa fikun pe ede ilu Osogbo ti oun gbe dagba, ni oun n sọ, yoo si nira puọ lati paarọ ahọn oun nigba ti oun de Eko. O wa yan pe awọn osere tiata to fi ere itage bẹrẹ isẹ bii ti oun ni akọsẹmọsẹ, yatọ si awọn osere aye ode oni ti wọn n gbe ẹrọ ayaworan lasan si loju.",0,yoruba "Lọjọ iṣẹgun yii ni awọn mejeeji joko jiroro lori abadofin naa, ti wọn si buwọlu ofin to gbe idasilẹ ikọ alaabo naa silẹ nipinlẹ wọn. Ṣaaju asiko yii ni awọn ijọba ilẹ kaarọ o jiire ati ijọba apapọ ti fẹnu ko si pe, ki awọn ipinlẹ kọọkan pada lọ fi ofin gbe idasilẹ Amọtẹkun silẹ ni ipinlẹ wọn. Yatọ si ipinlẹ Eko ti o mu atunṣe ba ofin to ṣe idasilẹ ikọ alaabo Neighbourhood Watch, ti o ti wa nilẹ tẹlẹ, awọn ipinlẹ to ku ṣẹṣẹ bẹrẹ igbesẹ lati fi ofin de idasilẹ Amọtẹkun lagbegbe wọn ni. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Asọ Amọtẹkun lawọn aṣofin Oyo wọ wa si ile N ṣe ni awọn aṣofin ile aaṣofin Oyo ko anko wọ aṣọ to jọ awọ Amọtẹkun, wa si ile lati le fi ifarajin wọn han lori sisọ abadofin yii di ofin. Bẹrẹ lati olori ile to fi dori awọn aṣofin to ku, bi wọn ti ṣe n wọ dansiki, lawọn miran de gberi ọdẹ sori. Koda agbọpa ile gan ko gbẹyin, ti oun naa si fi asọ amọtẹkun gbe ọpa ile lọwọ, ti wọn si tun wọ ifunpa si apa wọn.",0,yoruba "Ọgbẹni Sowore, to jẹ oludasilẹ ileeṣẹ iroyin Sahara Reporters, jẹ ọkan lara awọn to ṣe agbatẹru iwọde kan ti ẹgbẹ Global Coalition for Security and Democracy in Nigeria, fẹ ẹ ṣe ni ọjọ Aje, ọjọ karun un oṣu Kẹjọ ọdun 2019 ṣugbọn ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe ""ete iditẹ gba ijọba ni iwọde naa."" Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Agbẹnusọ fun ajọ DSS, Peter Afunaya sọ fun BBC pe, awọn lọ ọ gbe oludasilẹ iwọde naa, ti wọn pe 'Revolution Now' ni owurọ ajọ Abamẹta to kọja, nitori pe oun n pe fun iditẹ gba ijọba. Ṣaaju ọjọ naa ni ikọ Coalition for Revolution ti Sowore da silẹ, ke si awọn ọmọ Naijiria kaakiri orilẹede yii lati jade si igboro, ki wọn si beere fun opin si aisi aabo ni Naijiria. Ẹgbẹ naa tun n beere fun ẹkọ ọfẹẹ, ati eto ilera fun gbogbo eniyan, ati eto ọrọ aje to dara. Amọ ajọ DSS ko sọ boya wọn yoo mu ẹnikẹni to ba yọju fun iwọde naa l'ọjọ Aje. Awọn ileeṣẹ iroyin kan sọ pe, agbẹnusọ ajọ DSS, Afunaya sọ pe awọn gbe igbesẹ naa ni ibamu pẹlu ojuṣe wọn l'abẹ ofin.",0,yoruba dànsákì o ọba ajínisáyé mo sùn mo jí sáyé ìwọ lọpẹ́ yẹ o baba gba ọpẹ́ mi o,0,yoruba "Paroparo ni awọn mọṣalaaṣi kan da nilu Eko, lasiko irun Jimọ to yẹ ko waye. Eyi yani lẹnu botilẹjẹ pe ijọba ipinlẹ Eko ti kede pe ki awọn ile ijọsin bẹrẹ sini ṣi pada lati ọjọ Jimọ, ọjọ keje, oṣu Kẹjọ, lẹyin oṣu bi i maarun ti wọn ti ti ilẹkun wọn nitori isede aarun coronavirus. Lasiko ti akọroyin BBC kan de awọn mọṣalaaṣi bi ti Ikoyi ati Lekki lati kirun, titi pa ni awọn ilẹkun ibẹ wa lai si irun Jimọ. Ṣugbọn ṣa, irun Jimọ waye ni awọn mọṣalaaṣi kan. Awọn musulumi nipinlẹ Eko yoo laanfani lati kopa ninu irun Jimọ loni lẹyin nkan bi oṣu mẹrin ti ijọba fofin de akojọpọ lawọn ile ijọsin. Awọn ṣọọṣi naa yoo ṣi pada lọjọ Aiku. Lati oṣu kẹta ọdun 2020 ni ijọba ti ni ki wọn sọ agadagodo sawọn Mọṣalaṣi ati Ṣọọṣi nitori ajakalẹ arun Covid-19. Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu sọ pe igbesẹ ṣiṣi awọn mọṣalaṣi yi jẹ apẹrẹ pe Naijiria n tẹsiwaju ninu idoju ija kọ arun Covid-19. Ṣugbọn ṣa ijọba ni ida meji awọn to ba yẹ ko wa ni aaye ijọsin naa ni awọn yoo faye gba lati jọsin. Bẹẹ ni wọn ni awọn olujọsin gbọdọ tẹle ilana bi wiwọ ibomu,fifọ ọwọ ati ijinasiraẹni lasiko ti wọn ba n kirun. Aarẹ Muhammadu Buhari ti fi ọwọ si afikun ọsẹ mẹrin si abala keji didẹwọ isede coronavirus. Akọwe ijọba apapọ, to tun jẹ Alaga fun igbimọ to n mojuto itankalẹ aarun Covid-19, Boss Mustapha, lo kede eyi lasiko ti o n ba ara ilu sọrọ l'Ọjọbọ. O ni isede to n bẹrẹ laago mẹwa alẹ ṣi wa sibẹ. Mustapha sọ pe igbesẹ yii waye lati le fi idi aṣeyọri ti Naijiria ti n ṣe lori igbogbun ti aarun coronavirus mulẹ. Gẹgẹ bi o ṣe sọ, àwọn ayipada ti yoo kan wa ni pe wọn yoo bẹrẹ si ni ṣi papakọ ofurufu fun irinajo si ilẹ okeere diẹdiẹ, ni ibamu pẹlu awọn ilana to yẹ. Igbimọ amuṣẹya naa sọ pe ki awọn ileeṣẹ baalu to n rinrinajo lọ silẹ okeere, ati awọn alaṣẹ papakọ ọk ofurufu bẹrẹ igbaradi fun ṣiṣi irinajo silẹ okeere. Bakan na ni irinajo ọkọ oju'rin naa yoo bẹrẹ pada. Ṣugbọn ko gbọdọ si irinajo laarin ipinlẹ kan si omiran lasiko isede fun awọn arinrinajo loju popo. Botilẹjẹpe ofin ṣi de awọn ile faaji, ijọba sọ pe oun ti gbẹsẹ kuro lori ofin to de lilọ si awọn ọgba igbafẹ, ṣugbọn ko gbsdọ si ifarakan ara nibẹ. Ko tan sibẹ o, Ọgbẹni Mustapah tun kede pe awọn eero ọkọ baalu labẹle le ma a de si papakọ ọkọ ofurufu ni wakati kan ataabọ ṣaaju irinajo wọn, dipo wakati mẹta ti ijọba kede tẹlẹ. Ṣugbọn ṣa, o sọ pe dandan ṣi ni fun gbogbo eniyan lati maa tẹle awọn ilana ti ijọba la kalẹ. Ìgbìmọ̀ amúṣẹ́ṣe ìjọba àpapọ̀ lórí Covid-19 ti fẹdun ọkan wọn han lori bi itankalẹ aarun Coronavirus ṣe n pọ si laarin awọn to n bẹ nì'jọba. Eyi si ni wọn lo n mu isoro ba eto isejọba ati didaabo bo ilu lọna to yẹ lorilẹ-ede Naijiria. Alaga igbimọ ọhun, to tun jẹ akọwe ìjọba apapọ, Boss Mustapha lo salaye ọrọ yii lasiko ijabọ bi nkan ṣe lọ fun ara ilu to ma n waye l'Abuja lojoojumọ. O sọ ọ di mimọ pe, ṣiṣe ofin konile ogbele tuntun miran le waye lati dẹkun itankalẹ arun yii to n peleke sii. Akọwe ìjọba wa rọ gbogbo ọmọ Naijiria lati tẹle àwọn ilana to yẹ lati dena aarun Coronavirus nitori pe aarun naa ko mọ olowo tabi talaka. Ikilọ alaga yii ko sẹyin bi awọn gomina ipinlẹ lọkan o jọkan, ṣe n lugbadi arun naa ni lọọlọ yii. Laipẹ yii ni Gomina Ondo, Rotimi Akeredolu, Gomina Ebonyi David Umahi ati awọn miran lugbadi aarun naa. Mustapha wa kilọ fun awọn to wa nipo aṣẹ lati sọra nitori gbogbo awọn to ti lugbadi arun laipẹ ba ṣe aisan, eyi yoo di isejọba lọwọ lati seto ilu ati lati daabo bo wọn. ""A rọ gbogbo ọmọ Naijiria lati maa foju s'ọri bi alakan, yala o jẹ olowo tabi talaka. Aarun yii ko bikita ipo ti ẹnikẹni wa, sugbọn igbimọ amusẹya ìjọba ko ni sinmi, lati maa ṣe ikilọ ni igba gbogbo."" Ẹwẹ, Boss Mustapha ni, awọn nkan to ba jẹyọ ni awọn ọsẹ to n bọ yii, ni yoo sọ inu odo ti igbimọ naa yoo da ọrunla si lori pe, boya ki ìjọba kede igbele gbogboogbo miran.. ""A o le sọ nkan ti yoo sẹlẹ lọjọ iwaju sugbọn nkan to ṣe pataki julọ ni pe, didaabo bo awọn ọmọ Naijiria lo ṣe pataki julọ."" ""Lati ṣe eyi, to ba jẹ pe kikede konileogbele lọna abayọ, a o ṣe bẹẹ gẹgẹ. A o gbe abajade iwadi ati ero wa siwaju Aarẹ lati ṣe ipinnu lori aba igbimọ amusẹṣe, nkan to ba sẹlẹ ni ọṣẹ mẹta si asiko yii ni yoo sakawe igbesẹ ti ijọba yoo gbe."" Saaju la ti kede pe awọn asaaju ẹgbẹ ọmọlẹyin Kristi (CAN) ti n sọrọ lori aṣẹ ti ìjọba apapọ pa pe, awọn ọmọde ati arugbo ko gbọdọ lọ sile ijọsin. Nigba ti wọn n ba BBC Yoruba sọrọ lori iṣẹlẹ yii, awọn alaga ẹgbẹ CAN nipinlẹ Oyo ati Ondo, Pasitọ Benjamin Akanmu ati Ayo Oladapo woye pe, ijọba fẹ tete sekupa awọn arugbo ni, ti wọn ko ba ni anfaani lati jade sita. Lero ti Akanmu, erokero ati iku ojiji ko jinna si arugbo to ba da nikan wa nile, ti aigbọ ọrọ Ọlọrun ni oore koore ko si le ṣe awọn ọmọde loore. O wa daba pe ki ijọba kesi awọn onimọ ijinlẹ lati tete wa ọna abayọ si arun Coronavirus yii, nitori itọju la nilo, kii ṣe ka gbe ilẹkun ile ijọsin ti pa. ""Ohun to n ba ijọba ipinlẹ Oyo lẹru ni pe awọn eeyan to n lugbadi arun Covid-19 n pọ si dipo ki wọn dinku, eyi lo mu ko tilẹkun ile ijọsin, ẹni to si kan lo mọ, amọ gbogbo ọkan lo n pohungbẹ lati wa sile Ọlọrun, ipa ti adura si n ko, kii ṣe ipa kekere."" Ninu ọrọ tiẹ, alaga ẹgbẹ CAN ni Ondo salaye pe, ijọba kan n fi ẹtẹ silẹ, maa pa lapalapa ni nitori awọn onimọ isegun ti kede saaju pe, awọn arugbo ni ko sa fun Covid-19, kii ṣe ọmọde. Oladapo ni "" Ti awọn obi ba lọ sile ijọsin, nibo ni wọn fẹ fi awọn ọmọ wọn si, ṣe wọn yoo tilẹkun mọ wọn sile ni abi wọn yoo ko wọn da si titi? Ijọba apapọ ko ro ero rẹ daadaa ko to gbe sita."" O fikun pe o dara bi awọn arugbo ba joko sile, amọ wahala ni wọn fẹ da silẹ pẹlu ọmọde ti wọn ni ko jokoo sile, tori awọn ọmọde ko ni pẹ maa sọnu ladugbo. Oladapo, to faramọ awọn ilana tijọba Ondo gbe kalẹ lori ijọsin tun ni, ohun to dara ni bi ijọba ṣe kọkọ tilẹkun ile ijọsin pa nitori igbagbọ ninu Kristi ko ni idiwọ, isẹ Ọlọrun si n tẹ siwaju.",0,yoruba Ṣí àwọn àmì-ìwé inú àkọlé yìí nínú àwọn táàbù tuntun,0,yoruba aláìì a yi fi ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìwà: ti o nuni ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Bàbá lo ni Bẹ́ẹ̀ ni.,0,yoruba Ihahilo Ekiti ti dopin o! Gomina lola @user ni ohun o fa ijogbon mo o. O no owo ife si Gomina @user http://t.co/RFAa5XXz7e,0,yoruba "àwọn alákòó. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Bàbá lo ni ìgbà mi owó àkokò, Ọba ri Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "àsà tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba ó nídìí tí ṣe ní kí a máa,0,yoruba "Bùhárí ní òṣèlú ẹ̀tánú ló wà nì ìpìlẹ̀ wàhálà àgbẹ̀ àti darandaran, Nígbà tó ń gbàlejò Bíṣọ́ọ̀bù àgbà ìjọ Anglican ní Canterbury, Ẹniọ̀wọ̀ Justin Welby ní ìlú London. Buhari ní, ""Torí awuyewuye tó ń jà láàárín àwọn ọmọ Nàìjíríà lórí bóyá màá díje tàbí n kò ní díje ló jẹ́ kí n kéde kí n tó kúrò ní Nàìjíríà."" ""Omi ń bẹ láàmù fún wa lórí ètò àbò, ètò ọ̀gbìn, ọrọ̀ ajé, gbígbógun ti ìwà ìbàjẹ́ àti bẹ́ẹ̀bẹ́ẹ̀ lọ. Kò yẹ kí òṣèlú ó jẹ́ ìdààmú fún wa."" Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ̀tanú ló wà ní ìdí wàhálà darandaran Ààrẹ Mùhámádù Bùhárí tún ṣàlàyé àwọn àṣeyọrí ìjọba rẹ̀ fún ẹni ọ̀wọ̀ Welby. Ó ní lórí wàhálà àgbẹ̀ àti darandaran, òṣèlú ẹ̀tánú ló wà nì ìpìlẹ̀ rẹ̀. Bákannáà ni ààrẹ Mùhámádù Bùhárí ní àwọn ń mójú tó àtipadà wálé e Leah Sharibu, akẹ́kọ̀ Dapchi tó ṣì wà ní àhámọ́ àwọn Boko haram nítórí pé ó kọ̀ láti yípadà sí ẹ̀sìn Islam.",0,yoruba "tó kún jú, àwọn ènìyàn ni ó pa Ọmọ lo aye àìlẹ̀.",0,yoruba "Owó gọbọi wá nídìí oko-owo igbó gbingbin, Ìpínlẹ̀ Ondo kò ní pẹ gba àṣẹ láti gbin - Akeredolu Iroyin lawọn iwe iroyin abẹle n sọ pe lasiko iṣejọba oloogbe Oluṣẹgun Agagu ni wọn ti fi owo naa pamọ si aṣuwọn banki igbalode kan. Ninu atẹjade kan, kọmiṣọna feto iroyin ni ipinlẹ Ondo, Donald Ojogo ni kọmiṣọna feto iṣuna lo ṣawari owo naa nibi to farasin si. O ni ni kete ti kọmiṣọna feto iṣuna kansẹ ba owo naa lo fi to ijọba leti ti wọn si ti ṣe akọsilẹ rẹ. O ni ko si ọrọ sisan owo fun agbaṣẹṣe kankan lori owo naa nitori ko si agbaṣẹṣe ti wọn gba fun eto gbigba owo naa pada. Ondo Coronavirus: Akeredolu ní igbó ìpínlẹ̀ Ondo ló dára jùlọ lágbaye tí kò sì yẹ kó máa ṣòfò Gomina Ìpínlẹ̀ Ondo, Rotimi Akeredolu tí ṣàlàyé nípa opo anfaani tó wa nídìí ọ̀gbìn igbó.Akeredolu, lásìkò to ń kopa lórí eto kan lórí ìkànnì BBC Yoruba taa pé ní 'Sọ tiẹ̀' ni opo owo wa nídìí lílo èròjà igbó fún eto oko-owo.Akeredolu ni ""owó wá nibẹ, èwe ọlá sì lawa ń pè igbó. A fẹ́ wá ibi ti wọn yóò ti máa gbìn igbó, ti àjò to ń gbógun ti oogun oloro yóò sì mọ nípa rẹ, a máa sọ ibẹ tọsan toru, a gba àṣẹ láti ṣe bẹ́ẹ̀, tí yóò si dohùn, torí òpó anfaani lo wá nìdí rẹ."" Nígbà tó ń ṣàlàyé lórí bí ẹ̀ka aladani àti àwọn ileeṣẹ ṣe leè kopa nìdí gbingbin èwe ọlá náà torí owó pupọ tó wá nídìí rẹ, Akeredolu ni àwọn gbọdọ gba àṣẹ na, láti rí dájú pé wọn kò loo nílò kulo. "" Ọ̀pọ̀ biliọnu náírà ni idokowo náà yóò gbà, gbogbo agbaye sì ti ní èwe igbó tí wọn gbìn ni Ìpínlẹ̀ Ondo lo dára julọ lagbaye, kò sì yẹ ká máa sún wọn ni iná."" Nígbà tó ń ṣàlàyé ìdí tó fi ń fi arákùnrin si ìbẹ̀rẹ̀ orúkọ rẹ dípò ọlọ́lá jùlo, Akeredolu ni orúkọ tí bàbá òun ń pè òun láti kékeré ni òun padà sí, òun kò si fẹ́ òye kankan.Akeredolu tún ṣàlàyé pé, òun fẹ́ràn ìpínlẹ̀ òun àti ìlú Ọwọ, tíì ṣe ìlú abinibi oun, ní òun ṣe dù ipò gomina, àwọn ará ìlú Ọwọ sì lo wà bẹ òun n'ilu Ibadan, láti wá dù ipò náà.""Isẹ asofin tí mo ń ṣe tó mi, àmọ́ ìlú ko le è pé mi, kí n má jẹ́, ní mo ṣe dù ipo gómìnà, mo sì gbà pé Ọlọ́run fẹ ki n se ni"".O fikùn pé, ara àwọn àfojúsùn òun gẹ́gẹ́ bíi Gómìnà ni lati mú amugbooro bá eto ọrọ aje nipinlẹ Ondo, èyí tó tọ́ tí fò sókè ga láti mílíọ̀nù lọ́nà eedegberin náírà si biliọnu méjì náírà báyìí.""A ti pese ọpọ àwọn ohun èlò amayedẹrun si ìpínlẹ̀ Ondo, tá si tún ṣe àtúnṣe sì àwọn ilé ẹ̀kọ́ alakọbẹrẹ wá, a ti ṣe ọpọ nkan tó ṣe mú yangàn dáadáa, a sì dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run."" Owó gọbọi wá nídìí oko-owo igbó gbingbin, Ìpínlẹ̀ Ondo kò ní pẹ gba àṣẹ láti gbin - Akeredolu Akeredolu, nígbà tó ń ṣàlàyé ìdí tí Ìpínlẹ̀ Ondo ṣe fà sẹ́yìn nínú èsi idanwo asejade làwọn ilé ẹ̀kọ́ gírámà, ó ṣàlàyé pé, àwọn akẹ́kọ̀ọ́ nipinlẹ náà ń ṣe daada àmọ́ ó ni bí ọmọ ṣe pọ sì láti jókòó ṣe idanwo asejade ilé ẹ̀kọ́ gírámà, ní wọ́n se n tó àṣeyọrí ìpínlẹ̀ kọ̀ọ̀kan sí.Lórí ajakalẹ àrùn Coronavirus, Akeredolu ni àjálù ńlá ni àrùn náà, ìpínlẹ̀ Ondo sì ti dangajia nítorí àwọn tí ni oriri tẹ́lẹ̀ nípa itọju ibà lassa, tó ti kọkọ bá wọn fínra.""A ti pàṣẹ kí àwọn ọmọ má ṣe lọ sí ilé ẹ̀kọ́ nítorí Coronavirus, ó sì ti ṣe ìpalára fún ọrọ aje wá, a sì ti ń fún àwọn èèyàn ní èròjà oúnjẹ, láti mú kí ayé dẹrun fún wọn""O ṣàlàyé pé, àwọn ọlọ́pàá méjì tí wọn wá láti Eko sì Ondo lo mú kí owoja àrùn Covid-19 lè sì ni Ondo, tí àwọn fi ní alárùn mẹ́jọ, tí mẹta sì yí lọ sílè nínú wọn. Owó gọbọi wá nídìí oko-owo igbó gbingbin, Ìpínlẹ̀ Ondo kò ní pẹ gba àṣẹ láti gbin - Akeredolu ""Bí àwọn ènìyàn ṣe ń wọ Ondo kò yẹ wá, a ti bá àwọn ọlọ́pàá ṣe ipade pé àwọn ènìyàn wọn ń gba owó láti jẹ ki awọn eniyan wọlé, tí wọn si ti ṣèlérí láti ja ọrọ náà kunra si, ọ̀rọ̀ tí aarẹ Buhari sì sọ lọ́jọ́ Aje sì ti mú kó nira bayii láti rinrin àjò láti ìlú kan si òmíràn."" Gbógbo ohun tí aarẹ sọ ni àwa ń ṣe. Kódà ó ti di dandan láti lo ibomu, tá si ti ń rán ibomu lọ́wọ́, bẹ́ẹ̀ la tún yàgò fún ara wa pẹ̀lú ṣíṣe isede."" Àmọ́ àwọn èèyàn wa kò gbọ́ràn pé, kí wọ́n mase lọ sí ọjà mọ. Sísun mọ́ra pọ leè ṣe àkóbá, ó sì dáa kí wọ́n máa patẹ síwájú ilé wọn, dípò lílọ sì ọjà.Nígbà tó ṣàlàyé ipò tí irẹsi tí ìjọba àpapọ̀ pín fun ìpínlẹ̀ Ondo wa, gomina ní ọrọ oselu kò sì níbi ọrọ Irẹsi náà rara.""Iresi tá gba, a rí díẹ̀ nínú rẹ tí kò dáa, àmọ́ kò pọ rárá, wọn ní ká dá èyí tó ti bajẹ padà, ki wọn parọ́ rẹ fún wa. Kò si bí a ṣe máa gba tirela Irẹsi mẹta, tí a kò ní rí èyí tó ti bajẹ nibẹ nítorí wọn tí kò àwọn Irẹsi náà kalẹ, ọjọ́ tí pẹ. Kini Yoruba ""international passport""? Lórí ìpèsè ohun ìdẹ̀rùn fún aráàlú lásìkò igbele Coronavirus, Akeredolu ni òun kò ní kí ẹnikẹ́ni mase tá ọjà, àwọn wọn kan ni kí wọ́n má sú pọ ni.Ó ní awon onimoto tí kò leè ṣíṣe nìkan ni ọ̀rọ̀ yìí kan, táwọn sì ń ṣàn owó oṣù fún àwọn òṣìṣẹ́ ọba, bẹ́ẹ̀ ni àwọn tí ń ṣe ìpèsè oúnjẹ fún àwọn tí kò rí oúnjẹ jẹ.Nípa ṣíṣe ayẹwo fáwọn alárùn Coronavirus àti ẹ̀sùn pé àwọn gómìnà ń fi àrùn náà pá owó ni, Akeredolu ni ìjọba àpapọ̀ kò tii fún ẹnikẹ́ni lowo, bẹ́ẹ̀ sì ni banki agbaye lọ fẹ́ yà àwọn lowo, kii sì ṣe ọ̀fẹ́, àwọn yóò san owó náà padà.Gẹ́gẹ́ bí ìpínlẹ̀ to ni epo robi àti eto eto idokowo, gomina ni ipo karùn-ún ni ìpínlẹ̀ Ondo wá, isẹ ribiribi tí àwọn sí ń gbé ṣe lo ń fà àwọn olokoowo wá sí Ondo.Lórí ìpèsè àwọn ohun èlò amayedẹrun si agbegbe Ikalẹ, gomina Akeredolu wa rọ awon ọmọ bibi agbegbe naa pé kí wọn fi ọkàn balẹ, nítorí wọ́n kò ní pẹ máa wa ohun àlùmọ́ọ́nì bítúmẹ́nì tó sodo sì agbegbe Ikalẹ, tí ibùdó ojú omi yóò sì tẹdo sí àgbègbè náà pẹlu.Lórí ọjà tó gbé owó lórí lásìkò Coronavirus yìí, gomina woye pe, ""àwa ara ilu ko feran ara wa, ìdí di nìyí tí wón se n gbe owo lè èròjà gbogbo, ìwọ̀nba sì ni ìjọba leè ṣe lórí rẹ."" Nígbà tó ń sọ̀rọ̀ lórí igbesẹ riro àwọn obìnrin lágbára àti ìwòsàn àrùn jẹjẹrẹ, Akeredolu gbé oriyin fun aya rẹ, Betty, fún isẹ takuntakun tó ń ṣe, pẹ̀lú àfikún pe ó tún ń kọ àwọn ọmọdébìnrin ni onírúurú isẹ ọwọ, kí wọ́n leè dá dúró fúnra wọn.Lórí ṣíṣe ṣáá kejì lórí aleefa, Akeredolu ni laipẹ ni ìpolongo ibo yóò bẹ̀rẹ̀, tí Ọlọ́run bá sì ní òun yóò ṣe ṣáá kejì, kò sì wàhálà, ohun tí Ọlọ́run yóò ṣe, ni òun ń dúró de.O wa pàrọwà sáwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Ondo láti fọkàn balẹ torí ohun rere sí ń bọ̀ nipinlẹ náà, tó sì rọ wọn láti jẹ ki itẹsiwaju wá nínú iṣejọba.",0,yoruba re yóò ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó ṣe pàtàkì.,0,yoruba This is good Ìfẹ́. Kú akitiyan 💪 https://t.co/JdEUov1Oxk,0,yoruba "Rukayat Folawewo ni òun ri iṣẹ́ ìyànu gba lọ́dọ̀ pasitọ Favour David lẹ́yìn ìjàmba ọkọ tó lágbara Wọn fẹ̀sun kan pé wọ́n ń ṣe iṣẹ́ amí ati iṣẹ ìyanu èké ti wọ́n si n purọ gbówó lọ́wọ́ àwọn olùgbé Lekki àti Epe nípínlẹ̀ Eko. Àwọn pásìtọ tí wọ́n fẹ́sùn kan ní Favour David ati Favour Chimobi pẹ̀lú ìfọwọ́sowọ́pọ̀ Rukayat Folawewo àti Bunmi Joshua, láti maa ṣe ìṣẹ́ jìbìtì wọ́n. Agbẹ́nusọ ọlọpàá ní ìpínlẹ̀ Eko Bala Elikana, sọ nínú àtẹjáde kan pe àwọn afurasí náà maa n wá ọmọ ìjọ fún ìjọ Wonders Assembly Ministry to waà ni àdojúkọ Lagos Business School ní márosẹ̀ Lekki/Epe ni Ajah. Elkana ni ""a mú afurasí mẹ́rin ti wọ́n maa n fi iṣẹ́ ìyanu òfége lo gbájuẹ̀ fún àwọn ara ilú ti ko fúra, wọ́n ṣe asọtẹlẹ, awọ́n miran a jẹri èké, èyi ni wọn n lò láti gbowó lọ́wọ wọ́n ti wọ́n a sì tún maa lo àwọn ọna miran láti kó ọrọ̀ jo."" Elkana ni lẹ́yin ti ará ìlú tàwọn lolobó ni àwọn gbé ìgbésẹ̀ ti àwọn si mú àwọn obinrin méji, Rukayat Folawewo àti Bunmi Joshua ti wọ́n n ṣe bi ọmọ ìjọ naa ti wọ́n sì ri iṣẹ́ ìyànú ìwòsàn gbà láti ọwọ pásìtọ lẹ́yìn ìjàmba ọkọ̀. Ondo disability: Kò sí ẹni tí àkàndá kò lè ya ilé rẹ̀- Ayọdele ""Ní ti Bunmi Joshua nítirẹ, oun jẹ́ri èké fún àwọn ọmọ ìjọ naa pé ọmọ oun to ti kò gbọ́ran ti ko si lè sọrọ ri ìwòsàn gbà. O tun ni o sì ti n gbọ́ran àti sọ̀rọ̀ báyìí lábẹ́ iṣẹ́ ìránṣẹ́ pásìtọ Favour Chimobi ti ìjọ Elijah Ministry ní Port Harcourt ti oun ati pasitọ David Favour jọ ń ṣiṣẹ́ pọ̀. Elkana sàlàyé pé ìwádìí fihan pé ìrọ panbele ni gbogbo ẹ̀rí náà, ti wọ́n si mu àwọn afurasi náà lásìkò ìṣọ́ oru.",0,yoruba "Ní nígbà àkerekere, Ọba ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí gbogbo ènìyàn gbọ́dọ̀ kọ̀ láti rí ìdìsẹ̀ àti àlàáfíà.",0,yoruba "Gbàgede Nyerere Square ní Dodoma , olú - ìlú orílẹ̀ - èdè Tanzania , àti ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin , """""""" Bunge . """"""""",0,yoruba Ẹ̀rọ - ayàwòrán amóhùnmáwòrán ká ìṣẹ̀lẹ̀ náà sílẹ̀ .,0,yoruba Ara eni lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ài: ti o lẹ.,0,yoruba "Re Mi ~ ni àmì oríi ọ̀rọ̀ yìí -> wọlé. Kíni àmì oríi ọ̀rọ̀ wọ̀nyìí; baba (father), iba (fever), eja (fish)? #ibeere #Yorùbá",0,yoruba onà.. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "ìwájú. Bàbá lo ni ìgbà mi owó àkokò, Alàji lo ìgbà ọkọ.",0,yoruba "Irúfẹ́ iṣẹ́ tí bọ́tìnì yìí dúró fún. Àwọn fálù tó lè jẹ́ ni""lọ́ọ̀kì"",""parí iṣẹ́"",""rọ́ọ̀nù"",""wádìí""àti ""ìmáwòrán"". Bọ́tìnì yìí kàn wúlòtí bọ́tìnì irúfẹ́_nǹkan bá jẹ́ ""ápúlẹ́ẹ̀tì-iṣẹ́"".",0,yoruba @user Doctor ni doctor ń jẹ́ o🙄,0,yoruba "@user: @user #Omo #Akanbi alaketu nikan ni obinrin"""""""""""""""" Alákẹ́tu àti Olówu :)",0,yoruba "Ọwọ ọlọpaa tẹ Yesiru Salisi, amọ ẹni ti wọn jọ ge awọn ẹya ara naa salọ Iroyin sọ pe wọn ba agbari eeyan mẹrin, ọwọ meji, ati àgbọn mẹta lọwọ ri. Afurasi naa, ni wọn sọ pe ilẹ isinku Kristiẹni kan to wa ni adugbo Oke-Eri, nilu Ijebu-Igbo, lo ti ge awọn ẹya ara naa lọjọ Aje, pẹlu iranlọwọ ẹnikan, Lekan Bakare, to ti salọ bayii. Gẹgẹ bi iwe iroyin abẹle, The Punch, ṣe sọ, ọwọ tẹ Salisu, lẹyin ti awọn araalu fi ẹjọ sun ni agọ ọlọpaa to wa ni Ago-Iwoye. Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ogun, Abimbola Oyeyemi, sọ pe ẹni to lọ fi ẹjọ sun ni oun ri ọkunrin kan to gbe apo dani, ti oun fura si pe ẹru ẹlẹru lo wa ninu rẹ. Ati pe nigba ti wọn beere ọrọ lọwọ rẹ, o ju apo naa silẹ, o si sa wọ inu igbo lọ. Eyi lo mu ki awọn ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ lọ si ibẹ, ti wọn si ba awọn ẹya ara eeyan to ti gbẹ ninu apo naa. ""Lẹyin naa ni wọn yẹ inu igbo ti afurasi naa sa wọ daadaa, nibi ti ọwọ ti tẹ ẹ. ""O si jẹwọ pe ilẹ isinku to wa ni Oke-Eri nilu Ijebu-Igbo, ni oun ati ẹnikan ti ge awọn ẹya ara naa."" Nibayii, iwadii ti n lọ lori ọrọ naa. LASU Ritual: Àwọn akẹẹgbẹ́ akẹ́kọ̀ọ́ LASU tí wọn fi ṣowó sọ̀rọ̀ lórí ìgbé ayé olóògbé",0,yoruba ẹkọ́ ṣẹlẹ ni Ibadan ti gbogbo eniyan sọ o ṣe pataki. (2001),0,yoruba ní wúlò. ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa òkè: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní.,0,yoruba "Ilu Accra tii ṣe olu ilu orilẹede Ghana ni wọn ti n sefilọlẹ ami ẹyẹ tọdun yi Awọn akọroyin jakejado ilẹ Afrika ni wọn npe lati kopa ninu ami ẹyẹ yii, eyi ti afojusun rẹ wa lati sawari ati agbelarugẹ awọn irawọ tuntun latilẹ Afrika. Ẹni to ba yege yoo lo osu mẹta ni olu ileesẹ BBC nilu London, yoo ni ọpọ imọ kikun ati iriri. Deede aago mejila ku isẹju kan loru ọjọ kẹtalelogun osu kẹta ọdun 2018 ni ikọwe beere lati kopa ninu ami ẹyẹ naa yoo wa sopin. Wọn gbe ami ẹyẹ naa kalẹ lati bu ọla fun Komla Dumor, gbajugbaja agbohunsafẹfẹ to dantọ lati orilẹede Ghana, o tun jẹ oniroyin fun ikanni iroyin BBC lagbaye. O sadede dagbere faye lọdun 2014 lẹni ọdun mọkanlelogoji. Ilu Accra tii ṣe olu ilu orilẹede Ghana ni wọn ti n sefilọlẹ ami ẹyẹ tọdun yi. A o pese ami ẹyẹ yii fun ẹda kọọkan to tayọ, ti wọn ngbe, ti wọn si tun nsisẹ nilẹ Afrika, ti wọn ko ọgbọn atinuda fun isẹ akọroyin papọ mọ ẹbun to tayọ lori afẹfẹ ati ẹbun to pegede ninu sisọ awọn itan to jẹmọ tilẹ Afrika pẹlu ilakaka ati aayan lati di irawọ ọjọ ọla. Yatọ si pe ẹni to ba yege lati gba ami ẹyẹ naa yoo lọ lo akoko kan nibujoko ileesẹ BBC nilu London, bakanaa ni onitọun yoo tun se abẹwo wa si Afrika lati wa kọ iroyin-ti wọn yoo si se alabapin iroyin naa jakejado ilẹ Afrika ati lagbaye. Ẹni to gba ami ẹyẹ naa lọdun 2017 Amina Yuguda kọ iroyin nipa awọn isẹlẹ ayika lasiko to wa pẹlu BBC Awọn eeyan to ti gba ami ẹyẹ Komla Dumor tẹlẹ ni Nancy Kacungira lati orilẹede Uganda, Didi Akinyẹlurẹ lati orilẹede Naijiria, ati Amina Yuguda, lati orilẹede Naijiria bakanaa. Fun isẹ akanse rẹ, Amina kọ iroyin lati orilẹede Uganda lori Ewu to n koju adagun odo Victoria, tii se adagun odo to tobi julọ pẹlu omi ọtun nilẹ Afrika, eyi tawọn onimọ ijinlẹ sayẹnsi sekilọ pe o lee maa ku lọ. Amina ni: ""Gẹgẹ bii ẹni to gba ami ẹyẹ Komla Dumor tileesẹ iroyin BBC lagbaye fọdun 2017, o dabi ẹnipe ibẹrẹ isẹ ti mo yan laayo niyi lo se ri lara mi. Lati de ipele isẹ akọroyin lagbaye, ki n jẹ ilu mọọka lagbaye, o dabi ẹnipe mo ti de ibi giga ni. ""Lasiko ti mo fi ngba idanilẹkọ, mo kọ nipa pataki sisọ otitọ, kikọ iroyin lai segbe sibikan ati fifun igun kọọkan ni anfaani ọgbọọgba, ti mo si tun ni iriri lori baa se lee ni oju inu to se iyebiye lati kọ iroyin nipa ilẹ Afrika, lọna ti yoo fi fa oju awujọ agbaye mọra. ""Ori wa wu nipa ọna ti Komla gba soju ilẹ Afrika ni awujọ agbaye, mo si ri ara mi bii ẹni taa bu ọla fun pẹlu sise iranwọ lati mu ki ogun rere yi tẹsiwaju."" BBC ṣe'filọlẹ ami ẹyẹ Komlar Dumor Amina yoo kopa nibi ayẹyẹ ifilọlẹ ami ẹyẹ naa fun tọdun yi, pẹlu Jamie Angus, tii se oludari ileesẹ BBC agbaye. O sọrọ siwaju ayẹyẹ naa: ""Iyi nla ni fun mi lati wa lorilẹede Ghana, nilu abinibi Komla, laarin awọn mọlẹbi ati ọrẹ rẹ, lati se ajọdun ogun rere to fisilẹ, ki n si tun sawari ogo tuntun mii to tun kan ti yoo bẹrẹ si ni tan ninu isẹ iroyin lati ilẹ Afrika. ""Awọn eeyan mẹtẹẹta to ti gba ami ẹyẹ naa siwaju - Nancy, Didi ati Amina - ti safihan pe akọroyin to ni ẹbun gidi ni wọn, ti wọn si nimọ kikun to fidi mulẹ nipa ilẹ Afrika ati oju inu nipa ọna taa fi lee mu agbega ba ibasepọ wa pẹlu awọn ololufẹ wa. ""A tun ti n foju sọna lati wa awọn akọroyin mii to muna doko lati ilẹ Afrika, ka si ki wọn kaabọ gẹgẹ bii ẹni to jawe olubori ninu idije ami ẹyẹ Komla Dumor mii, tileesẹ iroyin BBC lagbaye.""",0,yoruba "Sẹnetọ Adeyẹmi to bu omije soju lasiko to n da ṣi ọrọ wahala eto aabo to mẹhẹ ni Naijiria, eyi ti ile gbe yẹwo ni, irufẹ ipaniyan to n waye bayii ni Naijiria ko fẹẹ ni ẹlẹgbẹ, lati igba ti wọn ti tẹẹ do. Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ, Sẹnetọ Adeyẹmi woye pe laijẹ pe Naijiria n jagun lọwọ, iye ẹmi to n padanu lorilẹede yii kọja eyi ti awọn aṣiwaju gbọdọ mojuto. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Lori itaporogan to waye laarin oun ati akẹgbẹ rẹ, Sẹnetọ Rẹmi Tinubu, lori pe ọrọ rẹ dabi ọrọ alatako, Sẹnetọ Adeyẹmi ni ọrọ to wa nilẹ bayii ti kuro ni ọrọ ẹlẹgbẹjẹgbẹ, ti gbogbo awọn aṣofin si gbọdọ jigiri lori rẹ. O ni oun ko lee sọ san an pe ijọba aarẹ Buhari ti ja araalu kulẹ nitoripe awọn nnkan ti wọn ṣe to dara pẹlu wa. Sugbọn o ni koko agbekalẹ iṣejọba fun araalu, eyi to jẹ aabo ẹmi ati dukia ni ijọba Buhari ti ja kulẹ, ti o si nilo ki o ji giri wa nnkan ṣe si. Sẹnetọ Adeyẹmi to nṣe oju ẹkun idibo apapọ iwọ-oorun Kogi (Kogi West) ni lootọ Buhari lee jẹri sii pe oun wa lara awọn aṣofin to n fi igba gbogbo tii lẹyin. Ogbomoso: Ẹbọ ọkùnrin àti obìnrin tí kò ní ìbálòpọ̀ rí ni wọ́n rú dènà ogun Fulani Amọ o ni sibẹ, nibi ti hilahilo ọrọ aabo de bayii, awọn aṣiwaju ko gbọdọ fi ọrọ naa ṣe egbo ile nitori iye ẹmi to n ṣofo ni Naijiria bayii pakasọ. Remi Tinubu rí ìbínú ọmọ Nàíjíríà lórí bó ṣe tọwọ́ òṣèlú bọ ètò ààbò Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe, orukọ Remi Tinubu lo leke tente lori ayelujara lorilẹede Naijiria ni owurọ Ọjọọru, lẹyin ti fidio kan safihan gbolohun ti Remi Tinubu sọ lori eto aabo to mẹhẹ ni Naijiria. Sẹnetọ to n soju ẹkun idibo Iwọ oorun ipinlẹ Kogi, Smart Adeyemi lo n fi itara sọrọ lori eto aabo to ti dẹnukọlẹ ni Naijiria, o ni ki pe ki aarẹ Buhari o wa nkan ṣe si ni kiakia. Lasiko ti Adeyemi n sọrọ lọwọ ni Remi Tinubu, to n ṣoju ẹkun aarin gbungun ipinlẹ Eko, nile Igbimọ Aṣofin agba ọhun sọ wi pe, lo n bi akẹẹgbẹ rẹ naa pe se o si wa ninu ẹgbẹ oselu PDP ni? Bakan naa ni Remi tun n Adeyemi pe se aguntan to da asọ ikooko bora ni? Ọrọ rẹ yii si lo bi ọpọlọpọ ọmọ Naijiria ninu. Bawo ni ọrọ ṣe ṣẹlẹ ni Ile Aṣofin Agba ni Ọjọ Iṣẹgun? Senato Sani Musa lo ke gbare pẹlu aba to gbe sita pe awọn agbesunmọmi Boko Haram ti gbakoso ijọba ibilẹ mẹta ni ipinlẹ Niger, ti wọn si ti gbe asia wọn soke sibẹ lati jẹ olori le awọn eniyan lori. Lasiko yii ni Sẹnatọ Smart Adeyemi dide, to si fi itara sọrọ wi pe eto aabo lorilẹede Naijiria ti dẹnukọlẹ patapata. Ninu ọrọ rẹ, Adeyemi, ẹni to n fi omije sọrọ ni o ṣeni laanu wi pe, awọn eniyan paapaa ijọba, n fi ọwọ yẹpẹrẹ mu eto aabo to ti dẹnukọlẹ kaakiri nitori ọpọ ọmọ Naijiria ni ẹmi wọn ti sọnu sinu ijamba ikọlu kaakiri. ''Nigba kan ri, mo le tẹ ọkọ leti lati ibi ti mo wa lọ si Maiduguri lai si wahala, amọ ọrọ ko ri bẹẹ mọ, ko si ọkan ẹni to balẹ lati wa ọkọ lati ilu kan si omiran'' ''Aarẹ! Ina njo lori papa lorilẹede Naijiria, asiko si ti to lati sọ ododo ọrọ lai fi ti ọrọ oṣelu bọ ọ, nitori ọpọ ẹ̣mi lo n sọnu kaakiri ẹya ati ẹkun Naijiria'' ''Ẹ kesi awọn orilẹede lagbaye lati wa ran wa lọwọ, ki ẹ fi ti igberaga silẹ, nitori apa ẹnikẹni ni Naijiria ko ka ọrọ to wa nilẹ yii mọ'' Kini Remi Tinubu sọ to bi awọn ọmọ Naijiria ninu? Lasiko ti Sẹnatọ Adeyemi n fi itara sọrọ lọwọ lori eto aabo naa, ti omije si n bọ loju rẹ, ni fidio safihan Remi Tinubu to n sọrọ labẹlẹ. Ninu ọrọ to sọ, Remi Tinubu ni ''Ṣe ọmọ ẹgbẹ oṣelu PDP ni ẹ ni? Abi ikooko to wọ aṣọ aguntan ni iwọ n ṣe ni? Amọ, Smart Adeyemi ko tilẹ fun Remi Tinubu lesi, to si bẹrẹ si sọrọ fitafita pe, asiko ti to lati beere iranwọ ni oke okun lori eto aabo, nitori ẹgbẹlẹgbẹ biliọnu Naira ni ijọba ti na, ti ko si si aṣeyọri kankan. Akomolede ati Aṣa: Kọ́ ẹ̀kọ́ si nípa ààlọ́ nílẹ̀ Yorùbá Awọn ọmọ Naijiria sọ oko ọrọ si Remi Tinubu Loju ọpọ Twitter ni awọn ọmọ Naijiria ti fi ero wọn han si itakurosọ to waye ni Ile Igbimọ Asofin Agba naa ni Ọjọ Iṣẹgun. Ọpọlọpọ awọn to sọrọ ni, ko yẹ ki Remi Tinubu ti ọrọ oṣelu bo ọrọ eto aabo to mẹhẹ kaakiri ẹkun Naijiria, ati wi pe iwa buruku gba a ni arabinrin naa wu. Awọn miran ni Remi Tinubu pẹlu iwa rẹ ko le e jẹ iyawo aarẹ lorilẹede Naijiria, ti ọkọ rẹ ba dije dupo ni ọdun 2023, nitori wọn ko ni dibo fun un. Olugbon of Igbon: ‘Rubber Stamp’ làwọn aṣòfin àpapọ̀, wọn kò ṣojú aráàlú Bakan naa ni awọn miran ni Remi Tinubu gbọdọ bẹbẹ, ko si tọrọ aforiji lọwọ awọn ọmọ Naijiria, nitori ọrọ aibikita to sọ nipa bi ẹ̣mi awọ̣n ọmọ Naijiria ṣe n sọfo lojoojumọ nitori eto aabo ti ko muna doko. Bi o tilẹ jẹ pe ọkan gboogi ninu ẹgbẹ oṣelu APC, Asiwaju Bola Ahmed Tinubu to jẹ ọkọ Remi Tinubu ko tii sọ ni gbangba pe, oun yoo dije dupo aarẹ ni ọdun 2023, ọpọlọpọ eniyan lo n sọ wi pe arakunrin ọhun ti n gbe igbesẹ to jọ bẹẹ.",0,yoruba "Kurukuru oju ọjọ sediwọ pupọ lati sawari ibi tisẹlẹ naa ti sẹlẹ Baalu ileesẹ Aseman, eleyi to n lọ si igboro Yasuj to wa ni guusu iwọ-orun ilẹ naa lati Tehran, jabọ laarin awọn oke Zagros ti wọn wa laarin-gbun-gbun Iran. Ẹgbẹ alaanu Red Crescent ton se iranlọwọ pajawiri ti tari awọn adoola ẹmi lọ sibi ti isẹlẹ naa ti waye lẹba igboro Semirom nipinlẹ Isfahan. Osisẹ kan l'orilẹede naa so wipe, kuru-kuru oju-ọjọ ko jẹ ki wọn le lo ọkọ baalu aba-sibi-o-ri, lati fi s'awari ibi tisẹlẹ naa ti waye. Ọgọta ero, ẹsọ meji, osisẹ baalu meji ati awakọ ofurufu meji lo wa ninu baalu naa Agbẹnusọ kan sọ wipe: ""Wọn ti ta gbogbo awọn osisẹ iranwọ pajawiri ji lati wa ni sẹpẹ."" Wọn ni awọn nigbagbo wipe, baalu naa jẹ irufẹ baalu ATR 72-500 to ti lo to ogun ọdun. Iroyin sọ wipe awọn to wa ninu baalu na jẹ ogota ero, ẹsọ meji, osisẹ baalu meji ati awakọ ofurufu meji.",0,yoruba @user Bẹ́ẹ̀ ni. ó dára púpọ̀ fún kíkọ àwọn èrò ọkàn àti ìrírí ẹni sílẹ̀. Ẹṣé.,0,yoruba Ẹkọ́ ti o wo fun ipilẹ̀ ti o tó lẹ̀ẹ̀kọ́ jẹ́ pataki gan. Gbogbo ẹkọ̀ dé ibi yen.,0,yoruba "RT @user: @user Oba Ogbaba ti gba alail'ara, gbanigbani n'ijo ewu, A wo igba arun ma gb'eje, el'eti gb'aroye eda, Ab'eti ...",0,yoruba kèrègbè tó fọ́ dẹ̀yìn lẹ́yìn odò orí burúkú dẹ̀yìn lẹ́yìn mi òfò àti ọ̀fọ̀ ajogun gbogbo dẹ̀yìn lẹ́yìn mi dẹ̀yìn ojúmọ́ ire o,0,yoruba "Baàlè se. Nitori eyi, ara eni lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn.",0,yoruba "Ile Igbimọ aṣofin kẹjọ Koda, adari ile Sẹnẹtọ Bukọla Saraki naa yoo dagbere fun ile aṣofin lẹyin to fidi rẹmi ninu idibo gbogboogbo to lọ. Ọpọ lo ti tako awọn aṣofin laarin ọdun to kọ ja ti wọn ti n ṣofin ni olu ilu Naijiria, Abuja. Ṣugbọn iwadii fidi rẹ mu lẹ pe ile igbimọ aṣofin agba kẹjọ to n ko gba sile lonii lo ṣaṣeyọri julọ ninu itan eto oṣelu orilẹ-ede Naijiria. Eyi ni diẹ lara awọn aṣeyọri ile igbimọ aṣofin agba kẹjọ l'Abuja. '500 level'' ni mo wà nígbà tí mo di adélé Ọba' Gbigbe eto iṣuna ile sita Lẹyin ọpọ atotonu awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria, ile igbimọ aṣofin fi eto iṣuna ile sita lọdun 2017. Eyi ni igba akọkọ ti iru rẹ yoo ṣẹlẹ lati ọdun 2010 ti adari ile tẹlẹ, David Mark ti n ṣe ọrọ eto iṣuna ile ni oku oru. Ijiroro gbagade lori eto iṣuna ile Ile igbimọ aṣofin agba l'Abuja ṣe ijiroro gbagade ẹlẹẹkẹta iru rẹ lori eto iṣuna ile ninu oṣu kẹta, ọdun 2019. Ile bẹrẹ eto yii labẹ adari Sẹnẹtọ Bukola Saraki lọdun 2016. Eto yii ti fun ọpọ ọmọ Naijiria lanfaani lati beere oniruuru ibeere lori eto iṣuna ile. Ajayi: ṣé ìwọ mọ irúfẹ́ ọmọ tí Yorùbá ń pè bẹ́ẹ̀? Ofin ọdọ o kere lati ṣejọba Ile igbimọ aṣofin gbe abadofin ọdọ o kere lati ṣejọba lọ siwaju Aarẹ Muhammadu Buhari, eleyi ti aarẹ buwọlu lọdun 2018. Ofin naa din ọjọ ori awọn oludije fun ipo aarẹ ku lati ogoji ọdun si ọdun marundinlogoji, ati tawọn gomina ku lati ọdun marundinlogoji si ọgbọn ọdun. Ṣisẹ ofin to pọju lọ Ile igbimọ aṣofin agba kẹjọ ṣiṣẹ lori abadofin to din meje lọọdunrun un(293) lati igba ti wọn ti bẹrẹ di oṣu karun un, ọdun 2019. Meji din ni aadoje(128) ni ile igbimọ aṣofin keje le ṣiṣẹ le lori, nigba ti ile kẹfa ṣiṣẹ ofin mejilelaadọrin (72). Eto aabo Lootọọ, kii ṣe ojuṣe ile aṣofin lati pese eto to mọnyan lori fawọn ara ilu, ṣugbọn ile aṣofin kẹjọ ṣe apero lori eto aabo ninu oṣu keji ọdun 2019. Yatọ si apero yii, ile jiroro lọsọọsẹ lori bi eto aabo yoo ṣe gbopọn si lorilẹedee Naijiria bo tilẹ jẹ pe diẹ ninu aba wọn ni igbimọ alaṣẹ ṣiṣẹ le lori. A kii mọ rin, kori o ma min, eyi ni awọn kudiẹkudiẹ ti ile igbimọ aṣofin agba kẹjọ ni, bi wọn ti kogba sile lonii. Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú",0,yoruba "Winter Olympics ti bere ni south korea Lasiko ti wọn n gbaradi fun idije naa, orilẹede South ati North Korea fọwọsowọpọ fun igba akọkọ, ti wọn si parapọ yan awọn obinrin ti yoo soju wọn fun ere idaraya Hockey, ninu idije naa. Pyeongchang gbalejo lọjọ kẹsan si ọjọ karundinlogbon osu keji Iroyin fi lede wipe gbajugbaja elere idaraya to le ni ẹgbẹrun mẹta ni yoo kopa ninu Winter Olympics fun ayẹyẹ ami irawọ (Medal) to le lọgọrun ninu orisirisi ere idaraya marundinlogun. Fun ẹkunrẹrẹ lẹsẹlẹsẹ lori bi ere idaraya Winter Olympics naa se n lọ, ẹ le kan si ẹka iroyin BBCTV, Redio, gbogbo ẹrọ ayelujara ti BBC ati ti oju opo BBC Sports. Akwasi Frimpong Akwasi Frimpong ni oludasile ajo ere idaraya ere ori yinyin ilẹ Ghana,ti a mo si Bobsled and Skeleton Federation(BSF-Ghana) lodun 2016. Elere ori papa ni Frimpong je tẹlẹ sugbọn ijakule eṣe ibi gigise rẹ mu ki o yan ere idaraya mi laayo. Sabrina Simader Simader, ti awọn molebi rẹ ko lo si Austria nigba ti o wa lọmọdun mẹta ni ẹni akoko ti yoo soju ilẹ Kenya nibi idije Winter Olympics. Ọdun 2013 lo bere si kopa nibi idije oun.Lọdun 2016,o soju orilẹẹde rẹ nibi idije Winter Youth Olympics ni Norway. Mialitiana Clerc Mialitiana Clerc bẹrẹ sini kọ nipa ere ori yinyin nigba ti o jẹ ọmọ ọdun mẹta ni ilẹ France.O di ọmọ ọdun mẹrindinlogun ni osu kọkanla ọdun 2017,eyi to mu ko jẹ ọkan lara awọn oludije ti ọjọ ori rẹ kere julọ nibi idije naa. Samir Azzimani Samir Azzimani kọkọ kopa ninu ẹka ere ori yiyin ‘alpine skiing’ ki o to wa sun kuro lọsi idi ẹka ere miran ti wọn npe ni ‘cross-country skiing. Adam Lamhamedi Adam Lamhamedi ti baba rẹ jẹ ọmọ Morocco ti iya rẹ si jẹ ọmọ Canada se oun manigbagbe nigba ti o di ọmọ ilẹ Afrika akoko to gba ami ẹyẹ goolu nibi idije Winter Youth Olympic Games ni Austria lọdun 2012. Moriam Seun Adigun Seun Adigun loludasilẹ ikọ kẹkẹ ori yiyin ‘Bobsleigh team’ akọkọ fun orilẹẹde Nigeria.Ọun ni awakọ ikọ naa. Saaju ni o je elere ori papa to kopa ninu idije asafogi ‘hurdles’ Summer Olympics lodun 2012 nilu London. Akuoma Omeoga Akuoma ni wọn npe ni “brakewoman” fun ikọ kẹkẹ ori yiyin ‘Bobsleigh’ akọkọ fun orilẹẹde Nigeria. Bakanna lo jẹ osise a wa aye fun ni si ẹka ilera. Ngozi Onwumere Ngozi Onwumere je elere ori papa to ti soju orilẹẹde Nigeria ninu idije ere idaraya ilẹ Afrika lọdun 2015 Simidele Adeagbo Lẹyin isinmi ọdun mẹsan fun ere idaraya,Simidele Adeagbo ni iwuri latari aseyori ikọ kẹkẹ ori yiyin ‘Bobsleigh team’ orilẹẹde Nigeria. Adeagbo ni ọmọ orilẹẹde Nigeria ti yoo kọkọ kopa ninu idije ti wọn pẹ ni ‘’skeleton’ Connor Wilson Connor Wilson kẹko gboye nipa itọju ẹranko ni ile ẹko fasity Vermont ni orilẹẹde Amerika. Mathilde-Amivi Petitjean Mathilde-Amivi Petitjean ti fi saaju jẹ okan lara ọmọ iko ere idaraya ori yiyin fun orilẹẹde France ki o to sun lati soju Togo ilẹ abinibi rẹ. Alessia Afi Dipol Pẹlu bi ko se tan mo ile Togo,Alessia Afi Dipol yan lati soju ilẹ naa. O kọkọ kopa labẹ asia Togo nibi idije Winter Olympics lọdun 2014 ni ilu Sochi. Shannon-Ogbani Abeda Abeda to dagba silẹ Canada gbero lati jẹ agbaboolu afigi gba lori yiyin ‘ice hockey’ sugbọn awọn obi rẹ ni ere yiyo lori yiyin pẹlu opa onirin(skiing) ni yoo je ere idaraya to ye. Oun ni ọmọ Eritrea akoko ti yoo soju orilẹẹde rẹ nibi idije Winter Olympics. Ẹni to ni aworan: Matthias Hangst/Getty Images, Dimitar Dilkoff/AFP/Getty Images, Francois Xavier Marit/AFP/Getty Images, Shaun Botterill/Getty Images, Christophe Pallot/Agence Zoom/Getty Images, Alexander Hassenstein/Getty Images, ALEXANDER KLEIN/AFP/Getty Images, Dean Mouhtaropoulos/Getty Images, Courtney Hoffos",0,yoruba "✅Ọ̀bẹ ń wó ilé araa rẹ̀, ó ní òun ń ba àkọ̀ nínú jẹ́. ✅Àdá l'ẹnu tálákà, igbó la ó fi dá. ✅Bí ọwọ́ ẹni ò bá tẹ èkù idà, kì í béèrè ikú tó pa baba ẹni. ✅Ọkọ́ kì í kọ ju ilẹ̀ lọ. #InYoruba #learnyoruba #Language #Yoruba https://t.co/wGgh6e2v3s",0,yoruba "nípa ìwájú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Ṣébi wọn ni ibi gbogbo là ń dáná alẹ́ nitori naa, Kayefi ti oṣu yii kii ṣe lati tabuku ba ẹnikẹni, ẹgbẹ tabi ijọ kankan. Ṣugbọn ijọ yii ti wọn darukọ rẹ ninu fidio to wa loke wa ni ilu Igboora, wọn si ni Woli kan to n dari wọn. Wolii Aroye Jesu kọ ni oludasilẹ ijọ o ṣugbọn nigba ti oludasil ijọ papoda, wọn lọ ba baba kan niluu. Baba ọhun lo mu ẹni kan ti o pe ni Wolii wa lati maa wa dari wọn ninu ijọ. Ọrọ pọ ninu iwe kọbọ ti ko ni ṣee kọ jade tabi ka tan, lẹnu kan de, ẹ wo fọnran yii lati wo gboogbo alaye bi Bosede Oguntunde lati ilu Ilorin, ẹni ọdun mẹtadinlaadọta koda to ti ni ọmọ-ọmọ ṣe di ẹni ti n pọ owó fún Woli Aroye Jesu ni ilu Igboora. Awọn Iroyin mii ti ẹ le nifẹ sii",0,yoruba "Ọjọ́ Ẹtì ni ilé ẹjọ́ tó ga jùlọ lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà yóò kéde gómìnà tòótọ́ fún ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun Ni oṣu kẹsan an ọdun 2018 lawọn eeyan ipinlẹ Ọṣun dibo lati yan gomina to wu wọn. Lati igba naa wa, awọn meji to lewaju ninu esi ibo ọhun- Gboyega Oyetọla ti ẹgbẹ oṣelu APC pẹlu Ademọla Adeleke ti ẹgbẹ oṣelu PDP-ti n wọle jade nile ẹjọ kaakiri pẹlu ẹsun emi ni mo bori-iwọ kọ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Adeleke bori ni ipele akọkọ ni ile ẹjọ to gbọ awuyewuye idibo l'Ọṣun, Oyetọla lo rẹrin bọ ni ile ẹjọ kotẹmilọrun, ni bayii ọrọ ti wa di ti ile ẹjọ to ga julọ. Widows Day 2019: Mo máa ń sá kiri wá owó ilé ni -Opó Eyi lo mu ki alaga ẹgbẹ oṣelu APC ni ipinlẹ Ọṣun, Gboyega Famodun o ke sawọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu naa lati wọ inu adura lọ bayii ki nnkan lee ṣe ẹnuure bọ fun wọn lati ile ẹjọ naa. Mo máa n forin mi kìlọ̀ ìwà ìbàjẹ́ láwùjọ ni -Hameen Ninu atẹjade kan to fi sita, Ọmọọba Famodun ni 'adura ṣe pataki lati wawọ awọn igbesẹ awọn ẹni ibi lori lori idajọ naa.' International Day Against Drug Abuse and Trafficking: ìdí ti mo fi ń mu oògùn olóró",0,yoruba o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà.,0,yoruba "Awọn alaṣẹ ile ijo naa ṣalaye pe awọn gbe igbesẹ ọhun lati dena itankalẹ arun ọhun ni nitori pe agbo ti ọpọlọpọ eeyan lati origun mẹrẹẹrin agbaye ti n pade ni. Ile ijo naa ni oun yoo tubọ maa bẹju wo bi nnkan ba ṣe n lọ si lori arun naa ki wọn to tun lee sọ igba ti faaji yoo pada bẹrẹ nibẹ. Coronavirus: Ọmọ ìkókó kan wà lára àwọn márùn ún míràn tó ṣẹ̀ṣẹ̀ kó àrùn coronavirus lórílẹ̀èdè Nàìjíríà Minisita feto ilera lorilẹede Naijiria, Dokita Osagie Ehanire ti fi soju gbangba pe ọmọ ikoko kan wa lara awọn eeyan marun un ti wọn ṣẹṣẹ ri wi pe o ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria. Minisita feto ilera ṣalaye pe, mẹrin ninu awọn eeyan marun un naa ni wọn jẹ ọmọ Naijiria ti ọmọ ikoko naa si jẹ ọkan lara wọn. O fi kun un pe ọmọ orilẹede Amẹrika ni eeyan kan to ku ninu wọn ati pe kii ṣe ọkọ ofurufu loun ba wọ orilẹede Naijiria ni tirẹ. O ṣalaye siwaju sii pe gbogbo awọn eeyan to ba ṣẹṣẹ n wọ orilẹede Naijiria lati oke okun gbọdọ fi ara wọn si igbele ọlọjọ mẹrinla, koda bi ohunkohun ko ba ṣe wọn lasiko ti wọn wọ orilẹede Naijiria. Coronavirus: Ìjọba àpapọ̀ kéde èèyàn márùn ún míràn tó ní àrùn Coronavirus lorilẹ̀ede Naijiria Ijọba apapọ ti kede eeyan marun miran pẹlu arun Coronavirus lorilẹede Naijiria. Eleyi ti sọ iye awọn eeyan to ko aarun naa di mẹjọ. Minisita feto ilera to kede eyii. O ni awọn maraarun naa ni wọn ti rinrinajo lọ sorilẹede Amẹrika ati ilẹ Gẹẹsi laipẹ yii. Coronavirus: Nítorí àrùn Coronavirus ìjọba àpapọ̀ ní káwọn arìnrìnàjò láti orílẹ̀èdè Amẹ́ríkà, Gẹ̀ẹ́sì, Faransé àtorilẹ̀èdè mọ́kànlá míràn o gbélé wọn Gẹgẹ bii ara eto lati tete wawọ ọwọja arun Coronavirus wọlẹ, ijọba orilẹede Naijiria ti gbẹsẹle irinajo lati awọn orilẹede Mẹtala kan wọ orilẹede Naijiria. Ohun ti eyi tumọ si ni pe ko si awọn arinrinajo lati awọn orilẹede mẹtala naa to gbọdọ wọ orilẹede Naijiria. Elebuibon: Àwọn àṣà àtọ̀húnrìnwá ló fa títa ẹ̀jẹ̀ nítorí ògùn owo Awọn orilẹede ti ọrọ kan naa ni orilẹede China, Italy, Iran, South Korea, Spain, Japan, Faranse, Germany, Amẹrika, Norway, ilẹ Gẹẹsi, Netherlands ati orilẹede Switzerland. Ijọba apapọ ni awọn gbe igbesẹ yii lori awọn orilẹede to jẹ wi pe iye awọn eeyan to ti fara ko arun Coronavirus ti ju ẹgbẹrun kan lọ. Alaga igbimọ amuṣẹya ti ijọba apapọ gbe kalẹ lori pipalẹmọ arun Coronavirus kuro lorilẹede Naijiria (Presidential Task Force on COVlD-19) ṣalaye fawọn oniroyin ninu Abuja pe ayẹwo to munadoko yoo maa waye fun gbogbo awọn eeyan to ba wọ orilẹede Naijiria lẹyin abẹwo sawọn orilẹede wọnyii; ti wọn yoo si fi wọn sinu ahamọ iyasọtọ ati ayẹwo fun ọjọ mẹrinla. Bakan naa ni ijọba apapọ tun ṣalaye pe aṣẹ yii lo bẹrẹ si ni fi ẹsẹ mulẹ bẹrẹ lati ọjọ Satide, ọjọ kọkanlelogun oṣu kẹta ọdun 2020. Bakan naa ni wọn tun fi idi rẹ mulẹ pe, lasiko ti aṣẹ yii yoo fi fidi mulẹ, ko ni si aye a n fun ẹnikẹni ni iwe aṣẹ iwọlu-gbelu ti a mọ si visa.",0,yoruba @user @user nko ro wipe iyen see se ni ile Naijiri ija eleyameya ati elesinmesin koo ni je ki o see se,0,yoruba Àwọn t'ó ka àtọ́wò ní ààrẹ̀ tẹ́lẹ̀; OBJ kọ ń'nú ìwé pé ààrẹ̀ GEJ ò dángájíá tó. Èmí rò pé ìwé nípa ara ẹni ní #MyWatch? #Nigeria,0,yoruba @user @user @user @user @user @user @user @user @user @user @user Mo ki gbogbo wa... Didun losan o so loni. Ilekun ayo koni ti mowa o. Ojo eti yi o ti lekun oshi ninu aiye wa. Aaji re bi! #TweetInYoruba,0,yoruba "Omotola Taiwo, ti ọpọ eeyan mọ si ""Omohtee"" ti ṣalaye ohun toju rẹ ri lẹyin iṣẹ abẹ to ṣe ni ọdọ Dokita Anu, lọna ati jẹ ibadi rẹ tobi sii. Omohtee tu pẹrẹpẹrẹ ọrọ naa ninu ifọrọwerọ kan pẹlu BBC pe oun kabamọ igbeṣẹ naa, koda, o ni diẹ lo ku ki oun gba ẹmi ara oun. Ẹni ọdun mejidinlọgbọn ọhun to jẹ oniṣowo aṣọ sọ pe, oriṣirṣi eetu lo n jade ni idi oun ati irora ti ko ṣe fẹnusọ lẹyin iṣẹ abẹ naa. Oṣu kinni ọdu 2020 ni Omohtee ṣe iṣẹ abẹ kanti wọn n pe ni 'Liposuction' ti yoo jẹ ki ikun rẹ pẹlẹbẹ, bẹ lo tun fa ọra ikun rẹ, to si jan mọ idi rẹ ki idi ọhun lee tobi si. Omohtee ti fẹsun kan dokita to ṣe iṣẹ abẹ naa, dokia Anu fun iṣẹ ajabanku to ṣe si oun lara. Ṣugbọn dokita Anu ti pee lẹjọ fun ibanilorukọjẹ, to si n bere fun owo itanran miliọnu marundinlọgbọn naira. Nigba to n sọ tẹnu rẹ fun BBC, dokita Anu ni oun kọṣe mọṣẹ, ati pe oun gba iwe ẹri to dantọ. Anu tun sọ pe iṣe Omohtee kọ ni akọja ewe oun, nitori oun ti ṣe awọn iṣe mii to lami laaka to bi ẹgbẹrun kan ṣaaju iṣẹ rẹ. Dokita ọhun pari ọrọ rẹ pe awuyewuye iṣẹ Omohtee ti mu ki oun padanu iye owo to le ni ọgọrun un miliọnu naira, yatọ si pe ijọba ti gbe ile iwosan oun ti. Ijọba Naijiria ti fi ofin gbe dokita kan, Anu Fela (Medcontour), wọn si ti gbe e lọ si ile ẹjọ giga ijọba apapọ ni Ikoyi nilu Eko. Ọjọ Ẹti, ọjọ kẹrin, oṣu Keje, ni ajọ to n daabo bo ẹtọ oníbàràá ni Naijiria, FCCPC, kede pe oun ti mu Anu, to ni ileewosan Medcontour. Iṣẹ abẹ idi ati ọyàn ni Dokita naa ma n ṣe. Awọn onimọ iṣegun maa n pe iru iṣẹ naa ni Cosmetic Surgery. Wọn ni kò fọwọsowọpọ pẹlu wọn lori iwadii ẹsun ti wọn fi kan an pe ọna ti ko tọ ọ lo n gba ṣiṣẹ abẹ. Ọpọlọpọ igba ni awọn eeyan ti pariwo Dokita Anu, ati ileeṣẹ rẹ lori ayelujara lati bi ọdun meji sẹyin. Ẹsun ti wọn fi n kan an ni pe, iṣẹkiṣẹ lo ṣe si ọyàn ati ìdí ti awọn ni ko ba wọn tun ṣe. Wọn ni niṣe ni ìdí tabi ọyàn awọn burẹwa si, tabi ko di ọgbẹ adaajina. Ọkan lara awọn oníbàràá rẹ, lo pariwo sita lori ayelujara l'oṣu Kẹrin pe, iṣẹ abẹ ti Anu ṣe si idi oun ti da aisan si oun lara. Gbogbo igba si ni Dokita Anu ma n sẹ lori awọn ẹsun naa. Lọjọ kẹẹdogun, oṣu Kẹrin, ni awọn alaṣẹ ti ọfiisi Medcontour pa nilu Eko, lori ẹsun pe oun ṣe iṣẹ ti ko ba ofin mu. Ninu iroyin ti ajọ FCCPC fi sita lọjọ Ẹti, wọn ni awọn fi ofin mu Dokita Anu, nitori pe ko tẹle awọn ilana ti ajọ naa la kalẹ fun iwadii ẹsun naa. Ọga ajọ FCCPC, Babatunde Irukera, ti oun fun'ra rẹ jẹ amofin, ni yoo jẹ olori igbimọ ti yoo rojọ tako. Ojoojumọ ni iye eeyan to n ṣe iṣẹ abẹ ọyan ati idi n pọ si ni Naijiria.",0,yoruba "Báyìí ni àwọn tó sá ń'lé ní Damboa àtàwọn ìlú mìí se ń gbé ní ibùdó tí wọ́n sá lọ Ó lé ní ogójì ènìyàn tó farapa nínú ìbúgbàmù náà báyìí èyí tó wáyé lálẹ́ ọjọ́ àbámẹ́ta. Kò tíì sẹ́ni tó fojú hàn gẹ́gẹ́ bí ẹni tó sokùnfà rẹ̀ sùgbọ́n òjú ni kìí se àìmọ̀ f'ólóko pé ikọ̀ Boko Haram máa ń ṣ'ọṣẹ́ ní agbègbè náà. Awọn iroyin miran ti ẹ le nifẹ si: Adó olóró méjì to bu gbamu yìí ti pa eniyan mọkanlelọgbọn ni ìlú Damboa, ìpínlẹ̀ Borno, ní apá ìlà oòrùn àríwá Nàìjíríà. Isẹlẹ náà waye lẹyin wakati diẹ ti Ọ̀gá àwọn ọmọ ogun oríilẹ̀ orílẹ̀èdè Nàìjíríà, Ọ̀gágun Tukur Buratai ní kí àwọn ènìyàn apá ìlà oòrùn àríwá padà sí ilé wọn. Ọ̀gágun Tukur Buratai ní kí àwọn ènìyàn apá ìlà oòrùn àríwá padà sí ilé wọn Burutai rọ àwọn ará ìlú tí ogun lé kúrò nílé láti padà nítorí pé àláfíà ti jọba lagbeegbe naa. Lẹ́yìn ìbúgbàmù ọ̀ún ni iná rọ́kẹ̀tì láti ìlú míì tún tú jáde. ìròyìn ní obìrin ní àwọn agbésùmọ̀mí mẹ́fà tó siṣẹ́ ọ̀hún bótilẹ̀ jẹ́ pe àwọn Boko Haram kò tí jáde wá pe àwọn ní àwọn ṣe ìkọ́lù ọ̀hún. Ènìyan tó lé ní ogojì ló farapa ninu isẹlẹ ibugbamu naa.",0,yoruba Ọlọ́pá YouTube naa ní ègé olóótọ fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tó gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ àti ìbi tí wọn wà.,0,yoruba "O le ni aadọfa akẹkọ Dapchi to tun bọ sọwọ Boko Haram Wakili fi kun pe kawọn ọmọ Naijiria mase mikan rara nipa ipo tawọn ọmọ Dapchi naa wa nitori eera kankan ko rin won pẹlu ọmọ oun ati awọn ọrẹ rẹ. O ni igun kan ninu ikọ Boko Haram, Barnawi ti kan si oun lọjọbọ pe ọdọ awọn lawọn ọmọ Dapchi ti wọn ji gbe wa. Wakil, jẹ ọmọ igbimọ to nrisi eto ifikunlukun ati yiyanju ipenija eto aabo nitunbi nnubi ( Dialogue and peaceful resolution of security challenges committee), ti ijọba Jonathan da silẹ. Ijọba ti da awọn olori ileesẹ́ alaabo atawọn osisẹ wọn sipinlẹ Yobe lati se awari awọn akẹkọ Dapchi Wakil, ẹni to maa nkan si ikọ Boko haram atawọn asaaju rẹ kede pe oun setan lati fi ẹmi ara oun lelẹ lati doola ẹmi awọn ọmọ Dapchi naa. ""Mo bẹ wọn pupọ, ti mo si ni ki wọn mase jẹ ki awọn akẹkọ yi wa pẹlu wọn fun igba pipẹ, fun ẹgbẹrun ọjọ tabi ju bẹẹ lọ bii tawọn akẹẹkọ Chibok, amọ wọn ko sọ ohunkohun."" ""Ọmọ daada ni Habib, ko lee pa wọn lara rara, bẹẹ ni ko ni fi ọwọ kan wọn tabi ko pa wọn"" Wakil fi kun pe oun nrọ awọn ọmọ Naijiria lati se suuru, ki wọn si kun fun adura nitori ohun gbogbo yoo pada yọri si rere.",0,yoruba "àìmọ́. Nitori eyi, ara eni lo ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..",0,yoruba "Nígbà tó kún jú, àwọn ènìyàn ni ó pa Ìyá lo tun se mú.",0,yoruba ṣùgbọ́n èdùmàrè ṣe iṣẹ́ rẹ̀ lọ́nà àrà ojú ti ọ̀tá ẹni èmi ò lè ṣàìdúpẹ́ njẹ́ ẹni tó bá láròjinlẹ̀ yó mọpẹ́ dá,0,yoruba "àìmọ́. Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Nollywood In Court: Baba Ijesa, Baba Suwe, Yetunde Wunmi àtàwọn òṣèré tíátà tó ṣe ẹjọ́",0,yoruba aṣà. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìwà: ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó wáyé..,0,yoruba naa ní ègé olóótọ fún àwọn ìkòkò tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Alàji lo joko.,0,yoruba Akọ̀ròyìn Esdras Ndikumana túwíìtì :,0,yoruba Ṣàfihàn àkóónú ìwòyí ojú-ìwé lọ́wọ́lọ́wọ́,0,yoruba pe lẹ ìkòkò wey ti o pẹ jú nìlọ̀ ni ọ̀nà tí ẹ̀ọ́ kan máa ń gbé ìyẹ̀ alẹ́.,0,yoruba jare. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọba lo lọ.,0,yoruba RT @user: @user amin oo ire á je ti wá,0,yoruba dídì yìí ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba RT @user: Àìkọ́wọ̀ọ́ rìn ní í jẹ ọmọ ejò níyà.,0,yoruba Àwòrán tí a mú láti Ibùdó - ìtàkùn - àgbáyé iṣẹ́ Ìtàn Àwọn Ènìyàn .,0,yoruba "Bẹ́ẹ̀ lójú ti rí ìyá tí ó ta téru nípa lẹ́yìn oṣù kan. Ìgbàgbọ́ àwọn tí ó ṣẹ̀ wá ni wípé ewu ń bẹ l'óko l'Óńgẹ́, l'Óńgẹ́ fún'ra rẹ̀ náà ewu ni kí ogójì ọjọ́ ó tó pé. Ojú ara ìyá ọlọ́mọ á ti jiná, ara yóò ti padà sí ipò, sàárè ikú á ti dí fún t'ọmọtìyá.",0,yoruba "ìwájú. Nitori eyi, ara eni ni nfàn ojú kakaaki.",0,yoruba "COVID - 19 : ìpínlẹ̀ Kano bẹ̀rẹ̀ oúnjẹ pínpín fụ́n àwọn ará ìlú Ìjọba ìpínlẹ̀ Kano yóò bẹ̀rẹ̀ sì ní máa pín oúnjẹ láti fi ṣe ètò ìrànwọ́ fún àwọn ọmọ ìpínlẹ̀ náà , kí ó le dín wàhálà tí wọ́n ń kojú lásìkò ètò kónílé - gbélé kù nípasẹ̀ ààrùn COVID - 19 Olùrànlọ́wọ́ ìjọba ìpínlẹ̀ náà lórí ìròyìn ,",0,yoruba akú oṣù túntún happy new month,0,yoruba "Òmì ni Chelsea ta pẹ̀lú Man U Ọpọ lo ro pe alubami ni Chelsea yoo lu Man U saaju ifẹsẹwọnsẹ ọhun, ṣugbọn awọn agbabọọlu ikọ Man U ya ọgọrọ ololufẹ ere bọọlu lẹnu lẹyin ti wọn ta omi alayo mejimeji pẹlu Chelsea End of Twitter post, 1 Koda diẹ bayii lo ku, wọn o ba na Chelsea mọle ni papa isere Stamford Bridge. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ṣugbọn Ross Barkley ti wọn gbe wọle fun Mateo Kovacic lo gbayo keji wọle fun Chelsea nigbati ifẹsẹwọnsẹ naa. Antonio Rudiger lo kọkọ gbayo sawọn fun Chelsea, sugbọn Anthony Martial sọ ere bọọlu naa di omi alayo kọọkan nigba to dayo naa pada. Anthony Martial gbáyò sáwọ̀n fún Man Uinted Lai besu bẹgba, Martial tun ṣe bẹẹ o tun gbayo ẹlẹẹkeji wọle ṣugbọn omi ni ere bọọlu naa pari si. Jose Mourinho ni wọn n ditẹ mọ oun Nnkan ko fara rọ pẹlu akọnimọọgba ikọ Manchester United Jose Mourinho lẹyin ti ẹgbẹ agbabọọlu naa kuna lati fakọyọ ninu awọn ifẹsẹwọnsẹ kan ti wọn gba laipẹ yii. Koda, Mourinho ni bi awọn oniroyin ere idaraya ti n tako ikọ Man U n sakoba fun awọn agbabọọlu ikọ naa. Ọpọ oniroyin ati awọn agbabọọlu to ti fẹyinti tilẹ sọ pe Mourinho le padanu iṣẹ rẹ ti Manchester United ba fidi rẹmi ninu ifẹsẹwọnsẹ ọjọ Abamẹta. Chelsea àti Manchester United wàákò ní pápá ìṣeré Stamford bridge Ṣugbọn akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea Maurizio Sarri sọ pe ikọ Manchester United lo ni awọn agbabọọlu to pegede julọ saaju ifẹsẹwọnsẹ wọn. Gbẹgẹdẹ yóò gbiná nígbà tí Eden Hazard àti Paul Pogba bá kojú ara wọn Mourinho ti figba kan ri jẹ akọnimọọgba ikọ Chelsea nibi ti o ti gba ife ẹyẹ Premier League lẹẹmẹta pẹlu ikọ naa. Chelsea ló kọ́kọ́ gbáyò wọlé Sugbọn ta ni yoo jawe olubori ninu ifẹsẹwọnsẹ t'ọjọ Abamẹta? Ipade dori papa ni Stamford Bridge nilu London.",0,yoruba "RT @user: """"""""""""""""""""""""""""""""Orile ede America fi enu ete ba isele jamba ti ipinle Plateau http://t.co/hoClzvab44 via @user @user """"""""""""""""""""""""""""""""",0,yoruba A ti ni ìrìn ìròyìn kan mòní nípa àkóbì asin.,0,yoruba "ronú lọ́rọ̀.. Nitori eyi, ara eni lo ni àṣà ìdílé lo je gbogbo ise ibile tèmi.",0,yoruba "Ní ìgbà àtijọ́, inú òkun ni a ti ń kó owó ẹyọ (Ajé) jáde. #OwoEyo #Yoruba",0,yoruba Ṣí Líǹkì nínú Táàbù _Tuntun,0,yoruba ọpọlọ wa ti yòòrò bíi ọsẹ lómi,0,yoruba "Wọ́n ti fi ọkunrin kan si àhámọ́ lori bi wọ́n ṣe gún ènìkàn lọ́bẹ pa lóri afárá London. Wọn darukọ rẹ pe, Usman Khan ni, ati wi pe o ti se ẹwọn ri lori ẹsun to jẹ mọ igbesumọmi ni ọdun 20-12. Awọn ọlọpaa ni ẹni ọdun mejidinlọgbọn naa ni awọn fi silẹ lọdun naa lọhun pẹlu ẹjẹ pe ko ni wuwa buruku lawujọ. Eniyan meji lo padanu ẹmi wọn ninu isẹlẹ naa, ti mẹta si farapa. Ilẹ isẹ ọlọpaa naa fikun pe iwadii n tẹsiwaju lori isẹlẹ naa, a ti wi pe awọn ti n tọpinpin bọya oun nikan lo se igbesunmọmi naa tabi pẹlu iranwọ awọn ẹlomiran. Wàhálà to bẹ́ sílẹ̀ jọ ìgbésùnmọ̀mí, ọlọpàá yìnbọn pa ẹnikan. Iròyìn to ń tẹ̀ wá lọ́wọ́ lórí afárá London ni pé àwọn ọlọpàá ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì ni àwọn ti pa ọkùnrin kan ọ́wọ́ ìgbésùmọ̀mi si ni àwọn fi mú ìṣẹ̀lẹ̀ náà. Ní báyìí wọ́n ti tí orí afára náà pa ti wọ́n si pa ọkùnrin kan to n gún àwọn ènìyàn lẹ́gbẹ̀ẹ́ afárá náà Awọn ọlọpàá MET sàlàyé pé àwọn gba ìpè pé ẹnikan n gú àwọn ènìyàn lágbègbè afárá náà ni ààgo meji ku díẹ̀ lọ́sàn oni Wọ́n fi kun pé àwọn ti mú ọkùnrinkan si ahámọ àwọn nítori pé kìí ṣe ìṣẹ̀lẹ̀ tó kan wáyé lásàn. Ọlọpàá sọ pé ọkùnrin ti wọ́n yìn ni ìbọn náà to si kunibi iṣẹ̀lẹ̀ náà ni àwọn àdó olóro to dì mọ́ra. Fọ́nran kan lori ayélujára sàfihan bi wọ́n ṣe n di okunrin kan mọlẹ lori afára náà, lẹ́yìn náà ni àwọn ọọpàá de ti wọ́n si ni ki àwọn ènìyàn kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀ ti wan si yín ọkùnrin náà nibọ̀n. Akoroyìn BBC John MaManus to wà nibi ìṣẹ̀lẹ̀ náà sàlàyé pé òun ri àwọn agbárijọ ọkunrin kan lori afára náà ti wọ́n n jà. Wòólì Alfred kú lọ́dún 1964, ó tún padà wà sí ìlú Agelu f'ọ́jọ́ mẹ́rìnlá! Lẹ́yin náà ni àwọn ọlọpàá de ti wọ́n sì da ìbọn bolẹ̀ àwọn ọlọpàá to dé ibẹ̀ Awọn ọlọpàá ti gba àwọn ènìyàn ni ìyànjú pé ki maa tẹ̀lé ìlànà ti àwọn ọlọpàá fi lélẹ̀. Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ",0,yoruba Fayose sọrọ lori lẹta Ọbasanjọ si aarẹ Buhari,0,yoruba #TweetinYoruba Oluwa oshe to jen ri ojo eni. Module lowo re. Olorun make she iyanu ninu aye . Like https://t.co/jtE0ZN7bkb,0,yoruba "Ó ní èyí ni láti le máa dóòlà ẹ̀mí àwọn ènìyàn to ni ààrùn kan tàbi òmíràn. Ogunleye sọ èyí nínú ìpàdé orí ayélujára nílùú Eko pé ètò náà wáyá láti pe àkíyèsí àwọn ènìyàn si pàtàkì ìwọ́ ọmọ fún ètò ìwòsàn láwùjọ. Ohun tẹ́ẹ gbúdọ mọ nípa kókó orí ọyàn yín lásìkò fífọ́mọlọ́yàn Adarí ilé iṣẹ́ ètò ìlera náà sàlàyé pé, ìwádìí ti fi hàn pé, ìwọ́ ọmọ mii ó wùlò jùlọ fún ìtọ́jú àwọn ààrùn kan ti o sì lé wúlò fun ìtọ́jú àwọn ààrùn márùndínláàdọ́rún kan. Àwọn ààrùn náà ni ààrùn O fi kun pé, wọ́n ti lòó láti fi ṣe ìtọ́ju ẹni to ni ààrùn fòníkú, fọ̀la dìde. Ogunleye ni kíkó ìwọ́ ọmọ wẹ́wẹ́ pamọ́ jẹ̀ ǹkan tó le wáye ni ẹ̀ẹ̀kan lọ́ja ayé ènìyàn láti rí ìwòsàn fún àwọn ààrùn to lágbára púpọ̀, ó fi kún pé, ibi ti wan ti máa n ri irú èròjà yìí tẹ́ẹ̀ ni inú mùdùnmúdùn inú egungun ènìyàn. Ó ní ìwòsàn àkọ́ka ti wọ́n lo sítẹ́mú sẹẹ̀lì fún wáye ni ọdún 1988 tí ó sì ni àṣeyọri, ó ni ẹni ti wọ́n ṣe fún ni ọmọkunrin kékere kan to ni ààrun ti wọ́n ń pè ni ""Fanconi's Anemia, ó sì niṣe pẹ̀lú ẹ̀jẹ̀ ti ko já geere. Wọ́n gba ìwọ́ àbúrò rẹ ti wọ́n bi wọ́n sì lòó láti fi ṣe ìwòsàn rẹ̀. Bákan náà lo ni ìwádìí ti fi ìdí rẹ̀ múlẹ pé ìwọ́ yìí le dí egungun, ẹran ara, ọkan, àti oníruyuru ẹ̀yà ara.",0,yoruba "àsa. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba RT @user: @user Ọ̀kan ńnú àwọn òkúta ńlá tí wọ́n ń yí oòrùn wa po ni. Ní nkan bí ago méje-àbọ̀ ìrọlẹ́ òní.,0,yoruba @user fi àwòrán ilé yìí tí àwọn màdàrú ti ń ṣe ayédèrú oyin ṣọwọ́ sí @user @user #oyinigan http://t.co/LWi2xVI1Ry,0,yoruba "Agbole baba rẹ ni Ipinlẹ Anambra ni wọn sin si Agbo ile Evidence Igwetu ni wọn sin si. Ẹ o ranti ẹgbọn oloogbe naa, Chinenye ṣe ṣalaye fun BBC pe bii agogo mọkanla alẹ lọjọ naa lọun ni Linda pari iṣẹ ni Outsource Global Company Mabushi to n ba ṣiṣẹ ni ọjọ Iṣẹgun. Lẹyin naa ni oun ati awọn alajọṣiṣẹ rẹ lọ sile igbafẹ kan lati lọ ṣe ajọyọ ipari ìsìnrú'lú eyi ti ayeye rẹ yẹ ko waye loni (Ọjọ́bọ̀) jakejade orilẹede Naijiria. Oju ọna ni ọlọpaa kan ti yinbọn si ọkọ wọn ti o si ṣeku pa Linda.",0,yoruba shi dede ne wapa ẹ̀wẹ̀só o ṣe ẹ wàpá,0,yoruba "kún jú, àwọn ènìyàn ni ó pa Alàji lo ojú odò.",0,yoruba EYES IN YORUBA . Ojú Ojú imú Ojú éti Oju inú Ojú ara Ojú idi Ojú ese And finally Ojú agba #Yoruba @user @user,0,yoruba "àkokò, Ìyá lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa iṣẹ́: ti o ní wúlò.",0,yoruba jẹ́ ìlú tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba ijọba orilẹede naijiria ti sọ wipe awọn ko mo nkankan nipa ibi ti adari ikọ ipob nnamdi kanu farapamọ si lati igba ti ikọ ọmọogun naijiria ti se ikọlu operation python dance lagbegbe ilaoorun gunsu orilẹede naijiria,0,yoruba àbájáde =► result kí ni àbájáde eré bọ́ọ̀lù alẹ́ yìí yóò jẹ́ what will the result of this nights football match be,0,yoruba nípa ìbadandun. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa òkè: ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá.,0,yoruba "Ninu ifọrọwerọ kan pẹlu Emmanuel Mwashumbe ati Shuga Boy, lori redio kan ni Kenya, obinrin ọhun, Cecilia Wambui, ṣalaye ohun to sun un de idi iwa ara meeriri naa. Gẹgẹ bo ṣe sọ, inu iya ati iṣẹ ti wọn bi oun si lo ṣokunfa bi oun ṣe maa n ba oriṣirṣi ọkunrin jade. O ni ""ọmọ ọdun mẹtadinlogun ni mo wa nigba ti mo pade ọrekunrin mi akọkọ, ọkunrin naa wu mi lori nitori o jẹ awakọ, o ni erọ tẹlifiṣọn pẹlu ohun elo idana gaasi."" Ọkọ mi bá àwọn ọmọ wa sọ̀rọ̀ lágo kan kó tó wọ bàálù tó já, àmọ háà! - Ìyàwó Olasunkanmi Olawunmi ""Bo tilẹ jẹ pe aarin oṣu mẹta pere ni a fi ara wa silẹ, o fun mi loyun ṣugbọn mo sẹ oyun naa, mo si tun ṣẹ aimọye oyun lẹyin re."" Cecilia ṣalaye pe laarin igba ti oun wa ni ọmọ ọdun mẹtadinlogun si marundinlọgbọn, oun ṣe igbeyawo pẹlu ọkunrin marun, ti oun si tun ba ọkunrin bii ọgọrun ni ibalopọ. Ṣugbọn nigba to di ọdun 2019 ni Cecilia ri ẹwọn he. O ni lara akitiyan oun lati di ẹni igbala lo mu oun darapọ mọ ayederu ijọ kan, nibi ti oun ti maa n ba awọn ẹmi okunkun ni ibalopọ. Gẹgẹ bii nnkan to sọ, ""mo le dede joko soju kan, ki n dẹ dede ri ara mi ni ile igbokusi ati iboji."" Ẹ̀yin olórin ẹ̀mí tó ń bóra, lo èékáná gígùn, oò yàtọ̀ sí aṣẹ́wó hòtẹ́ẹ̀lì tí wọ́n ń gbé bíi súùtì Pepper Menti - Bola Are Ibalopọ mi pẹlu awọn ẹmi okunkun naa dun mọ mi to bẹẹ ti mi o nifẹsi ati maa ba ọkunrin ni ibalopọ mọ nitori aẉon ẹmi naa maa n tẹ mi lọrun daadaa."" Cecilia sọ siwaju si pe pasitọ ijọ ọhun lo fun oun ni ọkọ lẹyin to sọ pe ọkunrin naa ni ori kọ mọ oun lati ọrun wa. O tẹsiwaju pe gbogbo igba ni oun maa n ri pasitọ naa loju ala, ti yoo sọ fun oun pe ki oun gbe ọwọ le nnkan ọmọkunrin rẹ, lẹyin naa ni ejo dudu kan yoo jade. Leyinorẹyin, o ni oun bẹrẹ si n ṣaisan ṣugbọn pasitọ oun yii ko gba ki oun lọ ile iwosan. Lọwọ yii, Cecilia ti fi ile ijọsin naa silẹ. Bo tilẹ jẹ pe o kọ lati fi orukọ ile ijọsin naa lede, Cecilia ti kọ ọkọ rẹ silẹ, ṣugbọn o ni oun ṣi maa n ri ni ojojumọ ti oun ba ji laarin oru ninu ile oun. Cecilia pari ọrọ rẹ pe oun mọ awọn obinrin marun un miran to jẹ ọmọ ijọ naa, ti wọn si n la irufẹ ohun ti oun la kọja lọwọlọwọ.",0,yoruba "Akọwe ijọba tẹlẹ dero ile ẹjọ Ajọ EFCC gbe Ọgbẹni Lawal ati marun un miran lọ ile ẹjọ lori ẹsun onikoko mẹwaa to da lori nina owo to ju ilaji biliọnu kan naira lati fi pa koriko. Awọn miran ti wọn jọ fẹsun kan ni Hamidu David Lawal, Sulaiman Abubakar, Apeh John Monday, ile iṣẹ Rholavision Engineering Limited ati Josmon Technologies Limited. Ile ẹjọ giga kan ni Abuja ni wọn gbe e lọ ti o si sọ wipe oun ko jẹbi ẹsun ṣiṣe owo ilu ni kumọkumọ. EFCC ni, akọwe agba fun ijọba apapọ tẹlẹ ri naa ni ipin tirẹ ti yoo gba ninu iṣẹ to gbe fun ile isẹ Rholavision Engineering Limited ati Josmon Technologies Limited lati ṣe. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: BBC Nigeria 2019: Lekan Kingkong ní a kò fẹ́ ìtàsílẹ̀ àti ikú ọ̀dọ́ lásìkò ìbò",0,yoruba "Aarẹ Ile Asofin, Bukola Asofin sọwipe kọ jọ oun loju nitori Ọga ọlọpaa naa ti kọ ohun si aarẹ orilẹede Naijiria ri Iroyin sọwipe igbakeji rẹ laarin ọsẹ meji nìyìí ti Idris ti kuna lati jẹ ipe awọn asofin lori fifi panpẹ ọba mu asofin to n soju ẹkun Kogi, Dino Melaye ati isekupani to n waye kaakiri orilẹede Naijiria. Ọga ọlọpaa naa lọse to kọja ran igbakeji rẹ, Joshak Habila lati soju fun un nílé Asofin. Ninu ọrọ rẹ, Aarẹ Ile Asofin, Bukola Asofin sọwipe kọ jọ oun loju nitori Ọga ọlọpaa naa ti kọ ohun si aarẹ orilẹede Naijiria, nigba ti Aarẹ Buhari sọ fun un wipe ko ko ẹru rẹ lọ si Ìpínlẹ̀ Benue lati le bojuto isekupani to n waye lọpọ igba ni agbeegbe naa. Ìgbà kèjì nìyí tí Ílé Ìgbìmọ̀ Asófin Agbà yóò pe Ọ̀gá Ọlọ́pàá láti wá sọ̀rọ̀ lórí ìsekúpani ti Benue Saraki ni Ọga ọlọpaa naa ko se bi Aarẹ se dari rẹ lọpọ igba, o si fikun un wipe awọn o tii ri i ki ọga ọlọpaa kọ lati yọju si awọn asofin lati igba ti ijọba tiwantiwa ti bẹrẹ lorilẹede Naijiria. Awọn asofin naa wa pinu lati ran ikọ lọ si ile isẹ aarẹ lati fi aidunnu wọn han lori iwa ti ọga ọlọpa hu si awọn asofin. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Ọpẹ́lọpẹ́ Ìbàdàn lára Yorùbá'",0,yoruba wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọmọ lo se.,0,yoruba "wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì lẹ̀.",0,yoruba "Amọ o fikun pe ti asẹ naa yoo ba mulẹ, awọn gbedeke kan wa ti oun yoo gbe kalẹ, eyi ti olori ijọ Shiite naa ati iyawo rẹ ti wọn dijọ n jẹjọ lọwọ, gbọdọ tẹle ki ọna to si silẹ fun wọn. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ninu atẹjade kan ti ijọba ipinlẹ Kaduna fisita lati ipasẹ Kọmisana rẹ fun eto iroyin, Samuel Aruwan ni eyi ti jẹyọ pẹlu afikun pe ijọba ipinlẹ Kaduna yoo pe ẹjọ tako asẹ ileeẹjọ naa, eyi to fun El Zakzaky ati iyawo rẹ laaye lati lọ gba itọju loke okun. Ijọba Kaduna ni bi o tilẹ jẹ pe oun maa n bọwọ fun ẹtọ ọmọniyan lati wa itọju fun ara rẹ ni ibikibi lagbaye amọ nibamu pẹlu aṣẹ ileẹjọ naa, awọn igbesẹ kan gbọdọ wa ti olori ẹsin naa gbọdọ tẹle, ki oun to lọ. Ilana ti ijọba Kaduna fi lelẹ ki El-Zakzaky tó lọ gba itọju:",0,yoruba ìròyìn. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba "Nígbà tí Alàji fè fi, Nitori eyi, ara eni lo ni ìwájú.",0,yoruba ó dùn mí pé n ò sí lẹ́gbá fún ọdún tó ńbọ̀ yó ṣojú ẹ̀míi wa láṣẹ ẹlẹ́mí,0,yoruba "Wọn figbe yii ta si ijọba latari bi wọn ṣe ni awọn daran daran n dun mọhuru mọhuru mọ wọn ninu ilu wọn. Awọn agbẹ naa ke gbajare pe pẹlu bi wọn ṣe pa ọkan lara wọn, ti wọn fipa ba awọn ọmọ wẹwẹ wọn lopọ ti wọn si ba oko wọn jẹ, sibẹ sibẹ, awọn daran daran yii ṣi n da ilu awọn laamu eyi to si n gba orun loju wọn. Akọwe ẹgbẹ awọn agbẹ Idera, Oloye Oyekola Joseph jẹ ko di mimọ pe gbogbo ohun to n ṣẹlẹ yii n kọ awọn lominu lati bii ọdun mẹjọ sẹyin to si n ke si ijọba pe ki wọn tete da si ọrọ naa ko to di nkan mii. Rúfin kóo san N1M táa bá ṣí òtẹ́ẹ́lì, ilé sinimá, gbọ̀ngàn ayẹyẹ padà - Ijọba Eko 'Bí a kò bá fẹ́ ìbínú Ọlọ́run, a gbọ́dọ̀ jẹ́ kí Tinubu du ipò ààrẹ̀ lábẹ́ àsìá ẹgbẹ́ APC ní 2023' Àwa la mọ báa ṣe mú Sunday Shodipe táa fà a lé ọlọ́pàá lọ́wọ́ - Ọlọ́dẹ Soludero Gẹgẹ bi iroyin ti a gbọ ṣugbọn ta o lee fi aworan rẹ sinu iroyin yii tori o buru jai, wọn fẹsun kan pe ""awọn daran daran ge ọwọ ọkan lara wọn ti wọn si tun ba oko wa jẹ, agbẹ kan ni wọn ṣa oun ni ada lori, awọn mii fara pa koda wọn fipa ba awọ́n ọmọde wa meji lo pọ"". Awọn agbẹ figbe ta pe wọn ko tii dẹkun kikọlu oko awọn, o ni awọn si ti bẹ wọn tititi ti wọn ko gbọ. Ẹwẹ, nigba ti a kan si ileeṣẹ Ọlọpaa ati Onikoyi ti Ikoyi Ile, Oba Abdul-Yekeen Atilola Oladipupo ko tii f fesi si ọrọ yii to si sọ fun akọroyin BBC pe oun yoo kan si wọn bo ba ya. Ilu Ikoyi-Ile jẹ ilu iṣẹmbaye kan ni ijọba ibilẹ Orire ni ipinlẹ Oyo eyi ti ilu to fẹẹ to ẹẹdẹgbẹrin yii ka bii ilu Olode-Elelu, Animashaun, Obamo, Igboayin, Laomi. ati bẹẹ lọ. Kọmísọ́nà ètò ìlera ìpińlẹ̀ Eko ọjọ̀gbọ́n Akin Abayomi ti lùgbàdì ààrùn Covid-19 'Ìgbà tí mo máa fi lajú sáyé padà, ọ̀fọ̀ ikú mi ní wọ́n ń kígbe'",0,yoruba "Eyi jẹyọ ninu atẹjade ti adari eto awujọ ile ișẹ NCC Ikechukwu Adeinde ati olori ibanisọrọ nile isẹ NIMC Kayode Adegoke jọ fi ọwọ si. Pantami ti ọpọ ọmọ Naijiria ti n bu ẹnu atẹ lu lati ọjọ diẹ sẹyin nitori pe o n gbe ti awọn alakatakiti Taliban ati gbogbo awọn ọrọ to ti sọ, salaye o le ni eniyan mẹrinlelaadọta lo ti gba nọmba idanimọ NIN ni Naijiria. Akọle atẹjade naa ""ni iforukọsikẹ NIN eniyan milionu 54 lo tiforukọsilẹbi ìjọba apapọ se buwọlu ogbọn ojọ osu kẹfa ọdun 2021 gẹgẹ bi gbendeke fun iforukọsilẹ."" O ni awọn gbe igbesẹ naa nibi ipade ori ayelujara ri awọn se ti minista naa si Peju bakan naa ni alaga ajọ NIMC AdeoluAkande wa nikalẹ to fi mọ awọn eekan ajọ to ku. ""Isunsiwaju yii ko ṣẹyin bi awọn ti ọrọkan ṣe n bẹbẹ fun titi di ọgbọn ọjọ, ati lati mu nkan rọrun fun awọn ara ilu ati awọn alejo Ọjọ karundinlogun oṣù Kejila ọdun 2020 ni ijọba pe lẹyin ogbọn ọjọ oṣù kejila ọhun gbogbo eni ti ko ba so nọmba ipe rẹ mọ ti NIN ko ni ṣiṣẹ mọ ati pe awọn ile ișẹ to n ri si ipe yoo ti pa loju opo wọn Nigba ti o se wọn tun sun ogbọn ojoosu kejila yii siwaju nigba ti gbkgbo awọn eniyan n naka alebu si, eyi lo mu ki wọn fi ọsẹ mẹta sun siwaju ti o si di ọjọ kọkandinlogun osu kini osun 2021. Fun awọn ti ko ni NIN rara ofun wọn di ọjọ keji osu keji ọdun 2021 lati lọ gba NIN ki wọn si so mọ nomba ipe wọn. Ọpọ ile isẹ lo ti pe fun ki wọn sun ọrọ NIN siwaju ki awọn òṣìṣẹ́ won le se nkan to yẹ kí wọ́n ṣe. Tóò bá fẹ́ràn àti máa pọ́n ọ̀rọ̀ tàbí èèyàn lé, ẹ̀kọ́ ráńpẹ́ yìí yóò wúlò fún ọ",0,yoruba @user @user @user @user @user @user @user @user @user Ògbóǹtarìgì oníṣòwò ẹrú nù un. Obìrin ogun.,0,yoruba iṣẹ́ ṣẹlẹ ni Ibadan ti gbogbo eniyan sọ o dara. (2003),0,yoruba "Ẹ kú ìrọ̀lẹ́ o, ẹ̀yin ọmọ Yoòbá àtàtà, ó tó ọjọ́ mẹ́ta tí a ṣe ìdánwò oníbèérè. Ní báyìí, ìbéèrè yá, ta l'ó tó gbangba sùn lọ́yẹ? #Ibeere",0,yoruba "Cameroon wa ìyà mu bíi gaàrí lọ́wọ́ England, 3-0 ló bá dé",0,yoruba ṣe àwọn iṣẹ́ tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó jẹ́ dára jù...,0,yoruba "Ọrọ yii dabi ẹni pe ko ni tan nilẹ bọrọ. Ọpọ lo ti n sọ pe aramọnda agbabọọlu Barcelona ati Argentina, Lionel Messi ni agbabọọlu to dara julọ ninu itan. Bakan naa, ọpọ ni wọn ko gba pe Messi ni agbabọọlu to dantọ julọ lagbaaye. Agbabọọlu Brazil tẹlẹ ri orilẹede Brazil to jẹ akẹgbẹ Messi ni ikọ Barcelona, Ronaldinho wa lara awọn to gbagbọ pe Messi kọ ni agbabọọlu to dantọ julọ ninu ere bọọlu. Laipẹ yii ni Messi gbami ẹyẹ Ballon D'or nilẹ Faranse fun igba kẹfa, amọ Ronaldinho t'oun naa gbami ẹyẹ Ballon d'or lọdun 2005 sọ pe oun ko le pe Messi ni agbabọọlu to dara julọ lagbaaye ninu itan. Ronaldinho ni idunnu lo jẹ fun oun pe Messi gbami ẹyẹ Ballon fun igba kẹfa loṣu yii amọ agbabọọlu bi Pele, Maradona, ati Ronaldo ko le jẹ ki sọ wi pe Messi lo dara julọ ninu itan. ""Ohun ti mo le sọ ni pe Messi lo dantọ julọ laarin gbogbo awọn agbabọọlu to wa lasiki tirẹ,'' Ronaldinho lo woye bayii. Cristiano Ronaldo lo ṣi keji lẹyin ti oun naa ti gba ami ẹyẹ Ballon d'or fun igba marun un.",0,yoruba "jẹ́ ìlú tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "Ọkan tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.. Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba o nuni ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó wáyé..,0,yoruba "Agba olorin takasufe, 2Baba lo gba ami ẹyẹ orin takasufe to gbayi julọ ni ilẹ Afirika Davido ni wọn fun ni ami ẹyẹ akọrin to gbayi julẹ pẹlu awo orin rẹ FIA. Bakan naa lo tun gba ami ẹyẹ akọrin ti ko lẹlẹgbẹ lẹkun iwọ oorun Afirika. Tiwa Savage gba akọrin obirin ti ko lẹlẹgbẹ lẹkun iwọ oorun Afirika pẹlu. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ilumọọka asọrọdorin, Rapper Falz ni wọn fun ni ami ẹyẹ olorin Rap ti o pegede julọ ni Afirika. Orilẹ̀èdè Ghana ni àmì ẹ̀yẹ náà ti wáyé Ko tan sori awọn olorin nikan, gomina ipinlẹ Eko, Akinwunmi Ambode pẹlugba ami ẹyẹ fun ipa ti o n ko lori idagbasoke aṣa ati irinajo afẹ, paapaa julọ gẹgẹ bii olugbalejo eto ami ẹyẹ ọhun laarin ọdun 2014 si 2017. Agba olorin takasufe, Innocent Idibia ti gbogbo eniyan mọ sí 2Baba lo gba ami ẹyẹ orin takasufe to gbayi julọ ni ilẹ Afirika. Ọ̀pọ̀ àmì ẹ̀yẹ ni 2Baba ti gbà Amọsa, gbogbo awọn olorin Naijiria to gba ami ẹyẹ yii ni ko sí nibi ti eto naa ti waye lorilẹede Ghana, to jẹ ẹlẹkaarun iru rẹ.",0,yoruba "Kẹtẹkẹtẹ jẹ ọkan lara àwọn nkan irinna to wọpọ ni Daura Bakan naa lo pa ààlà pẹlu ipinlẹ Jigawa ni ilu Kazaure. Daura ni ilu to ti pẹ ju ninu itan ẹya Hausa, koda, awọn oluwadii kan tilẹ gbagbọ pe Daura ni orisun ede Hausa. Daura jẹ ilu abinibi Aarẹ Muhammadu Buhari, ibẹ lo si ti lo eyi to pọju ninu ọjọ aye rẹ. BBC ṣe akọsilẹ awọn nkan marun un to ṣe koko, to si sọ ilu Daura di gbaju-gbaja kaakiri agbaye. Ibrahim Issa to n figbadun ṣayọ 1. Ìtàn ilu naa Nkan akọkọ ti Daura gbajumọ fun ni ìtàn iṣẹdalẹ ilu naa. Akọsilẹ ìtan tilẹ sọ pe Daura ni orisun ede Hausa ati awọn ẹya Hausa. Botilẹ jẹ wi pe awọn onimọ kan ko faramọ eyi. Ṣugbọn ohun to daju ni pe, Daura jẹ ọkan lara awọn ilu meje to jẹ orisun ẹya Hausa. Oriṣiriṣi ọba ati iṣakoso to ti ara Ayaba Daurama jade lo ti jẹ ni Daura titi di oni. Bakan naa ni ilu naa ni awọn ilẹkun abalaye ati ilu olodi, to wọpọ ni ọpọlọpọ ilu to wa ni ilẹ Hausa. 'A máa ń bẹ́ orí ẹni tó bá gbé imọlẹ̀ ọdún ìjẹṣu tó bá ṣubú ni' 2. Daurama A ko le sọrọ nipa ilu Daura, lai mẹnuba Ayaba Daurama - oun ni Ọbabinrin to jẹ kẹyin ni Daura. Ìtan fihan pe Daurama ni Ọbabinrin to wa lori itẹ lasiko ti akọni igbanni, Bayajidda lọ si Daura, to si pa ejo nla to n ba awọn araalu l'ẹru. Daurama fẹ ẹ fun iwa akikanju rẹ. Daurama lo bi awọn ọmọkunrin meje to pilẹ awọn ipinlẹ ẹya Hausa mejeeje - Bawo, Biram, Kano, Katsina, Zazzau, Gobir and Rano. Ìtan ẹya Hausa kò pe, lai si ọrọ Ọbabinrin Daurama ninu rẹ. 3. Bayajidda Ọpọlọpọ eniyan gbagbọ pe orilẹ-ede Baghdad ni orisun Bayajidda, ko to o di pe o wa si Borno nibi to gbe fun igba diẹ. Lẹyin naa lo lọ si Daura. Asiko naa lo ṣawari ìdà to fi pa ejo nla ti ko jẹ ki awọn araalu Daura o raaye pọn omi ninu kanga Kusugu. Lẹyin naa, Ọbabinrin Daurama fẹ Bayajidda l'ọkọ. ""Daurama si di iya nla ẹya Hausa ati awọn eniyan rẹ."" Ṣugbọn, awọn onimọ kan bi i Muhammad Tahar Adama (Baba Impossible) ati Ọjọgbọn Uba Adamu sọ pe ìtàn naa kii ṣe otitọ. Obasanjo: Atiku kìí se Áńgẹ́lì, àmọ́ yóò se dáadáa ní ìlọ́po méjì ju Buhari lọ 4. Kusugu Nigba ti Bayajidda de si ilu Daura, o de si ile obirin arugbo kan, Ayyana. O si beere fun omi, ṣugbọn o sọ fun un pe oun ko ni, nitori pe ejo kan fi inu kanga ti awọn n pọn ṣe ibugbe. Ọjọ Ẹti nikan ni ejo naa maa n fi aaye gba omi pipọn. Ni Bayajidda ba gba gooro ipọnmi kan lọwọ rẹ, o si lọ si ibi ti kanga naa wa. O pa ejo yii, o bẹ ẹ lori, o si pọn omi jade ninu kanga. 'Ó ṣojú mi kòró, ẹ wọ bí ìgbà ayé Bàbá Fagunwa ṣe rí' Nitori naa ni Ọbabinrin Daurama ṣe fẹ ẹ. Kanga naa ṣi wa nilu Daura titi di oni, wọn si n pọn omi ninu rẹ. Ṣugbọn, o ti di nkan ti awọn eniyan n rin irinajo igbafẹ lati wo. Ìtan ilu Daura ko pe rara lai sọ nipa kanga Kusugu. Bimpe: Èèyàn bíi tiyín ni àfín, ẹ dẹ́kun dídẹ́yẹsí àfín 5. Awọn olokiki eniyan Yatọ si wi pe ìtàn fi Daura si ipo pataki ni ilẹ Hausa ati Naijiria, Daura tun ni ọpọlọpọ awọn olokiki eniyan. Ọgagun Muhammadu Buhari: Olori ijọba ologun nigba kan ni Naijiria, to si tun jẹ aarẹ lọwọlọwọ. Ọmọ ilu Daura ni, ibẹ lo si ti lo pupọ ninu igbesi aye rẹ. O ṣoro fun ẹnikẹni to mọ Buhari lati ma mọ pe ọmọ bibi ilu Daura ni, nitori pe ibẹ lo ti maa n ṣe ọpọ ayẹyẹ rẹ. O ni ile, oko, ẹbi ati ọrẹ nibẹ. Ogundiya: Àṣìṣe Dókítà ló sọ mi di aláàbọ̀ ara lórí kẹ̀kẹ́ 2019 Elections: Èrò àwọn ọmọ Nàíjíríà se ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lóri ètó àlùfáà tàbí ìmámù lásìkò ìbò Ọba Umar Faruk Umar: Lọwọlọwọ, oun ni Emir ilu Daura. Oun si ni Emir ọgọta to jẹ ni Daura. Gbaju-gbaja ni kaakiri apa Ariwa Naijiria. Alhaji Usman Daura: Oun ni olori ẹṣọ alaabo fun Aarẹ Shehu Shagari, Ọgagun Muhammadu Buhari ati Ọgagun Ibrahim Babangida laarin ọdun 1981 si 1989. Sani Ahmed Daura: Gomina akọkọ to jẹ ni ipinlẹ Yobe lọdun 1991 si 1998. Sani Zangon Daura: Minisita fun iṣẹ agbẹ ati idagbasoke igberiko laarin ọdun 1999 si 2000, ati Minisita fun ayika lọdun 2000 si 2001. Ja'afar Mahmud Adam: Gbaju-gbaja onimọ ẹsin Islam ni, o si lo pupọ ninu igbesi aye rẹ ni ilu Kano. Ṣugbọn ọpọ mọ pe ilu Daura lo ti wa. Lawal Musa Daura: Ọga agba nigba kan fun ajọ alaabo DSS. Ambassador Mamman Daura: O ti ṣe aṣoju orilẹede Naijiria si Uganda, Saudi Arabia, South Korea, Belgium ati Cameroon. Awọn eekan lo ti jade lati ilu Daura sẹyin Akanṣe Ayẹyẹ Ilu Daura ti di orukọ ilumọọka kaakiri lẹyin ti Buhari di aarẹ lẹẹkeji Ayẹyẹ pataki nilẹ Hausa, Durbar, maa n waye lasiko ọdun ileya. O si maa n larinrin. Igbagbọ wa pe ilu Daura lo ti bẹrẹ. Awọn olukopa nibi ayẹyẹ naa sọ pe asiko Bayajjida lo bẹrẹ lati le mu ki iṣọkan wa laarin awọn Ọba ilẹ Hausa, ṣugbọn atunṣe ba a lẹyin ti ẹsin Islam de. Ọ̀tọ̀ ni nkan tí wọ́n sọ fún ẹbí rẹ̀, iṣẹ́ aṣẹ́wó ni wọ́n fi n ṣe",0,yoruba "Àbẹ́òkúta. Nitori eyi, ara eni lo ni ìgbà mi owó àkokò, Ìyá lo tun se mú.",0,yoruba Àjọ̀dún Òyìnbó ń bọ̀ lọ́nà dẹ̀dẹ̀ .,0,yoruba "Lati igba ti iroyin bi DJ Switch se ja pa naa gbalẹ́ kan, ni ọpọ awọn ọdọ miran naa ti n ya lọ si ileesẹ asoju ijọba orilede Canada ni Naijiria to wa nilu Eko. Koko ohun ti wọn si n beeere ni pe ki ijọba ilẹ Canada naa fi aaye gba awọn plu lati wa se atipo lọdọ rẹ, gẹg bo ti se fun obinrin naa. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Oniruuru awijare lawọn ọdọ naa mẹnuba pe o mu kawọn beere fun atipo naa, eyi ti wọn lo nii nnkan se pẹlu idunkooko mọ ẹmi awọn. Sugbọ̀n nibayii, olu ileeṣẹ asoju ijọba orilẹ-ede Canada ti sọ pe, ilẹ naa kii ṣadeedee gbawọn aṣatipo si orilẹ-ede naa. Ileeṣẹ asoju naa sọrọ yii nitori awon ọmọ Naijiria to fẹ ja pa bii ọkan lara awọn oluwọde EndSARS, DJ Switch to ti fi ilu silẹ bayii. Ohun to yẹ ki o mọ nipa ṣiṣe atipo tabi ṣiṣe abẹwo si orilẹ-ede naa ree: Canada Ileeṣẹ ọhun ṣalaye pe orilẹ-ede Canada n ṣiṣẹ pọ pẹlu igbimọ to n ri si ọrọ awọn aṣatipo ni ajọ iṣọkan agbaye, UNHCR at'awọn ẹgbẹ mii lati ṣe idanimọ awọn to nilo atipo gan an. Ba wo ni eto atipo ṣiṣe ṣe n ṣiṣẹ lawọn orilẹ-ede agbaye? Mo ti fẹsẹ̀ rìn kúrò ní Nàíjíríà àmọ́ ń kò tíì dé ibi tí mò ń lọ - DJ Switch Nibo ni DJ Switch wa? Se o ti sa kuro ni Naijiria ni? Orilẹede wo lo wa gan, ati pe, ta lo n dunkooko mọ ẹmi rẹ? Eyi ni ibeere to gba ẹnu awọn ọmọ Naijiria kan nipa obinrin yii, DJ Switch, ẹni to tu asiri fun araye nipa ikọlu ologun sawọn oluwọde EndSARS ni Lekki ni ogunjọ osu Kẹwa ọdun 2020. Bi wọn ba sọ fun awọn eeyan pe wọn wa ibi ti Obianuju Catherine Udeh wa, o ṣeese ki ọpọ maa beere pe ta lo n jẹ bẹẹ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ṣugbọn bi a ba ti fi inagijẹ DJ Switch kun ibeere yii, ko ni jẹ ohun iyalẹnu nitori ọpọ lo gba ori ayelujara ni Naijiria lọ ti wadii nipa akọni obinrin naa. Eyi ko si ṣẹyin bi iroyin ti ṣe gbode pe, gbajugbaja gbajumọ ori ayelujara ati DJ yii ti sa kuro ni Naijiria lọ si orilẹede Canada. Bawo lo ṣe de kuro ni Naijiria ati pe nigba wo lo lọ? Ninu iroyin to tẹ wa lọwọ eyi ti ileeṣẹ Iroyin Naijiria Punch gbe jade, amugbalẹgbẹ akọrin takasufe Peter Okoye ta mọ si Mr P fidi ọrọ mulẹ fun ileeṣẹ iroyin naa pe, DJ Switch ti kuro ni Naijiria Ninu ifọrọwerọ naa pẹlu Charles Abi, o ni lootọ ni pe alaafia ni DJ Switch wa ati pe o ti rinrinajo kuro ni Naijiria. Amọ ṣa, arakunrin Abi ko sọ ibi ti DJ Switch ka nlẹ lọ. Abi ni nitori idunkoko mọ ẹmi ti DJ Switch ni Naijiria ati aabo ti ko si fun ẹmi rẹ, lo mu ko tete sa asala fun ẹmi rẹ. ''A ko fẹ sọ nnkankan lasiko yii, ootọ ọrọ ibẹ si ni yẹn. Ọrọ idunkoko lọrọ taa n wo yii nitori wọn ti n dun koko mọ pupọ. Ootọ ibẹ ni pe, DJ Switch ko si ni Naijiria lọwọ yii. A o ni sọ boya Canada lo wa ṣugbọn ko si ni Naijiria bayi ati pe alaafia lo wa.'' Nipa iroyin to gbode pe DJ Switch ba awọn aṣofin ilẹ Canada sọrọ, Abi ni oun ko le sọ boya bẹẹ lo ri. ''Mi o le sọ fun yin pe o sọrọ niwaju ile aṣofin ilẹ Canada amọ bi ẹ ba ri ti ile aṣofin Canada fi ọrọ to jọ mọ bẹẹ sita, a jẹ pe o ri bẹẹ ni yẹn. Ọga mi ti kilọ fun mi pe, ki n ma kọ nkankan si oju opo rẹ, bi asiko ba to, yoo sọrọ'' Ohun ti BBC ṣe iwadii ree: Iwadii BBC ṣafihan pe DJ Switch ko kọ nkankan si oju opo rẹ lati le tọka ibi to wa. Ṣugbọn a ri fọnran fidio ipade igbimọ ile asofin Canada kan to n gbẹjọ nipa ẹtọ ọmọniyan nilẹ okeere eyi to waye lọjọ Kẹfa oṣu Kọkanla ọdun yii. Ninu fidio naa ti wọn gbe soju ayelujara, ni DJ Switch ati awọn ẹlẹri mii bi Osai Ojigho ti Amnesty International ti sọrọ. Tim Okafor ati Stella Nkemdimrim to ṣoju awọn ọmọ ẹgbẹ Biafra to wa ni Canada ati Abdulrazaq Namdas ṣalaye fun alaga igbimọ naa, Peter Fonseca, nipa ohun to ṣẹlẹ ni Naijiria sawọn oluwọde ENDSARS. Ko si ohun to tọka si pe Canada ni DJ Switch wa nigba to kopa ninu ipade yii ṣugbọn o sọ ninu fidio naa pọnbele pe, oun ti kuro ni Naijiria. Bakan naa akọrin takasufe P Square to jẹ ọga Charles Abi, naa ṣẹnu pẹmu, ti ko si sọ nkankan to jọ mọ ọrọ DJ Switch loju opo rẹ. Yatọ si awọn arigbamu yii, ijọba Naijiria naa ko ti sọ boya bi Switch ti sa kuro nilu de eti igbọ wọn ati iru igbeṣẹ ti wọn fẹ gbe nipa rẹ. Bi a ko ba gbagbe DJ Switch wa lara awọn to lewaju iwọde ENDSARS, ti o si ṣalabapin fọnran fidio to ṣafihan bi awọn eeyan ṣe n rọ yika oluwọde kan ti wọn yinbọn lu ni Lekki. Bo tilẹ jẹ pe ijọba ti jade lati sọ pe awọn ko dena mọ oluwọde kankan lati maṣe rinrinajo kuro nilẹ Naijiria, amọ ijọba gbe igbesẹ kan laipẹ yii to fi han pe, o ṣeeṣe ki wọn maa dunkoko mọ awọn to ni nnkan ṣe pẹlu iwọde naa. Bi a ko ba gbagbe, Modupe Odele agbẹjọro awọn oluwọde naa ṣalaye pe, awọn oṣiṣẹ ajọ to n risi iwọle-wọde da oun pada ni papakọ ofurufu Murtala Mohammed ni Eko lasiko to fẹ rinrinajo kuro ni Naijiria. O ni wọn pada da iwe irinna oun pada ṣugbọn oun ko ribi ba baalu to yẹ fun irinajo naa lọ. Bẹẹ naa tun ni ile ifowopamọ agba Naijiria CBN, gbegi le asunwọn owo awọn oluwọde kan to fi mọ Rinu Oduala ati Majekodunmi Temitope, ti wọn n ṣoju ọdọ nibi ijoko igbimọ iwadii ti ijọba Eko gbe kalẹnipa iwa ọlọpaa EndSARS. Awọn mejeeji ti tori igbesẹ naa binu kuro ninu igbimọ ọhun.",0,yoruba "orísìrísì ọ̀nà , bàbá dúró gẹ́gẹ́ bí òpómúléró nínú òsèlú àti ọ̀rọ̀ òfin .",0,yoruba "Ariwo ẹ̀rọ amúnáwá àwọn ará ibí ó jẹ́ kí èèyàn gbádùn, mọ́ jú kẹlẹlẹ ni. Nínú ariwo t'òun èéfí ni à ń sùn. Ó ga o! #IjebuLahun",0,yoruba "Gẹgẹ bi awọn ti ọrọ naa ṣoju wọn ṣe sọ pe obinrin ọhun ni oun yoo pa awọn ọmọ naa ti ẹnikẹni ba mu oun ni tulasi lati ṣi ilẹkun. Wọn ni obinrin naa ni oun n fi ẹhonu han lori bi baba awọn ọmọ naa ṣe pa oun ati awọn ọmọ naa ti lati igba ti oun ti wa ninu oyun ti oun si koju inira gidi. Àwọn òbìnrin tó ń ya fọ́tò ìhòhò ara wọn níwájú ilé kó sí gbaga ọlọ́pàá! Ojú wa rí, a ṣe IVF, oyún ìbeji bàjẹ́ kí á tó di ọlọ́mọ láyé - Adesua àti Banky W Dáa padà! Àwọn alátìlẹ́yìn Buhari fàdúrà jagun lòdì sáwọn tó ń fẹ̀hẹ́nùhàn lé e kúrò ní London Ọlọ́pàá fọhùn pé ẹgbẹ́ IPOB ni àwọn agbébọn tú ẹlẹ́wọ̀n 1,844 sílẹ̀ ní ọgbà ẹ̀wọ̀n Owerri Gbogbo ìbéèrè tóo ní lọ́kàn nípa dída omira obìnrin lásìkò ìbálòpọ̀, ìdáhùn rèé Kọmisọna ọlọpaa ipinlẹ Ekiti Tunde Mobayo, sọ pe lasiko ti oninure kan ladugbo ranṣẹ pé awọn ọlọpaa ni awọn ikọ oun sare lọ ibi iṣẹlẹ naa ti wọn si fi ọgbọọgbọn SEED doola awọn ọmọ náà. ""Kete ni a ko awọn ọmọ mejeeji lọ ile iwosan fun ayẹwo ati itọju ti iwadii naa si n lọ lọwọ, sugbọn awọn yoo pese aabo to yẹ fun awọn ibeji naa ati iya wọn, Mobayo fidi eyi mulẹ. Agbẹnusọ ọlọpaa ipinlẹ naa Sunday Abutu to sọ eyi di mimọ ninu atẹjade kan ni ipinlẹ Ekiti pẹlu akọle: 'Ọlọpaa Ekiti doola awọn ibeji' salaye pe awọn gba ipe ijaya pe obinrin kan ti awọn ibeji ti ọjọ ori wọn ko ju ọdun meji lọ mọle ti ko si fun wọn lonjẹ pẹlu ati pe oun yoo pa wọn ti ẹnikẹni ba mu oun ni tulasi lati ṣilẹkun. Àwọn èdè abẹ́ ahọ́n tóo lè fi sọ̀rọ̀ rèé láì tú àṣírí ọ̀rọ̀ rẹ áyé ""Ikọ awọn oniṣẹ pajawiri ni kete ti ipe yii wọle ni wọn gbe igbesẹ lati doola awọn ọmọ mejeeji. Lasiko ifọrọwanilẹnuwo ni obinrin naa ni lati igba ti oun ti wa ninu oyun ni Baba wọn ti lọ si ilu Calabar ni ipinlẹ Cross River ti ko si pada wale mọ lati tọju oun ati awọn ọmọ rẹ. ""Gẹgẹ bi o ṣe sọ, oun ko tilẹ le bọ ẹnu ara Kato wa sọ awọn ọmọ meji naa nitori iru ti oun n ṣe ko lọ dede mọ. Awọn meji naa ti ọwọ airi itọju wa lara wọn, ko le duro tabi rin ti ẹnikẹni ko ba ran wọn lọwọ nitori airi oúnjẹ jẹ."" Abutu sọ pe wọn ti ko awọn ọmọ mejeeji naa lọ si ile iwosan loju ẹsẹ fun ayẹwo, fi kun pe iwadii ti bẹrẹ sugbọn ri daju pe aabo to peye wa fun ìyá ati awọn ọmọ naa",0,yoruba a dupe pe opin ose de iyen ja si isimi fun wa,0,yoruba "Àkọ́kọ́, Alàji joko lòdì Ìbàdàn. Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.. A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..",0,yoruba #UEFAawards: Van Dijk gbadé UEFA mọ́ Messi àti Ronaldo lọ́wọ́,0,yoruba jẹ́ ìlú tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó wáyé..,0,yoruba "ti a wà kódà ni Kansu tí so pé kí àwọn ọdọ máa kopa títi di asiko yii, wípé komisona ni ó, gómìnà ni, ọdọ náà ni, tí ẹ bá wo irin àjò wá láti ìgbà yẹn sì asiko yii, o ju irẹ ni a fi ṣe mí ó fi ona kankan tán yín rárá. - @user",0,yoruba "Ní nígbà àkerekere, Ọba ri Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba Kunle Fela Anikulapo-Kuti: Olótìítọ́ ni Fẹla,0,yoruba "fi, Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.",0,yoruba "aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìṣẹ́ ọ̀pọ́lọ̀.",0,yoruba "Ninu iwadi kan ti wọn ṣẹṣẹ gbe jade, ajọ naa to jẹ ẹka ajọ iṣọkan agbaye ṣalaye pe ida mọkandinlogun iye iku ọmọde ni Naijiria lọdun 2018 lo tatara otutu igba aya wa. Ajọ ọhun tẹsiwaju pe ohun to saba ma n fa aisan yii ni aijẹun daada, eefin latara eedu ti wọn fi n dana ninu ile to fi mọ fifa atẹgun buruku simu layika. Aisan otutu igba aya yii a maa ṣakoba fun ẹdọ foro ti ọyun a si maa ko si inu rẹ. Ninu iwaadi ti wọn gbe jade, lagbaye lọdun 2018, otutu igba aya pa ọmọ tọjọ ori wọn ko to ọdun marun un to le ni 800,000. Lara awọn ọmọ to ba aisan yii lọ la ti ri o kere tan ọmọ Naijiria 162,000 to tunmọ si pe ọmọ 443 lo n ku lojumọ kan ti mejidinlogun a si maa ba aisan yii lọ ni wakati kọọkan. Jálà epo bẹntiróò di N600 nítorí ibodè títìpa Wo Bullet, ọmọ ọdun mẹjọ tó fẹ́ lùwẹ̀ wọ Olympics Ninu ọrọ adele aṣoju ajọ Unicef ni Naijiria, Pernille Ironside, o sọ pe ''aisan to le la ẹmi lọ ni otutu igba aya jẹ ti o si ti mu ọpọ ẹmi awọn ọmọde lọ ni Naijiria toun ti pe o ṣe dena.'' O fikun ọrọ rẹ pe pupọ awọn ileeṣẹ ati ẹka to n mojuto ilera lo ti gbagbe nipa rẹ ṣugbọn asiko to bayi lati mu ayipada wa'' Yatọ si orileede Naijiria awọn orileede mẹrin miiran ni itankalẹ aisan yi ti pakasọ. Awọn orileede naa ni India, Pakistan, DR Congo ati Ethiopia.",0,yoruba "Ìṣẹ̀lẹ̀ tó fara jọ èyí ṣẹlẹ̀ ní 2016 , lẹ́yìnin rògbòdìyàn sáà kẹ́ta Ààrẹ náà , nígbà tí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ nílé ẹ̀kọ́ kọ ìkọkúkọ sórí àwòrán ( Ààrẹ ) Nkurunziza nínú ìwé ìkọ́ni .",0,yoruba "Idije Premier League Lẹyin ti Everton pokọ iya fun Manchester United ni papa isẹre Goodison Park tan ni Crystal Palace ki Arsenal mọ lẹ nile wọn ti wọn si ki bẹndẹ siwọn ninu. Ami ayo mẹta si meji ni Palace fi ṣagba fun awọn Gunners nile wọ. Helen Paul sọ idi tó fi gba orúkọ ní kékere Arsenal si wa ni ipo kẹrin lori tabili Premier League, ṣugbọn Chelsea yoo gba ipo naa mọ wọn lọwọ ti wọn ba jawe olubori ninu ifẹsẹwọnsẹ ti wọn lọjọ Aje. Esi ere bọọlu yii jẹ iyalẹnu fun awọn ololufẹ ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal lẹyin ti wọn na Napoli tan ninu idijẹ Europa League.",0,yoruba aláìì a yi da ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ìyá lo ìgbà ọkọ.,0,yoruba "Àwọn àjèjì oníwà ìpáǹle Fulah (Fúlàní) yìí ló yí orúkọ Gobir padà, wọ́n sọ ọ́ di Ṣókótó. Wọ́n ri àsíá wọn mọlẹ̀. Gobir di ti Fúlàní. #Darandaran #ItanFulani #Sokoto",0,yoruba "Dangote kede bẹẹ nigba to n fesi si osuba nla ti ẹni to jawe olubori ninu idije tileesẹ Dangote to n pese simẹnti se fawọn onibara rẹ nipinlẹ Ondo ati Delta. Dangote, ẹni to rọ awọn ọmọ Naijiria lati mase sọ ireti ti wọn ni ninu orilẹede yii nu nitori pe ọla si maa dara, tun ni ohun ayọ lo maa n jẹ fun oun lati ran awọn alaini lọwọ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Bakan naa lo salaye pe oun mọọmọ maa dokowo kaakiri nitori ifẹ ti oun ni lati maa fi ọwọ kan awọn ti ko ri jajẹ lawujọ, ki oun si mu agbega ba igbe aye ọmọ Naijiria kọọkan. O fikun pe ohun to mu ki idije ti ileesẹ simẹnti ohun se ni irufẹ ẹbun ti awọn onibara n jẹ, nitori afojusun ileesẹ naa ni lati ro onibara wọn lagbara latipasẹ idije ọhun. Ninu idije tileesẹ aposimẹnti Dangote se naa, ẹnikan to ti jẹ Kanselọ ri nijọba ibilẹ kan nilu Akurẹ, to ti wa di ẹni to n yọ bulọọku ile bayii lo jẹ ẹbun akọkọ. Lara awọn ẹbun ti awọn onibara si jẹ ni ọkọ ayọkẹlẹ, kẹkẹ ẹlẹsẹ mẹta, ati ọkada, eyi ti yoo mu ki ọrọ aje awọn onibara Dangote ru gọgọ si, ti wọn yoo si tun ni anfaani lati dokowo ni ọna miran, ti owo yoo si tun maa wọle fun wọn.",0,yoruba Pápàpá iṣẹ́ tòní ń tán lọ. Ó wá ku fàájì pẹrẹhu. Àríyá kẹlẹlẹ.,0,yoruba tí a kọ eḳọ nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọba lo ìgbà ọkọ.,0,yoruba ọ̀run dídì. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba "Atamatase agbabọọlu Newcastle, Alexander Isak lee maa gba bọọlu mọ titi di ẹyin idije ife ẹyẹ agbaye loṣu kejila. Gẹgẹbi ọrọ ti akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu Newcastle, Eddie Howe sọ, Isak fi itan rẹ ṣeṣe ni eyi ni yoo si mu ki o maa lee tayo lori papa fun igba diẹ. Igba mẹta pere ni Isak tii gba bọọlu fun Newcastle lati igba ti wọn ti ra a ni ọgọta miliọnu pọun lati Real Sociedad loṣu kẹjọ. Bakan naa ni Diego Jota agbabọọlu Liverpool pẹlu. O gba goolu wọle sawọn ni ifẹsẹwọnsẹ akọkọ akọkọ rẹ tako Liverpool. Lasiko to n gbaradi fun ifẹsẹwọnsẹ kan fun ikọ orilẹede rẹ Sweden loṣu kẹsan an ni Isak fi itan rẹ ṣeṣe. “O ṣeni laanu pe itan rẹ to fi ṣeṣe yoo ṣediwọ fun un. A ko lero pe a o le ri Alex lori papa ki idije ife ẹyẹ agbaye to bẹrẹ” Idije ife ẹyẹ agbaye yoo bẹrẹ logunjọ oṣu kọkanla ni orilẹede Qatar. Jota fi ẹsẹ pa lasiko ifẹsẹwọnsẹ Liverpool pẹlu Manchester City lọjọ Aiku. Akọnimọọgba ikọ Liverpool, Jurgen Klopp sọ fun awọn akọroyin pe Diego Jota to ṣeeṣe ko ṣoju fun Portugal ni ife ẹyẹ agbaye ko ni lee kopa nitori o ti fi ẹsẹ ṣeṣe. Wọn gbe Jota kuro lori papa lasiko ti ifẹsẹwọnsẹ naa n mura ati pari ni papa iṣire Anfield. Iroyin ayọ ibẹ ni pe Jota ko ni ṣe iṣẹ abẹ lati tọju ohun to n ṣe e naa. Jurgen Klopp ṣalaye lasiko to n ba awọn  akọroyin sọrọ ni igbaradi fun ifẹsẹwọnsẹ pẹlu Westham United pe “iroyin ti ko dara to  nipa Diogo.” Klopp ko sọ pato asiko ti Jota yoo pada, amọṣa o ni ipa ti ko ṣee fẹnusọ ni aisi lori papa rẹ yoo mu ba ikọ naa",0,yoruba "Ni kete ti wọn kede esi ibo ọdun 2015 tan ni aarẹ naa lọ sibi igbeyawo Bello El-Rufai to jẹ ọmọ gomina ipinlẹ, Kaduna, Nasir Ahmad El-Rufai. Ninu osu kejila ọdun 2016 ni Aarẹ Buhari sin ọmọ rẹ, Zahra, nigba to fi fun Ahmed Indimi. Ogunlogo awọn oloselu lo pe si mọṣalaṣi nla to wa l'Abuja ati ile ijọba nibi igbeyawo ọhun. Lẹyin igba naa, Aarẹ, Buhari ati awọn gomina mejilelogun (22) ni wọn pe sibi igbeyawo ọmọ gomina ipinlẹ Ọyọ ati tipinlẹ Kano ninu osu kẹta. Buhari ati awọn gomina mejilelogun (22) ni wọn pe sibi igbeyawo ọmọ gomina ipinlẹ Ọyọ ati tipinlẹ Kano ninu osu kẹta Nibi igbewo yi Buhari lo se asoju ọkọ iyawo, Idris Ajimobi, to si san owo ori fun Asiwaju Bọla Tinubu, to ṣe asoju iyawo, Fatima Umar Ganduje. Nigba ti ẹni to lowo ju l'Afrika, Dangote fẹ f'ọmọ rẹ l'ọkọ, Aarẹ Buhari lo ṣe asoju iyawo, to si gba owo ori lọwọ asoju ọkọ iyawo l'ọjọ Ẹti (Friday). L'ọjọ naa ni Aarẹ Buhari pada sile ijọba nibi ti wọn ti bẹrẹ ayẹyẹ igbeyawo Damilọla Ọsinbajo, to jẹ ọmọ igbakeji Aarẹ, Yẹmi Ọsinbajo. T'ẹrin t'ayọ ni Aarẹ Buhari fi ba t'ọkọ t'aya ya aworan pẹlu awọn obi wọn.",0,yoruba "ìbàdandun ìlú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.",0,yoruba "Bí mo ti ṣe sọ ṣíwájú, oríṣi eégún lówà, lẹ́yìn Ológbojò tó jẹ́ eégún àkọ́kọ́ (àwọn kan gbà pé Ológbojò kò sí nínú eégún) #AraOrunKinkin",0,yoruba "Owo omode ko to pepe, ti agbalagba k'owo keregbe #yoruba #TweetinYoruba",0,yoruba "Nigba ti ile igbimọ aṣojusofin si fọwọ si aba naa, ṣe lo kuna nile aṣofin agba gẹgẹ bi Godswill Akpabio to jẹ adari ẹgbẹ to kere ju nile ko ṣe gba a wọle. Bakan naa, Bukola Saraki to jẹ aarẹ ile igbimọ aṣofin nigba naa ni ki wọn ni ki wọn kọkọ gbe abadofin ọhun ti na ki ijọba fi ṣe awọn atunṣe kan ki wọn wa gbe e pada wa ṣugbọn eleyi ko ṣẹlẹ titi ti saa wọn fi pari. Toyin Atoyebi mechanic: Ẹ wo Toyin, ọmọbinrin ọdún 16 tó ń tún skadà àti gẹnẹrátọ̀ ṣe ní Nigba to tun di inu oṣu keje ọdun 2020, ijọba tun un gbe wa siwaju ile igbimọ aṣofin kẹsan eyi si ti n mu ọpọ ọmọ Naijiria yari fohun silẹ. Lara awọn to ti kẹnu bọ ọrọ abadofin yii ni Ọjọgbọn Wole Soyinka, gomina Samuel Otorm ti ipinlẹ Benue, ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ́, Afenifere ati bẹẹ bẹẹ lọ tori naa, o lee koba irẹpọ orilẹede. Ẹwẹ, ijọba ti ṣalaye pe abadofin to ti wa niwaju ile igbimọ aṣofin kii ṣe tuntun bi ko ṣe pe ijọba kan fi awọn nkan kọọkan kun aba naa ni ko le wa ni ibamu pẹlu bi wọn ṣe n ṣe lagbaye. Ki ni abadofin lori omi fun ọdun 2020? Ofin mẹrin ọtọọtọ ni ijọba ko papọ di odidi kan si abadofin lori omi fun ọdu n 2020. Abala ofin mẹrẹẹrin si jẹ ti ọdun 2004. Abadofin naa n wa ki abojuto gbogbo orisun omi yala loke eepẹ ni tabi labẹ ilẹ ko wa labẹ akoso ijọba apapọ. Gẹgẹ bi minisita eto iroyin ati aṣa, Lai Mohammed ṣe sọ, wọn ṣe alakalẹ abadofin ọhun lati pese abojuto nipa ikọṣẹmọṣẹ ti yoo si wulo fun gbogbo ọmọ Naijiria. O fi kun un pe ijọba ko lẹbọ kankan lẹru lori ọrọ yii. Ki lo n bi awọn eeyan ninu nipa abadofin yii? Section 98 Abala yii n sọ pe lilo omi yoo nilo gbigba iwe aṣẹ paapaa ko to bẹrẹ iṣẹ akanṣe. Section 104 Abadofin naa yoo fun ijọba lanfani lati mọ ẹni to ba n lo omi laloju ki ijọba le din iye omi ti idile kan yoo maa ri gba si dede iye ti wọn nilo gẹlẹ. Section 107 Ijọba yoo lanfani ati fagile iwe aṣẹ bi ẹnikẹni ba n lo omi nilokulo. Section 120 Awọn ọmọ Naijiria gbudọ gba aṣẹ ki wọn to gbẹ ilẹ fun ẹrọ omi borehole fun owo ṣiṣe tabi fun ile. Wọn gbudọ gba iwe aṣẹ agbẹkanga. Section 125 Awọn to ba laṣẹ nikan lo le maa ṣamojuto bi awọn eeyan ṣe n lo omi wọn si gbudọ ni kaadi idanimọ. Section 131 Bi oo ba tẹle awọn ofin yii, oo le lo omi. Awọn ipinlẹ yoo le ṣamojuto ni aarin ipinlẹ wọn ṣugbọn labẹ ofin ijọba apapọ. Ẹwẹ, ofin yii ti bori gbogbo ẹtọ ti ẹnikẹni ni tẹlẹ lati lo omi. Iha wo lawọn eeyan kọ si i? Gomina Benue, Samuel Ortom ni gbogbo ohun to wa ninu abadofin naa ko ba eyi to wa ninu iwe ofin lilo ilẹ mu torinaa o ni ijọba ni nkan mii ti wọn fẹ ṣe labẹlẹ. Ọjọgbọn Wole Soyinka kilọ ni tirẹ pe bi wọn ba file buwọlu u, yoo fun aarẹ ni gbogbo agbara lori gbogbo ọna omi lori ilẹ ati labẹ ilẹ. Bakan naa, awọn ẹgbẹ naa n bu ẹnu atẹ lu u. Esi ijọba Minisita eto iroyi ati aṣa, Lai Mohammed ati minisita to n ri si ọrọ omi, Amojuẹrọ Suleiman Adamu ṣalaye pe awọn to n bu ẹnu atẹ lu u ko tilẹ tii joko ka anfani rẹ, wọn kan n ka ohun tawọn eniyan n sọ ni.",0,yoruba "@user Bùrùkùtù àti ọtíkà kì í ṣe ẹmu, àti pé ara ọ̀pẹ nìkan ni a ti ń bẹ́ ẹmu, ògùrọ̀ ni ti ìko, kí á máa fi àdàbà wé tòlótòló, ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn kò jọ ara wọn, gedegbe ni wọ́n yàtọ̀.",0,yoruba Nkechi Blessing: Gbajúgbajà òṣèré ní ó sàn fún òun láì tíì lọ́kọ báyìí ju kí òun lọ́kọ láì láyọ lọ,0,yoruba "Ọwọ sinku awọn ọlọpa ti tẹ ọgọọrọ awọn ọmọ ẹgbẹ ẹlẹsin Shiite ti wọn n fẹhonu han nile asofin apapọ ilẹ wa nilu Abuja. Atẹjade kan ti osisẹ alarina ileesẹ ọlọpaa ilẹ wa, Anjuguri Manzah fisita salaye pe, oun ba imọ awọn ọmọ ẹgbẹ Shiite naa jẹ lati fi tipa gba akoso ile asofin apapọ ilẹ wa lọjọ Isẹgun. Atẹjade naa ni iwọde wọọrọwọ lawọn ọmọ Shiite naa fi boju kọrọ to bẹyin yọ, ti wọn si fẹ fi tipa wọ ile asofin apapọ amọ tawọn ọlọpaa to wa nibẹ ko gba fun wọn. Manza ni idi ree ti wọn fi yinbọn mọ ọlọpaa meji lẹsẹ, ti wọn si tun lo okuta ati ọkọ lati fi da ọgbẹ si ọlọpaa mẹfa lara, ti wọn si ti gbe wọn lọ sile iwosan. Atẹjade naa ni ọwọ awọn ọlọpaa ti ba ogoji ọmọ ẹgbẹ Shiite ti wọn kopa ninu iwọde naa, ti iwadi si ti n lọ lọwọ. Atẹjade naa wa rọ awọn olugbe ilu Abuja lati maa ba isẹ oojọ wọn lọ, ti alaafia si ti n pada jọba ni agbegbe naa. Ẹgbẹ Musulumi Shia ti fẹsun kan awọn ọlọpaa pe, wọn pa eeyan meji to n fẹhọnu han lasiko ti wọn wa se iwọde ni Ile Igbimọ Asofin apapọ ni ilu Abuja. Eyi waye lẹyin ti ẹgbẹ Shia se ifẹhọnu han lọ si Ile Igbimọ Asofin ni ilu Abuja, eleyii to fa yanpọn-yanrin laaarin Shia ati awọn ẹsọ alaabo Ile Igbimọ Asofin. Iroyin fikun un wi pe, awọn ẹgbẹ Shia to wa se ifẹhọnu han naa le ni ẹgbẹẹrun, ti wọn si koju awọn ọlọpaa, ki o to di wi pe awọn ọlọpaa koju wọn. Gbogbo ilẹkun to wọ ile igbimọ asofin naa ni wọn ti ti bayii, ti awọn asofin ko si le e jade.",0,yoruba Ààtò-ìgasí _Ìwé-ẹ̀rí,0,yoruba "7. Yàtọ̀ sí ìbẹ́ta, orúkọ àmútọ̀runwá wo ni à ń pe ọmọ mẹ́ta tí a bí papọ̀? #Ibeere #Yoruba #learnyoruba #language #speakyoruba #MotherTongueDay https://t.co/Al48MtWRYS",0,yoruba "Ẹ̀rù bà á, kò le è gbé ọmọ titun padà síletò ni ó bá gbé e jù sílẹ̀ nínú igbó. #ItanObaIgala #Yoruba #Kogi #Igala",0,yoruba àwọn ènìyàn ni ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa iṣẹ́: ti o ní wúlò.,0,yoruba mikel ò wá sí àbí ó wá ṣé ẹ̀yin ríi lóríi pápá ni,0,yoruba yi lo ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba nípa ẹkọ́: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba Lo àwọn àwọ̀ rẹ,0,yoruba "Nitori eyi, ara eni lo ni Nitori eyi, ara eni lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba lẹ ìkòkò wey ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba ẹni tó ní òwú ò tẹ́rù èyí tí ó fi tan ná ló mú dání conclusions are informed by perspectives,0,yoruba "RT @user: @user Koni da fun eeeee, iwo oloriburuku algbako eda yi, iwo alaye abamo… Do your worst Big Fool #Animal #Buhariisanani…",0,yoruba Ìlú yorubá lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó ga jù.,0,yoruba Bí #Charleyboy sí #Anthony ṣe rí nírọ̀lẹ́ yìí rè é. Àwọn ti ọ̀nà #Ikorodu ló fà á o @user http://t.co/2Yu5IcBgrh,0,yoruba jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò.,0,yoruba Àtẹ̀jáde ìtúmọ̀ 22 Èbìbì 2019 13 : 12 GMT,0,yoruba "Ikọ Manchester City ti sun si ipo kẹta lori tabili Igba meji ọtọtọ ni Kevin De Bryne sọ bọọlu sinu awọn ikọ Arsenal ninu ifẹsẹwọn naa. Goolu rẹ akọkọ waye ni iṣeju keji ti ifẹsẹwọnsẹ ọhun bẹrẹ. Lẹyin igba diẹ sii ni Raheem Sterlin sọ goolu tirẹ sinu awọn Arsenal pẹlu iranlọwọ De Bryne yii kan naa. Ninu abala keji ifẹsẹwọnsẹ ọhun ni Kelvin De Bruyne sọ goolu keji rẹ sinu awọn, eyii to mu goolu ikọ rẹ pe mẹta. Aṣeyọri ikọ Manchester City ninu ifẹsẹwọnsẹ yii ti mu ki wọn sun si ipo kẹta lori tabili, ti Chelsea ati Tottenham si n tẹlẹ wọn lẹyin. Brain Squad: Àwọn ọmọdébìnrin Nàìjíríà ṣe ""App"" ìrànwọ́ owó iléèwè",0,yoruba "Bẹ́ẹ̀ ni, ewé amára ṣe gírí ni. Odù ìfọ̀rọ̀ṣeré tún yọ, bí a bá fi ewé ọfẹ gbéra, a ò ní mọ̀ pé a rìn rárá, kọ́nbọ́nkọ́nbọ́n ni. https://t.co/0ycmXe98Gu",0,yoruba "òní.. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "Goolu ti Javier Hernandez je dakun isoro Chelsea ni saa league ọdun yi Ni saa bọọlu ọdun yi, kaka ko mi san lara iya ajẹ́ ni ọrọ chelsea, amọ to n fi gbogbo ọmọ rẹ bi obinrin, ti ẹyẹ wa n yi lu ẹyẹ gbaa, nitori, ọpọ ipenija ni ẹgbẹ naa koju, to si dabi wi pe, ẹni to ti mọọ se ri, ko fẹ mọọ se mọ. Lọjọ ti wọn se iranti gbajugbaja ọmọ ẹgbẹ agbabọọlu naa nigba kan ri, Ray Wilkins to dologbe, Chelsea kọ lati bori West Ham. Olukọni ẹgbẹ naa, Antonio Conte ni, gbogbo awọn lawọn jo lẹbi aisedede naa. End of Twitter post, 1 Ọmi ti wọn gba ninu ifẹsẹwọnsẹse naa se okunfa bi West Ham ti se ja kuro lagbami ijakule pẹlu ami mẹfa sugbọn bi nnkan ti se ri, ko daju pe wọn yoo le kopa ninu Champions League lọdun to n bọ.",0,yoruba "ìgbà mi owó àkokò, Ọba ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..",0,yoruba ènìyàn a yi da ti o ní wúlò.,0,yoruba Omicron Covid 19: Kíni ìdí tí Nàìjíríà ṣe wà lára àwọn orílẹ̀-èdè tó léwu láti rírínàjò lágbàyé?,0,yoruba àìmọ́. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó ṣe pàtàkì.,0,yoruba "ó wọ́pọ̀ ní orílẹ̀ èdè Ilẹ̀ Adúláwọ̀ méje : Algeria , Cameroon , Ethiopia , Nigeria , Sudan , Tunisia àti Uganda .",0,yoruba jagunjagun ò ṣe é fi ogun mú,0,yoruba nínú oṣù Ẹrẹ́nà ọdún 2018 .,0,yoruba #DidYouKnow ju awọn ọmọ Afirika 5 000 000 lọ lori Twitter. Ọpọlọpọ wa lati awọn orilẹ-ede wọnyi: ZA 🇿🇦 NG 🇳🇬 KE 🇰🇪 ET 🇪🇹 TZ 🇹🇿 ZIM 🇿🇼 nibi ti ọpọlọpọ awọn ede Afirika ti awọn ori oke10 wa lati. Ṣe o mọ eyi? #Yoruba #AfricanLanguagesDay #IsComingSoon https://t.co/atUqRyw2om,0,yoruba "O ti pẹ diẹ ti orilẹede Naijiria ti gba ife ẹyẹ awọn ẹgbẹ agbabọọlu ni ilẹ Afirika kẹyin Awọn ikọ agbabọọlu naa ni MFM, Plateau United, Enyimba ati Akwa United. Eyi si ni igba akọkọ ninu itan idije naa ti orilẹede Naijiria yoo maa ni ikọ agbabọọlu mẹrin ọtọọtọ ninu idje naa. Eyi ko sa dede waye bikose pẹlu bi ẹgbẹ agbabọọlu MFM ati Plateau united to n soju orilẹede Naijiria tẹlẹ ninu idije CAF champions league se fidirẹmi lopin ọsẹ. Iroyin ayọ ni fun orilẹede Naijiria latọdọ awọn ikọ ẹgbẹ agbabọọlu to kopa ni idije Confederations cup Ẹgbẹ agbabọọlu MC Algers fi iya jẹ MFM pẹlu ami ayo mẹfa si odo lati ja kuro ni idije Champions league. Bẹẹ naa ni ami ayo kan ti Plateau United fi gbẹyẹ lọwọ Etuile du Sahel ko to lati pa ami ayo mẹrin si meji ti Etuile fi gbẹyẹ mọ wọn lọwọ ni abala akọkọ ifẹsẹwọnsẹ naa to waye lorilẹede Tunisia saaju rẹ. Iroyin ayọ ni lẹkunrẹrẹ fun orilẹede Naijiria latọdọ awọn ikọ ẹgbẹ agbabọọlu to kopa ninu idije Confederations cup lati ibẹẹrẹ pẹpẹ, iyẹn Enyimba ati Akwa United. Enyimba na Energie lati orilẹede Benin pẹlu ayo mẹta si meji eyi to sọ gbogbo ayo ti wọn gba di marun si meji. Akwa united pẹlu na Al ittihad pẹlu ayo mẹta si meji ni ipele gbe silẹ ko gba sile Penalties lẹyin ti wọn ta ọmi. Idije Liigi Naijiria Bakanaa ni idije liigi premiership orilẹede Naijiria waye lopin ọsẹ to kọja. Lẹyin ifẹsẹwọnsẹ to waye, ẹgbẹ agbabọọlu Lobi stars, kano Pillars ati Akwa United lo di ipo kinni, ikeji ati ikẹta mu nigbati Kwara United, Go Round, Heartland ati FC Ifeanyi Uba wa ni isalẹ tabili igbelewọn liigi orilẹede naijiria. Atẹ igbelewọn liigi premiership orilẹ̀ede Naijiria. Orisun: League Management Company, LMC",0,yoruba Àtẹ̀jáde ìtúmọ̀ 7 Èrèlé 2019 10 : 57 GMT,0,yoruba "Iṣẹ́ èwe bẹ àgbà k'ágbà má ṣe kọ̀ mọ́, gbogbo wa la níṣẹ́ a jọ ń bẹra wa. #EsinOro #Yoruba",0,yoruba "Mothers day: Lẹ́yìn Olorun, Ìyá mi ló kù- Papa Ajasco, Abiodun Ayeyinka",0,yoruba Àwọn òpó ní àwòṣe ọnà ilée ionic àti Corinthian .,0,yoruba "Sam Clucas gba ami ayo meji wọle ninu idije ti asọle Arsenal Petr Cech ti se asise l'ojule Ọmọ agbabọọlu Swansea Jordan Ayew f'agba han Cech loju'le nigbati ti o gba amin ayo kan wọle. Eyi jẹ ikunọ fun ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal lẹyin ti Sam Clucas ti gba ami ayo meji s'ojule. Ikọ Arsenal bi jabọ si ipo kẹfa lori tabili liigi, ti wọn to s'ẹhin ikọ Liverpool ti o wa ni ipo kẹrin. Ikọ Arsenal bi jabọ si ipo kẹfa lori tabili liigi, ti wọn to s'ẹhin ikọ Liverpool ti o wa ni ipo kẹrin Akọni-mọọgba fun ẹgbẹ Arsenal, Arsene Wenger ti salaye wipe awọn asise ti awọn ọmọ ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal se lori papa lo se okunfa ijakulẹ ninu idije naa. O wi siwaju sii pe loni ni awọn yoo mọ nipa boya ọmọ ẹgbẹ agbabọọlu Borrusia Dortmund, Pierre-Emerick Aubameyang yoo darapọ mọ wọn tabi bẹẹkọ.",0,yoruba "Lati ọjọ Ẹti to kọja ti gbajumọ olorin ẹmi, Osinachi Nwachukwu, ti di oloogbe, ni ọpọ ti n darukọ ọkọ rẹ, Peter Nwachukwu pe o lọwọ si iku rẹ. Ọpọ eeyan to mọ tọkọtaya naa, to fi mọ gbajumọ olorin ẹmi, Frank Edwards, lo n jẹri pe Ọgbẹni Nwachukwu lo lu iyawo rẹ pa. Lọwọlọwọ, Peter Nwachukwu ti wa ni ahamọ ọlọpaa nilu Abuja, nibi ti wọn ti n fi ọrọ wa l'ẹnu wo. Mama Osinachi, Arabinrin Madu, sọ fun BBC pe lẹyin ọdun mẹjọ ni oun to fi oju kan ọmọ oun nigba to ṣe igbeyawo pẹlu Peter. Bakan naa ni ẹbi naa sọ pe Ọgbẹni Nwachukwu ko gba ki Osinachi wa ẹbi rẹ tabi ki awọn naa o wa. Koda, wọn sọ pe awọn ti gbe kuro nile arakunrin naa ri, nigba to n fi iya jẹ. Ṣugbọn, oloogbe pada sile ọkọ rẹ ""nitori pe ko fẹ ki ẹnikẹni tu nkan ti Ọlọrun ti so pọ"". Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ti nawọ́ gán Peter Nwachukwu, ẹni tó jẹ́ ọkọ olórin ẹ̀mí, Osinachi Nwachukwu tó dágbére fáyé lọ́jọ́ Ẹtì tó kọjá. Ẹ̀sùn lílu ìyàwó rẹ̀ dójú ikú ni wọ́n fi kàn án. Agbẹnusọ iléeṣé ọlọ́pàá FCT, Josephine Adeh ló fi ìdí ọ̀rọ̀ ọ̀hún múlẹ̀ fún ikọ̀ ìròyìn BBC. Adeh ni àwọn nawọ́ gán Peter Nwachukwu lẹ́yìn tí ẹ̀gbọ́n olóògbé akọrin náà mú ẹjọ́ wá sí àgọ́ ọlọ́pàá láti fi ẹ̀sùn kàn ọkùnrin náà wí pé ó máa ń lu ìyàwó rẹ̀ nígbà tó wà láyé àti pé lílú tó lu obìnrin náà kẹ́yìn ló ṣekúpa. Agbẹnusọ ọlọ́pàá náà ní ìwádìí ti ń lọ lọ́wọ́ láti fìdí ìṣẹ̀lẹ̀ náà múlẹ̀. Kí ló ti ṣẹlẹ̀ sẹ́yìn? Láti ìgbà tí ìkédè ikú Osinachi ti jáde lọ́jọ́ Ẹtì ni àwọn ènìyàn ti ń gbe onírúurú ìròyìn lórí ayélujára wí pé níṣe ni ọkọ rẹ̀ máa ń lù ú bí i bàrà léyìí tí ọ̀pọ̀ gbàgbọ́ wí pé òhun ló ṣokùnfà ikú rẹ̀. Ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn akẹgbẹ́ rẹ̀ àti àwọn olólùfẹ́ akọrin ẹ̀mí náà ní gbogbo ìgbà ni ọkọ rẹ̀ máa ń nà án. Frank Edwards, tí òun náà jẹ́ akọrin ẹ̀mí, lórí Instagram ló kọ́kọ́ fẹ̀sùn kan ọkọ Osinachi wí pé gbogbo ìgbà ló máa ń sọ ìyàwó rẹ̀ di àpò ẹ̀ṣẹ́. Lẹ́yìn èyí ni ọ̀pọ̀lọpọ̀ náà ti ń bọ síta láti sọ ohun tí wọ́n mọ̀ nípa arábìnrin náà. Osinachi tó dágbére sáyé lẹ́ni ọdún méjìlélógójì ní ọjọ́ Ẹtì lẹ́yìn tó lo ọjọ́ mélòó kan ní ilé ìwòsàn kan ní ilú Abuja. Ìròyìn tó kọ́kọ́ jáde ni wí pé àìsàn jẹjẹrẹ ọ̀nà ọ̀fun ló ṣekúpa Osinachi àmọ́ àwọn ènìyàn rẹ̀ ní irọ́ tó jìnà sí òótọ̀ ni ìròyìn náà. Orin Ekwueme tí Osinachi ṣe pẹ̀lú Prospa Ochimana ló sọ di ìlúmọ̀ọ́ká. Bákan náà ló jẹ́ aṣáájú akọrin ìjọ Dunamis International Gospel Centre. Ọkọ àti àwọn ọmọ mẹ́rin ni Osinachi fi sáyé lọ. Awọn olólùfẹ́ orin ẹ̀mí ti n fi ọrọ ibanikẹdun sita lati ṣe idaro iku gbajugbaja olorin Kristẹni ọmọ Naijiria Osinachi Nwachukwu. Olorin naa to le ni ẹni ogójì ọdun dagbere faye lọjọ Ẹti n'ilu Abuja. Ọ̀rọ̀ ''Zoning'' ipò ààrẹ ní Naijiria dàbí àgbàlàgba tí wọ́n ń fún ní ''baby Formula'' - Dino Melaye Ọmọ Nàìjíríà àtàwọn orílẹ̀èdè mìí kò ní l'ánfàní láti ra ilé sí Canada mọ́ o! ìdí nìyí Wo àwọn ìlú tó jẹ́ ẹ̀ṣẹ̀ àti èèwọ̀ ni kí ènìyàn kú níbẹ̀ Ko to di pe o ku, Osinachi a maa kọ orin ẹ̀mí ti ilẹ yoo mi títí kódà ti awọn to n gbọ́ ọ yoo maa fi ọkan wọn sunmọ Ọlọrun. O máa n kọ iwe orin to sì di gbajumọ fun orin rẹ to kọ pẹlu gbajumọ olorin míì Prospa Ochimana ""EKWUEWE"". Orin naa gbayii to de ibi pe o ti lé ní èèyàn milionu mọ́kànlélógún to tí woo lori YouTube. Osinachi tun ti ba ọpọlọpọ eeyan kọrin bíi orin ""Nara Ekele"" pẹlu ilumọọka Pasito àti adari ìjọ Dunamis International, Pasito Paul Enenche to tun jẹ Pasito fún Osinachi torí o wa lara awọn adari orin akọrin ìjọ Dunamis. Bakan naa, o tun bá Ema kọ orin to gbajumọ yìí ""You no dey use me play ó"". Òun naa si ṣẹ̀ṣẹ̀ gbe orin kan jade ni to pé akọ́lé rẹ ni ""God of all power"". Ohun tí àwọn eeyan ko tun le gbagbe rẹ si ni pe o maa n fi ede abinibi rẹ, Igbo kọrin ni gbogbo igba ti ara àwọn to n gbọ́ ọ yoo si maa dìde. Osinachi fi ọkọ rẹ ati ọmọ mẹrin saye lọ. Latigba ti iroyin iku rẹ ti jade lori ayelujara làwọn akẹgbẹ rẹ ati awọn olólùfẹ́ rẹ ti n fi ọrọ ibanikẹdun síta lori ayelujara àti ránṣẹ́ si ẹbi rẹ. ""Ọjọ́ mẹfa sẹ́yìn péré ni mo pe Ọgbẹni Peter Nwachukwu láti fi erongba mi han pe mo fẹ́ gbe orin kan jade pẹlu ìyàwó rẹ Osinachi Nwachukwu ati pe ka jọ ṣepàdé papọ"", Edwin kọ èyí jáde lórí Facebook. Mo tọrọ àforíjì pé mo parọ́ ìgbéyàwó! Mi ò ṣe ìgbéyàwó kankan! Pásítọ̀ Leke Adeboye tọrọ̀ àforíjì ,ó kọ̀wé ẹ̀bẹ̀ sí àwọn pásítọ̀ ìjọ tó kàn labùku ""Wọn gba ìpè mi wọlé àmọ́ wọn ni kí n fún àwọn ni akoko lati gbàdúrà nípa rẹ. Mo wá l'Abuja lọjọ Aje tí mo sì tún pe wọn, wọn ní àwọn yoo da ìpè mi padà"". Edwin ni gbogbo ọjọ kejì ni fóònù wọn fi wa ni pípa ""afi to di asiko yii ti mo ri ìròyìn náà, mo si pe wọn láti gbọ́ òótọ́ boya o ṣẹlẹ̀, èyí dun mi gidi gan, mi ò sì gbagbọ pé o ṣẹlẹ̀ "".",0,yoruba níjó òní nípa ìya ìlú lo je gbogbo ise ibile tèmi.,0,yoruba "Agbẹnusọ fun gomina Seyi Makinde, Taiwo Adisalo sọ bẹ ninu atẹjade kan to fi sọwọ si awọn akọroyin. Adisa sọ ninu atẹjade naa pe irọ nla ni pe ijọba ipinlẹ Oyo lo n fi ọrọ isinkun ọhun falẹ gẹgẹ bi ahesọ ti awọn kan n gbe kiri. O ni ""Iroyin ofege yii ti awọn kan n sọ kiri jẹ ọna lati mọọmọ ba orukọ ijọba ipinlẹ Oyo jẹ ati lati ti ọrọ oṣelu bọ eto isinku oloogbe naa."" Adisa tẹsiwaju pe iroyin ofege ọhun bẹrẹ lati oju opo ikansiraẹni lori itakun agbaye, ko ti de pe awọn ileeṣẹ iroyin abẹle kan bẹrẹ si n pin iroyin naa kiri. O ni ""Ọpọ ileeṣẹ iroyin lo kan si ọfiisi gomina lọjọ Abamẹta lati bere bi ọrọ naa ṣe jẹ."" ""A fẹ jẹ ko han si gbogbo eeyan pe gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde ko lọwọ ninu bi eto isinku gomina ana, Abiola Ajimobi ṣe falẹ."" Ìkúnlẹ̀ abiyamọ o, ẹ̀yin olóògùn àyé, àjẹ́, oṣó, ẹ wá gbà wá ní Akínyelé, ìkú yíí ti pọ̀jù! Wo àwọn èèyaǹ jàǹkàn mérin tí àrùn Coronavirus ti sọ dèrò ọ̀run ní Naijiria Adisa ni awọn mọlẹbi oloogbe ọhun kan si ijọba lati sin oku rẹ si ori ilẹ kan ni Agodi GRA, ṣugbọn ẹjọ ṣi wa lori ilẹ naa, eyi to jẹ ko ṣoro lati fọwọ si pe ki wọn sin gomina ana ọhun sori ilẹ naa. O tẹsiwaju pe gomina Seyi Makinde gba ki wọn sin oku naa si ori ilẹ rẹ to wa ni Oluyole Estate, bo tilẹ jẹ pe ko ba ofin to rọ mọ ọrọ ilẹ mu ni ipinlẹ Oyo. Ṣugbọn ijọba gba ki wọn sin oku na sibẹ ko ma ba si ede aiyede laarin ijọba ati mọlẹbi ologbe ọhun. Adisa pari ọrọ rẹ pe o lodi si ofin ipinlẹ Oyo lati sin oku si eyikeyi ninu Oluyole Estate tabi Agodi GRA.",0,yoruba "Onírọ́ ni Atiku, gbogbo irọ́ tó pa mọ́ mi ni mà á fèsì sí - Wike",0,yoruba Àwọn ìkúndùn,0,yoruba ilera ṣẹlẹ ni Lagos ti gbogbo eniyan sọ o ṣe pataki. (2005),0,yoruba rere. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìṣẹ̀: ti o nuni ti o pataki.,0,yoruba "Ṣe dáadáa le jí. A kú òpin ọ̀sẹ̀, ọ̀pọ̀ rẹ̀ la ó ṣe láyé ńbí. Kò kín ṣe ní sáà ilẹ̀. Àmín àṣẹ",0,yoruba "nípa ọlọ́run. Nitori eyi, ara eni lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Olobó ta Ṣàngó wípé Ògún ń gbé ìjà bọ̀, ni Ṣàngó yára f'ẹsẹ̀ fẹ́ ẹ, ó ku Ọya. #OsuOgun #Ifa #Yoruba #Ogun7",0,yoruba bọ́la yó ṣe rí ònìí la yó ti mọ̀ ìbò ọdúnun ǹjẹ́ báyìí náà kọ́ ni yó ṣe rí ìjọba màdàrú,0,yoruba "Tó bá jẹ́ òótọ́, a lo bọ́tìnì ipa _àtòjọ-ẹ̀yàn gẹ́gẹ́ bíi ipa ti a ti lè̀ kọ́ àwọn àkóónú àtòjọ-ẹ̀yàn.Tó bá jẹ́ irọ́, a máa pa bọ́tìnì ipa_àtòjọ-ẹ̀yàn tì. Bọ́tìnì yìí kàn wúlò tí bọ́tìnì irúfẹ́_nǹkan bá jẹ́ ""nǹkan_àtòjọ-ẹ̀yàn"".",0,yoruba AFCON 2019: Wo àwọn ẹranko tí wọ́n máa figagbaga ni Egypt,0,yoruba "RT @user: @user otida bàyí, esè gán. O mà sé aso fun okunrin ati obinrin na.",0,yoruba Jọ̀wọ́ rọra mu *Kẹ́míkà*,0,yoruba yi kún fún àwọn ìkòkò tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó wáyé..,0,yoruba "dídì. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Bàbá lo ni ìgbà mi owó àkokò, Ìyá lo tun se fi.",0,yoruba Corornavirus: Kini Gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti ṣe fun baba tọ ni ọmọ òun ko gbọdọ tèlé oun déle nitori o ṣẹ̀ṣẹ̀ de lati Eko?,0,yoruba oṣù karùnún ọdún ire ọwọ́ a bí márùnún jèrè àrún ni tia lóṣù èbìbí yìí a óò dá bí ẹdun a ó rọ̀ bí òwè láṣẹ ọbaòkè,0,yoruba Ìle-Ìfẹ̀. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.,0,yoruba kí ede yoruba mabaa pare agbudo kó awon omo wa lede na latara si soó siwon ni gbogbo igba,0,yoruba lẹ. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Alàji lo lọ.,0,yoruba pàtàkì wey ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo.,0,yoruba "Ooni ti Ile-Ifẹ, Oba Adeyeye Ogunwusi ti ní ó seése kí àwọn ọdaràn má mọ ìjàmbá tí wọ́n ń se fún ará ìlú. Ọba Ogunwusi ni o seese ki awọn ọdaran yii ma mọ ijamba ti wọn n se fun ara ilu, nitori naa, ti ọwọ ba tẹ awọn afurasi ọdaran wọn yii, ki wọn se ifọrọwanilẹnuwo fun wọn daadaa. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọba Ogunwusi gbe imọran ọhun kalẹ lasiko to n gbalejo awọn osisẹ agba ajọ EFCC ni aafin rẹ nilu Ile Ifẹ. Bakan naa, ni Ọọni tun ke gbajare lori bi iwa ọdaran se peleke si ni ipinlẹ Ọsun, to si kesi awọn ọdọ lati jawọ ninu iwakiwa, bẹẹ lo tun kesi ajọ naa lati fi agbara kun bi wọn se n gbogun ti iwa ọdaran ni awujọ. Ninu ọrọ ti wọn, ajọ EFCC naa wa rọ Oba Adeyeye Ogunwusi lati kesi awọn ọba ni ile Yoruba, ki awọn naa tiraka lati gbogun ti iwa ibajẹ ni agbeegbe wọn.",0,yoruba Ìbàdandun ni ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn. (Item 125),0,yoruba àwọn ènìyàn: ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ìyá lo lọ.,0,yoruba ènìyàn a yi yi ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba "àlùfáà ni ìwájú lojiji. Ọmọ lo tun se lọ. Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "ọ̀pọ́lọ̀ ni ìbàdandun àtọ́wọ́dá, àwọn oníṣẹ́ ìṣẹ́ ni a ní nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o dara.",0,yoruba lòdì Àbẹ́òkúta. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba "Oṣù kejì ọdún ní í s'ọdún di akọ ọdún. Ọdún mẹ́rin mẹ́rin akọ ọdún ni 2016, irúu rẹ̀ tún di 2020. Elédùmarè yóò pa wá mọ́.",0,yoruba "Yanponyanrin laarin ẹgbẹ oṣelu PDP ti n waye baye fun osẹ diẹ eleyii ti awọn alagbara kan ninu ẹgbẹ naa n pe fun Uche Secondus, alaga apapọ ẹgbẹ oṣelu naa. Lẹyin ti ile ẹjọ giga kan nipinlẹ Rivers ti ni ko yẹba naa ko si ye e pe ara rẹ ni alaga apapọ ẹgbẹ Oṣelu PDP lorilẹede Naijiria. Ọmọọba Uche Secondus ti ṣalaye pe ko si ohun kan to babara ninu rẹ ju wi pe ki oun pẹlu lọ si ile ẹjọ lati lọ da ile ẹjọ loun ipe rẹ. Onidajọ Okogbule Gbasam ti ileẹjọ giga ipinlẹ Rivers to wa ni Degema ni Portharcourt paṣẹ ni ọjọ Aje petiti di igba ti wọn yoo fi yanju ẹjọ naa o, Secondus ko gbọdọ oe ara rẹ tabi ṣe ojuṣe alaga apapọ ẹgbẹ oṣelu PDP. Ninu ọrọ ti amugbalẹgbẹ fun Ọmọọba Secondus sọ, alaga ẹgbẹ oṣelu PDP naa ni ẹruko ba oun boti wulẹ ko mọ lori ipẹjọ naa oun si setan lati yọju si ile ẹjọ lori rẹ. ""Bi ẹnikẹni ba gbe Secondus ati ẹgbẹ oṣelu PDP lọ sile ẹjọ, o di dandan, yoo farahan ni lati wi tẹnu rẹ. Awọn ọmọ Naijiria lo ni ẹgbẹ oṣelu yiio si tobi ju ẹnikẹni tabi ẹgbẹ kankan lọ titi kan awọn afipa du ipo"". Yanponyanrin laarin ẹgbẹ oṣelu PDP ti n waye baye fun osẹ diẹ eleyii ti awọn kan ninu ẹgbẹ naa ti gomina Nyesom Wike tipinlẹ Rivers ko sodi lati tun igbimọ isakoso ẹgbẹ naa ka. Iléẹjọ́ ní kí alága gbogboogbò PDP, Uche Secondus lọ rọọ́kùn nílé Rogbodiyan to n ṣẹlẹ ninu ẹgbẹ oṣelu PDP ti fori sọ ibi kan kan lójọ Aje, lẹyin ti ileẹjọ giga ipinlẹ Rivers ni ki ni alaga gbogbo ẹgbẹ naa, Uche Secondus lọ rọkun nile na. Eeyan mẹrin, Ibeabuchi Ernest Alex, Dennis Nna Amadi, Emmanuel Stephen ati Umezirike Onucha lo ni ki ileẹjọ da Secondus duro gẹgẹ bi alaga ẹgbẹ ọhun. Adajọ ileẹjọ giga ẹkun Degema, O. Gbasam sọ ninu idajọ rẹ pe aṣẹ gun ẹbẹ awọn mẹrin yii. Nkan ko fara rọ ninu ẹgbẹ PDP lori awuyewuye ati yọ Secondus nipo ṣaaju ipade gbogbogbo ẹgbẹ naa to n bọ lọna. Ẹwẹ, Secondus ti sọrọ lẹyin aṣẹ ile ẹjọ to ni ko gbọdọ pe ara rẹ ni alaga PDP mọ. Oludamọran Secondus lori ọrọ iroyin, Ike Abonyi sọ pe Secondus ṣetan lati sọ ti ẹnu rẹ ni ileẹjọ. O ni ẹgbẹ oṣelu PDP kii ṣe dukia ẹnikan, awọn ọmọ Naijiria lo ni i.",0,yoruba "@user kòlè yé e yín. Àmọ́ mo mọ̀ wípé á á dára. E lè dá 'promo' dúró fún 'gbà díẹ̀. Ẹ dákun, ẹ mọ́ bínú, ó kú díẹ̀ :)",0,yoruba "àlùfáà. Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.",0,yoruba àkùkọ kọ ajá gbó ẹyẹ́,0,yoruba ri pe jẹ́ pàtàkì wey ti o gbagbé ti jade pẹ̀lú àwọn alákòó.,0,yoruba ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìwà: ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó ga jù.,0,yoruba Inu ibanujẹ lọpọ awọn obi ọmọ Obìnrin Chibok wa Wọn ni Obìnrin kàn láran awọn tí boko-haram ji gbé to ribi sá mọ wọn lọwọ l'agbegbe ibẹ ló jẹri sí wí pé lootọ ní àwọn ọmọ obinrin náà wà lahamọ níbẹ. Wọn ṣàlàyé pé o sọfun awọn pe abúlé Garin Magaji ati Garin Mallam ní Marwa lariwa Cameroon ní àwọn ọmọ náà wà. Obinrin ohun ní ọpọ nínú wọn ló tí lọkọ ti wọn sì ti bímọ. Boko Haram yóò dá Leah sílé Alága ẹgbẹ́ àwọn òbí ọmọbinrin Chibok tí wọn jigbe ṣàlàyé fún BBC pé àwọn gbà obinrin náà gbọ nitoripe o juwe àwọn ọmọ àwọn yékéyéké. Yakubu Nkekeso ni obinrin naa sọ wi pe nnkan ko rọgbọ lawọn abule ti awọn ọmọ naa wa ti wọn si fẹ le ma ri ounjẹ jẹ nibẹ. Méjìléláàdọ́fà ninu ọ̀rìnlénígba din mẹrin awọn ọmọbinrin naa ti wọn jigbe ni wọn ko mọ ibi ti wọn wa bayi. Boko Haram ta taba cewa ta musuluntar da 'yan matan wadanda mafi yawansu Kiristoci ne Ijinigbe wọn lọdun 2014 mu ki awọn eeyan jankanjankan kaakiri agbaye pe fun itusilẹ wọn. Ninu wọn la ti ri iyawo Aarẹ Amerika ana Michelle Obama.,0,yoruba àkòrí ìṣàmúlò èdè abínibí fún ìdàgbàsókè ìbomirin àlàáfíà àti ìbálàjà,0,yoruba Ẹni a nbọ́ kòlè mọ̀ pé ìyàn mú. https://t.co/pMARvzWBEx,0,yoruba "ìbàdandun àtọ́wọ́dá, àwọn oníṣẹ́ ìṣẹ́ ni a ní nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó wáyé..",0,yoruba kí ni orúkọ ìperí fún ẹranko inú àwòrán yìí nílẹ̀ẹ káàárọ̀oòjíire,0,yoruba "tèmi. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "tí Ọba fè joko, Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..",0,yoruba ó wáyé. ti Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó ga ju lọ nínú Nàìjíríà.,0,yoruba "Agba ọjẹ kan nidi isẹ tiata, to jẹ odu, ti kii se aimọ fun oloko laarin awọn osere tiata, Ọmọọba Jide Kosọkọ ni ẹgbẹ awọn osere ori itage lede Yoruba, taa mọ si TAMPAN, ti n se gudugudu meje, ati yaya mẹfa fun eto adojutodo fawọn ọmọ ẹgbẹ naa. Kosoko ni amọ irufẹ eto adojutofo yii ko ba ti waye tipẹ fawọn osere tiata Yoruba, bi kii ba se ọpọ wọn to pagi dina eto naa nigba naa, apẹyinda iwa aidaa yii si ni ọpọ wọn to n saisan n jẹ loni yii. Jide Kosoko wa tun rọ awọn ọmọ ẹgbẹ osere tiata lede Yoruba lati maa tọju ara wọn, ki wọn ma si lo gbogbo owo ti wọn n ri lati fi jẹnu tan, amọ ki wọn pọn omi silẹ de oungbẹ fun ọjọ alẹ.",0,yoruba "Eku iro ile, esi ku dede asiko yii. Aki ara ile ero ona se alafia lawa bi? #TweetInYorubaDay #TweetinYoruba",0,yoruba "onà.. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa òkè: ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn ẹ̀kọ́ ọmọ aláwọ̀ wà níṣẹ̀.",0,yoruba """Ẹ jẹ́ kí Buhari lọ jókòó"" Aarẹ Buhari nigba to n ba awọn igbimọ alaṣẹ ṣe ipade ni ọjọ aje ni Abuja, fi kun un wipe ohun yoo dije si ipo aarẹ labẹ ẹgbẹ oṣelu APC lọdun 2019. Lara awọn ara ilu nigba ti wọn n ba BBC Yoruba s'ọrọ wipe igba ko lọ dede fun awọn, nitori naa ko yẹ ki aarẹ sọ wi pe oun n lọ fun saa keji. Ará ìlú f'èrò hàn lórí sáà kejì Bùhárí Ṣugbọn awọn miran sọ wi pe saa keji yoo fun aarẹ naa laaye lati pari gbogbo iṣẹ to bẹrẹ ni saa kini rẹ. Ninu ọrọ ti wọn, onimọ nipa eto oṣelu, Gbola Oba ati Kayode Eesuola sọ wi pe Aarẹ Muhammadu Buhari lẹtọ labẹ ofin lati dije gẹgẹbi aarẹ lẹlẹẹ keji. Ará ìlú f'èrò hàn lórí sáà kejì Bùhárí Amọ, wọn fikun un wipe awọn ọmọ Naijiria ni yoo woye gbogbo bi eto oṣelu saa aarẹ Buhari ṣe ri lalakọkọ, ki wọn to pinnu lati d'ibo fun lelekeji. Àwọn iròyin tì ẹ leè nífẹ̀ síí:",0,yoruba "Nígbà tí Bàbá fè lọ, A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà.. A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..",0,yoruba Prince Philip: Wọ́n yìbọn sókè káàkiri Ilẹ̀ Gẹ́ẹ̀sì láti ṣẹ̀yẹ Duke ti Edinburgh,0,yoruba Eḳọ tí a ní láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba o lẹ. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọba lo tun se fi.,0,yoruba nípa ẹkọ́: ti o nuni ti o tẹ.,0,yoruba "Ìwà ipá bẹ́ sílẹ̀ ní Guinea lọ́jọ́ 14 oṣù Ọ̀wàrà , tí ó ti fa ikú ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn tí wọ́n sì ń kó àwọn ènìyàn kiri lẹ́yìn ìyíde ìféhónúhàn tí ó tako ìjọba ààrẹ tí ó wà lórí oyè ìyẹn Alpha Condé , ẹni tí ó ń gbèrò láti yí ìwé - òfin padà kí ó bá fi ààyè gba òun láti lọ fún ìgbà kẹta .",0,yoruba osun ija nbo laarin oloye bisi akande ati asiwaju tinubu tolulope,0,yoruba vidíò yorubá tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa aráyé: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ àti ìbi tí wọn wà.,0,yoruba "Iroyin to n jade lọwọlọwọ ni pe olorin ẹmi to ti di ilumọka bayii laarin ọjọ mẹta pere, Yinka Alaseyori ti sọrọ soke si bi ogbontarigi olorin Tope Alabi ṣe sọrọ ni gbangba pe ko tọ ki o pe Ọlọrun ni ""Oniduro Mi"". O ti fi ọrọ ranṣẹ si Tope Alabi ati gbogbo eeyan. Adeyinka Alaseyori kọkọ ṣebi ẹni ti ko fẹ mẹnu ba ọrọ yii rara lati igba to ti ṣẹlẹ gẹgẹ bi ko ṣe ba ile iṣẹ́ iroyin kankan sọrọ lati ọjọ yii ti pada fọhun. Nibi ti Yinka Alaseyori ti n ṣe isin orin iyin lati ṣaami ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ lo ti bẹ gbogbo awọn eeyan lori ọrọ yii. Lo ba tun fi adura bọ ẹnu fun gbogbo awọn to n ṣe iṣẹ to jẹ ọna to tọ pe: ""gbogbo ẹyin tẹ n ṣe iṣẹ ọna to tọ to n mu ounjẹ wa sori tabili yin, ẹ o maa lowo sii ni"". Àjinigbé pa ọmọ méjì wọ́n ji méjì gbé lọ tí wan jẹ́ ọmọ òbí kan ni Ondo, Kí ló fa ikú akẹ́kọ̀ọ́ ẹni ọdún 23 yìí tí ọlópàá ba oku rẹ̀ nílé ìtura? Alaseyori kọ́ ló ni orin ""Oniduro Mi"", àmọ́ ìdí tí mi ò ṣe bá a jà pé ó jí orin mi kọ nìyìí - Tolu Adelegan Ìjọba Saudi dájọ́ ikú fún ọ̀dọ́ kan lórí ẹ̀ṣẹ̀ tó ṣẹ̀ láti kékéré, ìdí rèé Nǹkan tí a mọ̀ nípa ìlera Asiwaju Ahmed Tinubu Ayédèrú òṣìṣẹ́ ìjọba ni Baba Ijesha fà kalẹ́ ló jẹ́ kó ṣì wà láhámọ́ - Ọlọ́pàá Alaṣeyori ni ti oun ba ti ṣe tan nibi eto orin iyin naa, ounjẹ loun n lọ jẹ gẹgẹ bo ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ to jẹ ọjọ kẹrin oṣu kẹfa gangan amọ to ni ko saye lati ṣe ayẹyẹ afi titi di oni ti oun fi ṣe eto orin iyin. Lẹyin ọpọlọpọ wakati orin iyin ti akọroyin BBC Yoruba joko ti loju opo ayelujara Adeyinka Alaṣeyori funrarẹ, ti oun ati olorin ẹmi mii Dare Melody kọ lati fi ṣide eto naa, Alaseyori fẹ re si orin alujo tori o ni ""mo fẹ ki ẹ jo amọ mo fẹ fi Ọlọrun bẹ yin..."" Alaseyori ni ""mo kọkọ fẹ dupẹ lọwọ gbogbo eeyan kaakiri agbaye, loke okun ati nile nibi fun ifẹ yin. ""Mummy Tope Alabi, iyaa mi ni"". O tẹsiwaju pe: ""Iya ni Tope Alabi jẹ si mi, ọna kan tabi omiran si ni gbogbo wa ti jẹ anfani lara awọn orin rẹ... Ẹ jọwọ ẹ jẹ ki alafia jọba"". Alaseyori ti ijo ati ohun orin didun si ba nile tẹlẹ ti gbogbo ijo wa lara rẹ - lo ba ni kan si orin ati ijo si Ọlọrun ati fun awọn ololufẹ rẹ. Yinka Alaseyori ko mẹnu ba idi kankan ti ko fi yẹ ki o kọ orin naa gẹgẹ igun awọn eeyan kan ṣe n ja fun pe kii ṣe ohun gangan ni Ọlọrun fun ni orin naa lati kọ kalẹ. Iroyin ti a kojọ ati ifọrọwanilẹnuwo BBC Yoruba pẹlu ni ti o gba imisi orin naa gangan, Evangelist Toluwalase Aladelegan fihan pe ọdun 2014 ni Tolu gba imisi orin naa to si tun kọ jade ni ile ito orin pọ. Mo rí òkú TB Joshua tó yọ sí mi lẹ́yìn ikú rẹ̀ - Jaiye Kuti Wòlíì Genesis fèsì lórí ọ̀rọ̀ Tope Alabi nípa orin 'Oniduromi' Ẹwẹ, Alaṣeyori to jẹ́ olorin ẹmi to maa n kọ gbogbo orin yala tirẹ ni tabi ti ẹlomiran bi o ba ṣe ni idari kẹnu bọ awọn orin to wu awọn eeyan lori gan. Diẹ lara wọn niyii: Iṣẹ nla lẹ ṣe laye mi Ẹyin tẹ fun wa lowo tẹ́ẹ fun wa laṣọ, fun wa ni ipara, ẹ o maa lowo, lọla sii. Ọlọrun ko da bi eniyan, eeniyan aronipin... Iwo ko lo da mi, iwọ kọ lo bi mi, o si n sọrọ bi Eledumare Jesus na you big o, Ọga patapata... Ẹ ṣee aye ọpẹ yọ, mo dupẹ aye ọpẹ pada yọ N o la agbaye ja, n go si ri bi Ọba... Oniduro Mi ẹ ṣeun o...",0,yoruba Ẹbọ ní ńpa ẹlẹ́bọ...,0,yoruba "Awọn kan n fẹ ki Aarẹ Buhari din iye ti wọ̀n n ta jaala epo bẹtiro ku. Awọn ọmọ Naijiria ọhun fesi si ibeere kan ti BBC News Yoruba fi sita loju opo Facebook rẹ pe 'Ti ẹ ba ni anfaani iṣẹju meje pẹlu Aarẹ Buhari, ki lẹ o ba a sọ?'' Content is not available End of Facebook post, 1 A si ṣe akojọpọ diẹ lara awọn nkan ti wọn sọ. Ọ̀kan lara wọn, Adeniji Jacobson Gbenga sọ pe oun yoo ni ''ki Aarẹ Buhari o fi kurani bura fun mi pe ìwé ẹri ti ajọ WAEC fun òun kii se ayederu"". Laipẹ yii ni awuyewuye waye lori esi idanwo WAEC ti Buhari ṣe nigba to pari ileewe girama. Ọpọlọpọ eniyan lo n sọ pe Buhari ko joko sẹ idanwo naa. Lati ọdun 2015 to si ni awuyewuye naa ti di gbajugbaja, nitori pe Buhari ko fun ajọ eleto idibo Naijiria, INEC, ni iwe ẹri rẹ gẹgẹ bi ara ohun ti wọn n gba lọwọ ẹnikẹni to ba fẹ ẹ dupo oṣelu ni Naijiria. Àjọ WAEC ṣàfihàn ìwé ẹ̀rí girama Ààrẹ Muhammadu Buhari Ohun ti Buhari sọ nigba naa ni pe ọwọ ileeṣẹ ologun ni iwe ẹri oun wa, ti awọn eniyan si n sọ pe to ba jẹ lootọ ni, ki ileeṣẹ ologun fi sita. Awuyewuye naa lọ silẹ diẹ ko tun to di ọdun 2018 ti Buhari tun kọ lati fun ajọ INEC ni iwe ẹri naa nitori pe o fẹ tun dije fun ipo aarẹ l'ọdun 2019. Lẹyin ti ariwo pọ ni Buhari mu iwe ẹri kan lọ fun ajọ naa, eyi to tun bẹrẹ awuyewuye mi i. Minisita meji ninu eto iṣakoso Muhammadu Buhari ni wọn fi ẹsun ayederu iwe ẹri agunbanirọ kan; Kẹmi Adeọṣun ati Adebayọ Shittu. Diẹ lara awọn to dahun ibeere ọhun n fẹ ki Aarẹ Buhari sọ owo oṣu awọn oloṣelu dọgba pẹlu t'awọn oṣiṣẹ ijọba ni Naijiria. O ṣeeṣe ki esi wọn yi jẹyọ nitori ẹkunwo oṣu ti ẹgbẹ́ oṣiṣẹ ni Naijiria, NLC, n beere fun. Ẹgbẹ́ naa n fẹ ki ijọba maa san ọgbọ̀n ẹgbẹrun Naira gẹgẹ bi owo oṣu fun oṣiṣẹ to kere ju. Buhari tẹwọgba abọ ipade igbimọ to jiroro lori owo oṣu tuntun fun oṣiṣẹ lọjọ kẹfa, oṣu Kọkanla, ọdun 208 Bo tilẹ jẹ pe Aarẹ Buhari ko ti i le sọ owo oṣu tuntun naa di ofin, lai jẹ pe ile aṣofin buwọlu, ọpọlọpọ awọn gomina Nairia ti sọ pe awọn ko le san ju ẹgbẹrun mejilelogun atẹẹdẹgbẹta Naira. Maa sọ fun Buhari ko jawọ ninu oṣelu Awọn kan to tun kopa ninu ibeere naa ni awọn yoo gba aarẹ Buhari ni iyanju tabi sọ fun pe ko fẹhinti ninu oṣelu, ko si pada si ilu rẹ, Daura nipinlẹ Katsina. Lara wọn gbagbọ pe Buhari ti dagba kọja ẹni to yẹ ko wa lori aga iṣakoso. Igba akọkọ kọ niyi ti imọran yii jade si Buhari. Awọn kan si gba pe iṣakoso rẹ ko so eso rere fun orilẹede Naijiria. Sugbọn eyi ko di Buhari lọwọ lati ma polongo ibo fun ọdun 2019. Ṣaaju ọdun 2015 to ti bọ si ipo aarẹ Naijiria ni ọpọ ọmọ orilẹede yii ti n pariwo pe ọjọ ori rẹ ko ni i jẹ ko ṣaṣeyọri nipo. Awọn kan si ti n sọ pe ọrọ wọn ọhun ti wa si imuṣẹ nitori bi Buhari ṣe ti lọ si ilẹ okeere lati gba itọju ni awọn asiko kan. Ki Buhari wa nkan ṣe si itajẹsilẹ O ti pẹ ti ija ẹsin ati ẹ̀yà ti n waye ni orilẹede Naijiria, paapa ni ẹkùn Ariwa. Ṣugbọn awọn kan gbagbọ pe ipaniyan ati ija ẹsin peleke si ni asiko eto iṣakoso Buhari. Awọn daran daran fi ọbẹ ge baba mi lori - ọmọ ọdun mọkanla Ipaniyan wọpọ l'awọn ipinlẹ bi i Kaduna, Plateau ati Benue. Bakan naa ni ẹgbẹ agbesunmọmi Boko Haram naa n ṣọsẹ l'awọn ipinlẹ kan. Ọpọ gbagbọ pe Buhari kọ lati koju awọn Fulani ti awọ̀n eeyan n fi ẹsun ipaniyan jakejado Naijiria kan, nitori pe o jẹ ẹ̀yà kan naa pẹlu wọn. Buhari, dakun mu adinku ba owo epo bẹtiro Awọn kan n fẹ ki Aarẹ Buhari din iye ti wọ̀n n ta jaala epo bẹtiro ku. Ọdun 2016 ni ijọba Buhari kede alekun owo epo, to si yi i pada kuro ni naira mẹtadinlaadọrun to wa tẹlẹ si naira marundinlaadọjọ. Alaye ti minisita keji fun ọ̀rọ̀ epo rọ̀bi, Ibe Kachikwu, ṣe nipe ijọba gbe igbesẹ naa lati fopin si ọwọn gogo epo bẹtiro to maa n waye. Ọwọn epo bẹtiro wọpọ ni orilẹede Naijiria, eyi si maa n waye latari ẹkunwo epo tabi ikunsinu latọdọ awọn oṣiṣẹ elepo rọ̀bì Owo epo to le si ni awọn kan gbagbọ pe o n mu inira ba awọn to n gbe ni orilẹede Naijiria, nitori bi owo ounjẹ, ile, owo ọkọ, ati awọn nkan mi i ṣe lewo si. Ijọba buhari kun fun iwa ijẹkujẹ Awọn kan gbagbọ pe Aarẹ Buhari kuna ninu ẹ̀jẹ́ to jẹ lasiko ipolongo ibo pe iṣejọba oun yoo gbogun ti iwa ibajẹ ni Naijiria, ti oun yoo si fi ofin fiyajẹ awọn to ti ko owo ilu jẹ. Lootọ ni ọwọ ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ ni Naijiria, EFCC, ti tẹ awọn oloṣelu kan to hu iwa ibajẹ, ṣugbọn awọn kan n koro oju si Buhari pe awọn ọmọ 'to jẹ ọ̀tá iṣakoso rẹ' nikan lo n fi igbesẹ rẹ gbogun ti. Ẹgbẹ oṣelu alatako gboogi, Peoples Democratic Party, PDP, tilẹ n sọ pe awọn ọmọ ẹgbẹ́ awọn nikan ni Buhari doju ogun kọ, ti ko si gbe igbesẹ kan naa si ẹsun ti wọn fi kan awọn ọmọ ẹgbẹ́ All Progressives Congress to jẹ ti ẹ. Ni ipari, ọ̀kan lara awọn olukopa, Mercy Mercy, n fẹ ki Buhari fi opin si eto isinru ilu, NYSC. O gba a nimọran pe ki ijọba maa ko owo to yẹ ki ọ̀dọ́ kọọkan o gba ninu eto isinru ilu fun un to ba ti n kẹkọ jade nileewe giga. Awọn agunbanirọ padanu ẹmi wọn lasiko awọ̀n eto idibo kan to ti waye ni Naijiria, ati ninu awọn iṣẹlẹ mi i. O ni wọn yoo le lo o lati fi da iṣẹ́ silẹ fun ara wọn, lati le koju iṣoro airi iṣẹ́ ṣe. Igba akọkọ kọ niyii ti ipe lọ si ọ̀dọ̀ ijọba lati f'opin si eto isinru ilu, paapa nitori bi awọn agunbanirọ sẹ maa n padanu ẹmi wọn nibi ti wọn ti n sinru ilu. Awọn agunbanirọ padanu ẹmi wọn lasiko awọ̀n eto idibo kan to ti waye ni Naijiria, ati ninu awọn iṣẹlẹ mi i.",0,yoruba "Eḳọ tí a ní nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìṣẹ́ ọ̀pọ́lọ̀.",0,yoruba "ìwájú. Ọba lo ni ìgbà mi owó àkokò, Alàji lo tun se lọ.",0,yoruba asin. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó ga.,0,yoruba "fè se, Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba "Ọ̀gá fi ọgbọ́n àrékérekè ọwọ́ wọn ba ti wa jẹ́, àmọ́ kò yé ọ̀pọ̀lọpọ̀ wa bẹ́ẹ̀ ẹni ire la pè wọ́n, ẹni ègbé ẹni ẹ̀tàn ni wọ́n. #Yoruba",0,yoruba iṣu apépe òpàràgà ìyàwókòlọ́rùn efùrù lákọ lóbí lọ bẹẹrẹ bí ọmú ajá kí là ń pàwọn ẹ̀yà ara iṣu,0,yoruba "Aworan to ṣafihan awọn ẹlẹsin meji to jijọ duro sara ọkọ ni awn ọmọ Naijiria n sọrọ lori rẹ loju opo ayelujara. Ṣugbọn kii ṣe gbogbo eeyan naa lo mọ pato nkan to waye ti Venerable ijọ Kristẹni kan ati Imaamu ilu Ijọmu Oro ni ipinlẹ Kwara ti ṣe n dọwẹkẹ lori ọkọ ti Imaamu ra. BBC Yoruba tẹsiwajulati t pinpin nkan tiowaye nibẹ la si ti ri aridaju pe lootọ ni Imaamu gbe ọkọ tuintun to ṣẹṣẹ ra lọ sọdọ alagba ijọ Kristẹni pe ko ṣadura si. Iṣẹlẹ yi ti mu ki ọpọ ọmọ Naijiria maa kan saara si awọn mejeeji pe iru awokọṣe to yẹ re lasiko yi ti ija ẹlẹsinmẹsin ati ẹlẹyamẹya gbode ni Naijiria Orukọ Venerable ti ọrọ yi kan ni Ebenezer Oyeleye Oyedalu ti wọn si jẹ oludari ijọ Christ Anglican Church,ni Ijọmu Oro . Gẹgẹ bi alaye ti o ṣe fun BBC Yoruba o loun kii ṣe ọmọ Ilu Ijomu Oro ṣugbọn lati igba ti iṣẹ Ọlorun ti dari rẹ wa si ilu naa ni irẹpọ ti wa laarin oun ati Imaamu ilu naa. ''Laarọ ọjọ Isinmi to kọja ni nkan bi ago mẹjọ ni mo kọja lẹgbẹ mọsalasi. O jẹ igab akọkọ ti emi ati Imaamu yoo ri ara wa lẹyin ti wọn ti ṣe ọdun tan. O beere pe akoko wo laa pari ijọsin mo si ṣalaye fun. Amọ o ni nkan bi ago mẹwaa loun le wa yọju si mi. Mo ni ko buru'' ''Sadede ni a n ṣe ijọsin lọwọ ni nkan bi ago mẹwaa owuro to si gbe ọkọ wa bawa ni ile ijọsin.Nigba ti mo jade si , o ni oun ṣẹṣẹ ra ọkan naa ni oun si fẹ ki n gbaura si.Inu mi dun, mo si gbaura pe ẹmi rẹ ni yoo lo ọkọ naa.'' ''Ibẹ la wa tawọn ọdọ ijọ ti jade ti wọn si ya aworan .Mi o mọ pe awọn eeyan tiẹ ti ri aworan naa loju ayelujara.'' Orukọ Imaamu ti o wa ninu aworan taa n wi yi ni Imaam Ibrahim Bashir Adewara oun si ni Imaamu agba ilu Ijomu Oro. Ninu alaye ree, o ni ohun ti oun ṣe nipa fifi ọkọ naa han Venerable pe ko ṣe adura si kii ṣe nkan to jẹ tuntun nitori awọn ko ṣẹṣẹ maa ba ara wọn ṣe. ''Ki n to ra ọkọ naa ni Venerable ati awọn olori ẹlẹsin mii to jẹ musulumi ati Kristẹni ti n fi adura ran mi lọwọ pe ki Ọlọrun pese ọkọ fun mi.'' ''Nigba ti mo si ti wa ra ọkọ naa tan, ṣe ko yẹ ki gbogbo wọn ṣadura si ni?'' Imam Adewara sọ pe ibaṣepọ alaafria lo wa laarin awọn ẹlẹsin gbogbo ni Ilu Ijomu Oro ati pe bẹẹ lawọn ṣ n ṣe ni gbogbo Oke Mesan Oro patapata. O fi kun ọrọ rẹ pe ohun ti ẹsin kọ oun ni pe ki oun ṣe daada si alabagbe oun ko si si iyasotọ laarin Kristẹni ati musulumi ninu alabagbepọ. Lafikun ọrọ rẹ, o ni eleyi to dara ju ni pe ki awọn olori ẹlẹsin fi apẹrẹ daada lelẹ fun awọn to n tẹle wọn ati pe ''awọn oloṣelu lo de ti wọn mu iyapa wa laarin gbogbo wa. Ninu ilu wa,musulumi ati Kristẹni ọkan naa ni gbogbo wa.''",0,yoruba "Àìmọ́ ni ó pa Ọba lo ìgbà ọkọ. ọsẹ àlùfáà. Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Ìdánwò egbògi ní Ilẹ̀ - Adúláwọ̀ — tí ó sábà máa ń wáyé lábẹ́ ẹ̀tàn “ ìfẹ́ẹ gbogboògbò """""""" tí ó pọn dandan ní ojúnà àti wá ìwòsàn fún àrùn aṣekúpani bí i àrùn yírùnyírùn àti àrùn kògbóògùn HIV / AIDS — ti lu agogo ìtanijí ìwà - ọmọlúwàbí fún àìníye ọdún — pàápàá jù lọ lórí ìgbàṣẹ",0,yoruba "@user @user @user @user @user. Bi a se wo osu kejila osu naa ko ni ko wa meru lo, Alubarika ni tiwa",0,yoruba òní. ti Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ àti ìbi tí wọn wà.,0,yoruba "Agbẹnusọ fún Ẹ̀ka Ìjọba tí ó ń ṣe àbójútó ètò ìforúkọsílẹ̀ , Valdemar José , sọ fún àwọn akọ̀ròyìn ìbílẹ̀ Angola pé ìdíyelé fún ìwé ìrìnnà ìwọ̀lú lásán - làsàn lọ sí òkè nítorí owó gegere ni ó ń jẹ láti ṣe ìwé náà :",0,yoruba ojumo ire ooo,0,yoruba "Kí ó tó di ìgbà ogun amúnisìn, àwọn Yorùbá ò rí ara wọn gẹ́gẹ́ bí YORÙBÁ KAN. Orúkọ ìlú kálukú ni wọ́n fi ń pe ara wọn. Bíi: àwọn ará Ẹ̀gbá, Ìjẹ̀bú, Ọ̀yọ́, Ìbàdàn, Ìjẹ̀sà, Adó Èkìtì, Ìlàjẹ, Òsogbo, Ẹdẹ, Ìlọrin, Ògbómọ̀ṣọ́ abbl",0,yoruba Títóbilolúwa Great is the lord. https://t.co/bPWm2KBZLC,0,yoruba Èyí ni òun tí a ní láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó wáyé.,0,yoruba "RT @user: Imoran f'eni to ba wole: Ti o ba joba tan, ma f'ade hu ibi, enikan ti waja ki o to kan e. O kan e tan, ranti pe Aderopo mbo…",0,yoruba "Nígbà tí Ọba fè mú, Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé.. Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba "Eeyan mẹtadinlogun lo jona raurau ninu ijamba ọkọ ero to ṣẹlẹ lopopona Bode-Saadu si ilu Jebba nipinlẹ Kwara lọjọ Abamẹta. Awakọ ero Toyota naa ni a gbọ pe ko le dari ọkọ ọkọ naa mọ lẹyin to ti gbiyanju lati ya ọkọ akẹru to ko ata ati ọkọ ajagbe kan to wa niwaju rẹ. Eleyi lo jẹ ki ọkọ bọọsi Toyota naa lọ fori sọ ọkọ ajagbe mii to n bọ lati ọna Jebba, lẹyin naa ni ina sọ! Loju ẹsẹ naa ni eeyan mẹtadinlogun gbẹmi mi nibi ijamba ọhun ṣugbọn ori ko ẹnikan yọ nibẹ lai farapa rara. Agbẹnusọ ileeṣẹ panapana ipinlẹ Kwara, Ọgbẹni Hassan hakeem Adekunle lo fidi iṣẹlẹ ọhun mulẹ ninu atẹjade kan to ṣọwọ sawọn akọroyin. Ọgbẹni Adekunle gbadura pe ki Eleduwa tu awọn ẹbi awọn eeyan to padanu ẹmi wọn ninu. Ọga agba ileeṣẹ panpana ipinlẹ Kwara, CFO Falade Olumuyiwa John rọ awọn awakọ lati maa tẹẹ jẹjẹ nitori ẹmi o laarọ.",0,yoruba @user @user @user Ìlú Gẹ̀ẹ́sì / Ìlú ọba. Nítorípé àwọn ni wọ́n múwa sìn. Kòsí ìjìnlẹ̀ Yorùbá fún diamond.,0,yoruba "Láti ọdún - un 2011 , Boko Haram , ajìjàǹgbara ẹ̀sìn Ìmàle ní Ìlà - oòrùn àréwá orílẹ̀ - èdèe Nàìjíríà , ti fi ẹ̀rù sí ọkàn àwọn ènìyàn àti bí àwọn ìkọlù tó rorò wọ́n ti ṣe fa ikú láì rò tẹ́lẹ̀ ìpí àwọn ènìyàn , tí ọ̀pọ̀ọ́ sì ti di àwátì .",0,yoruba àwọn èrò àti àsà tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ẹkọ́: ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó wáyé..,0,yoruba "Lara ohun ti iwadii naa fi han bayi ni pe dokita yi fun iyawo rẹ lọrun pa ni. A tun gbọ pe Ben Okigbo gbiyanju lati pa awọn ọmọ rẹ ẹni ọdun mọkanlelogun ṣaaju ki o to pokun so. 'Ọ̀lọ́pàá shátà mi láti Mowe dé Magboro dé Shagamu, wọ́n ní ṣé mi ò mọ̀ pé ìjọ́ba ni mo ṣiṣẹ́ fún' Ninu atẹjade ti ileeṣẹ ọlọpaa Sugar Land gbe jade, wọn ni awọn ọmọ rẹ mori bọ ti wọn ko si fara pa rara. ''A n tọ pinpin iṣẹlẹ yi gẹgẹ bi iṣekupani ati igbẹmi ara ẹni'' ni ohun ti awọn ọlọpaa sọ. Ajọ to n mojuto ọrọ awọn ọmọ Naijiria nilẹ okere ṣapejuwe iku dokita yi ati iyawo rẹ to fi Houston ṣe ibujogbe gẹgẹ bi ''ohun to fọwọ kan ni lẹmi.'' 'Pásítọ̀ ló sọ fún mi pé Ọlọ́run pè mí láti di Olokun tó ń bọ omi' Ninu atẹjade, alaga ajọ yi, sọ pe awọn n ba awọn mọlẹbi kẹdun iku wọn paapa julọ awọn ọmọ wọn. NIDCOM sọ pe awọn yoo maa fọkan tẹle iwadii ọlọpaa bo ba ṣe n lọ. Kini ohun taa mọ nipa iku dokita to pa ara rẹ ati iyawo rẹ yi? Nkan bi ago mẹwa owurọ kọja iṣẹju marun un lawọn eeyan ri oku Dokita Ben ati iyawo rẹ ni adugbo wọn Greatwood Subdivision, Brookstone Lane. Ileeṣẹ iroyin News Agency of Nigeria lo jabọ bayi. ""Ọkan ninu awọn ọmọ wọn lo pe ọlọpaa lori ago 911 nigba to fura si pe ija n waye laarin awọn obi rẹ. Nigba tawọn agbofinro yoo fi de wọn ba awọn oku wn ninu ile''. ""O jọ bi iṣekupani ati igbẹmi araẹni ṣugbọn a ko tii ri aridaju'' ni ohun ti ileeṣẹ ọlọpaa Sugar Land sọ. Ninu ọrọ kan to wa loju opo Facebook, ile ijọsin Episcopal Church of Epiphany ni Houston sọ pe''Ẹyin ọrẹ wa, ohun to n banin ninujẹ lọdun 2020 ṣebi ẹni pọ si'' ""ohun ibanuj lo jẹ lati fi to yin leti pe Ben ati Theresa Okigboku laarọ yi nile wọn to wa ni Sugar Land [Texas].'' O fi kun pe ""Iroyin yi bawa lọkan jẹ paapa awa mọlẹbi Epiphany to fi mọ awọn eeyan wa lati Naijiria to ṣe pe Ben ati Theresa lapa ni igbesi aye wọn'' Ileeṣẹ ọlọpaa Sugar Land sọ pe awọn ṣi n ṣe iwadii lori ọrọ naa.",0,yoruba "igba mi owó àkokò, Ọba lo ojú odò.",0,yoruba Ẹ kú ọjọ́ Ẹtì Rere o. Mo gbà á láàdúrà pé gbogbo ohun burúkú ayée wa yóò di rere. #GoodFriday #OjoEtiRere,0,yoruba asin. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ẹkọ́: ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ìyá lo tun se fi.,0,yoruba "Musiliu Haruna Ishola: Ọmọ gbajúgbajà olórin Haruna Ishola mú BBC rìnrìnàjó sínú ìtàn ayé rẹ̀, ìbáṣepọ̀ òun àti bàbá rẹ̀",0,yoruba Ẹ KÚ ÀÁRỌ̀ O... 😍 AÀ JÍIRE BÍ? 🤷‍♀️ ÈDÙMÀRÈ Á PA ÀLỌ ÀTI ÀBỌ̀ YÍN MỌ́ LỌ́SẸ̀ YÍ. ỌWỌ́ YÍN Ò NÍÍ KAN ÌSÀLẸ̀ ÀPÒ. TÁBÌLÌ YÍN YÓÒ KÚN ÀKÚNWỌ́SÍLẸ̀! 🙏 #yoruba #iwure #adura #ojumoire #oseaseyori #owurolojo #ojoaje #osuagemo #omooodua #kaarọoojiire https://t.co/0HVjFUg2Gr,0,yoruba ọ̀gbọ́n. Ọba lo ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba mo ti ṣe bẹ́ẹ̀ bayìí o alàgbà ó wá ku kí ọlá sún kan èmi náà o,0,yoruba àsa. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba Kagara abduction: Lai Mohammed ní ìjọba ò sanwó fáwọn ajínigbé láti fi àwọn akẹ́kọ̀ọ́ iléèwé Kagara sílẹ̀,0,yoruba ní wúlò. ti o nuni ti o pataki.,0,yoruba ìrísí àti ìlànà tí a fi gbọ́ àwọn àkàrà ìbílẹ̀ wọ̀nyí la fi sọ wọ́n lórúkọ,0,yoruba "Baàlè ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba Àbẹ́òkúta. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa òkè: ti o dara.,0,yoruba "Oṣere Ilẹ Gẹẹsi naa ni o di ilumọọka nitori ipa to ko ninu fiimu James Bond to si kaakiri agbaye nitori ipa akọni to ko ninu ere naa. Awọn ẹbi rẹ ni o sun ni ko ji mọ ni ile rẹ to wa ni Bahamas. Amọ iroyin kan gbe e pe o ti n saarẹ fun igba diẹ sẹyin. Ọpọlọpọ ọdun lo ti fi kopa ninu awọn fiimu to lamilaaka, to si ti gba ami ẹyẹ Oscar, ami ẹyẹ Bafta lẹẹmeji ati Ami ẹyẹ Golden Globe ni ẹẹmẹta. Lara awọn fiimu to ti kopa ninu rẹ ni ""Diamonds are Forever,"" ''Hunter for red'' , ''October'', ''Indiana Jones'' , ''Last Crusader'' ati ''Rock''. Titit di oni ni awọn eniyan ṣi n ri gẹgẹ bi oṣere to datọ julọ lati se bii oṣere 007. Ni ọdun 1988 ni o gba ami ẹyẹ Oscar gẹgẹ bi oṣere to jẹ oluranlọwọ pataki ninu fiimu '' The Untouchables'', to si se bi ọlọpaa ile Ireland nibẹ. Ọdun 2000 ni Ọbabinrin Ilẹ Gẹẹsi fun un ni Ami Ẹ̀yẹ ''Knight'' ti aafin Holyrood Palace. Oṣu Kẹjọ, ọdun 2020 yii ni Sean Connery ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi ẹni aadọrun ọdun lori ilẹ aye ko to di wi pe o di oloogbe.",0,yoruba "àlùfáà. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "ìdílé. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.",0,yoruba iyalẹnu wey ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Bàbá lo ojú odò.,0,yoruba "ẹ̀ká ojú. Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "8. Kí ni orúkọ ẹyẹ yìí tó kúndùn láti máa jẹ ata ní èdè Yorùbá? Fún olobó, ẹyẹ yìí ni wọ́n máa ń perí bí wọ́n bá ní 'ó ń rẹ́rìn-ín bí ____'. #Ibeere #Yoruba https://t.co/H0mMFWJbNZ",0,yoruba "tó kún jú, àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó ṣe pàtàkì.",0,yoruba ejo se afise ni asofin iwa jagidijagon o boju mu,0,yoruba Mo fẹ́ràn bí àwọn ilé ṣe máa ń gún régé ní ìlú yìí. http://t.co/w4XVKaCF,0,yoruba "lálai. Nitori eyi, ara eni lo ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba Túwíìtì tàn kárí ilé kárí oko tí ó sọ pé àwọn ọmọ Yorùbá ń tiná bọ ìsọ̀ àwọn oníṣòwò tí ó jẹ́ ẹ̀yà Igbo ní Èkó .,0,yoruba Ara eni lo ni ọ̀gbọ́n. Ìyá lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba "RT @user: @user 🇳🇬🇨🇫🌍Ashura ni iṣọtẹ ti olododo ati ominira pẹlu nọmba kekere, igbagbọ ati ifẹ nla si awọn alade aafin ati aw…",0,yoruba nìkan. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa òkè: ti o nuni ti o ní wúlò.,0,yoruba lojiji. Ọba lo ni ẹ̀ká àwẹ eyti o gbe lori iwa rere.,0,yoruba bí ìṣẹ̀ṣe ṣe dá lórí ìmọ̀ oṣù ìràwọ̀ àti oòrùn náà ni islam dá lé orí ìsàkíyèsí ìwọ̀ ìlà oòrùn àti òṣùpá,0,yoruba "'Ìkọlù darandaran pa èèyàn 2000' Ajọ naa ti orukọ wọn n jẹ ""The Coalition on Conflict Resolution and Human Rights in Nigeria"" ninu atejade kan to jade ni Ọjọ Ajẹ, sọ wi pe ọgọọrọ lọ si ti di alairile gbe ni tori isẹlẹ naa. Gẹgẹbi ọrọ ajọ naa, iye eniyan to ku naa ni wọn fi lede lẹyin iwadii lori iye ẹmi to ti sọnu, dukia, ile ati ọna to ti bajẹ nitori aigbọraeniye laarin awọn agbẹ ati darandaran lẹkun gbungun ariwa orilẹede Naijiria to fi mọ Benue, Taraba, Plateau, Kogi ati ipinle Nasarawa. Opo eniyan ku ninu ikolu fulani darandaran nipinle Benue Wọn fikun wipe awọn ọlọsa naa tun kopa ninu isẹlẹ naa, nipa kiko ohun ini awọn eniyan ti ọfọ ba see. Ti a ko ba gbagbe, awọn ile isẹ ologun Naijiria ti ran ikọ wọn lọ si agbeegbe naa lati da wọ isẹlẹ naa duro, sugbọn ikọlu si n waye lawọn igberiko kookan lagbeegbe naa. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:",0,yoruba Ohun ìtìjú !,0,yoruba "iṣẹ́ aláwọ̀. Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba "ṣe àwọn iṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Àwọn asòfin ilẹ̀ Italy ti dìbò láti gé iye àwọn asòfin lórílẹ̀èdè náà láti lè pèsè owó fún ìsèjọba orílẹ̀èdè náà. Ile asofin kekere buwọlu ofin to ni ki wọn ge iye awọn asofin lati Ojilelẹgbẹta o din mẹwa si irinwo, ti awọn asofin agba naa yoo si dinku lati okoolelọọdunrun o din marun si igba eniyan. Igbesẹ yii wa lara ileri ibo ti ẹgbẹ oselu Five Star Movement, to je ijọba to wa ni ipo se fun awọn araalu lasiko ipolongo ibo rẹ. Awọn asofin naa ni adinku to ba iye awọn asofin lorilẹede naa yoo jẹ ki orilẹede Italy ni ọgọọrọ miliọnu Euro nipamọ lati ara owo osu ati owona. Amọ, awọn alariwisi ọrọ naa ni igbese yii yoo mu ifasẹyin ba isejọba tiwantiwa lorilẹede naa. Bakan naa ni ofin tuntun naa ko le e wa si imusẹ a fi ti wọn ba se idibo gbogbo-gboo nitori yoo mu ayipada ba ofin orilẹede naa.",0,yoruba @user♠ Ẹ kú orí ire #NigerianBlogAwards #BestNewsBlog,0,yoruba ìṣẹ́ tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ẹkọ́: ti o nuni ti o ṣe pataki.,0,yoruba ALGON Oyo: Àwọn alága káńṣù APC fẹ́ kí ẹjọ́ ọ̀hún tẹ̀síwájú,0,yoruba lo fi. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba Ó ti ṣe àwárí ìjápọ̀ nínú ìlú ( láti ìtakò sí ibi ìṣẹ̀ṣe ) # NiboniLuisCarlosWa .,0,yoruba Telegram naa ní ègé olóótọ fún àwọn ìkòkò tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa àwọn ènìyàn: ti o.,0,yoruba Rumuekpe Port Harcout explosion: Èèyàn 25 jóná níbi ọ̀pá epo tó fọ́,0,yoruba Arée pànpàlà bí o ò lọ ó yàgò tí ń ṣẹlẹ̀ láàárín àwọn onímọ̀ ìjìnlẹ̀ àti oníṣẹ́ ìwádìí kò ṣẹ̀yìn ìgbésẹ̀ láti ṣe àyẹ̀wò àwọn oògùn tí wọ́n rò pé ó lè wo àrùn COVID - 19 sàn lára ọmọ ènìyàn ti ń dá gbọ́nmisíi - omi - ò - tóo sílẹ̀ ní Ilẹ̀ - Adúláwọ̀ .,0,yoruba "Sisí Yétúndé, mọ gbà fún-un yín o @user",0,yoruba "ìbàdandun ìlú. Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba """Kò yẹ kí ọ̀rọ̀ ẹnu rẹ̀ dá. kò yẹ kó lè rìn, ó yẹ kí ẹnu rẹ̀ wọ́ koda ""fẹgbẹ wọ ọ"" ni wọn o ba maa pe e àmọ́ iyalẹnu ni ifọrọwanilẹwo waq pẹlu Anifat jẹ.\n\nArun Hemiplegia Cerebral Palsy lo n baa finra leyi to jẹ pe lati kekere ni nkan ti yipada fun un ni gba to wa ni nkan bii ọmọ ọdun mẹta ti aisan iba yọju. ""Mama mi sare gbe mi digba digba lọ sileewosan, awọn nọọsi bẹrẹ iṣẹ amọ ṣaadede ni mi o le rin mọ. Iya mi tilẹ gbagbọ pe iru abẹrẹ ti nọọsi fun mi lo sọ mi di da bi mo ṣe da"".\n\nAnifat Sadu ni Hemiplegia lo kọkọ bẹrẹ, igba to to bii ọmọ ọdun mẹsan, o ni ohun tun ni Scoliosis eyi to yẹ ko sọọ di ẹni ti egungun rẹ wọ, ki ara maa dun un ki iṣan maa dun o si ṣe apẹrẹ nkan ti gbajugbaja elere ori ọdan, Usaine Bolt n la kọja tori aisan Scoliosis yii. ""Ti wọn ba n ṣe ere idaraya, wọn a ni ki n lọ joko si ẹgbẹ kan, ti mo ba n rin loju titi, awọn eyan a maa doju bo mi, mo maa sunkun gidi pẹlu ibanujẹ ọkan"". \nAnifat ní ""àwọn ẹlẹ́gbẹ́ mi máa ń fi mi ṣe yẹ̀yẹ́ bí ọwọ mi bá ń gbọ̀n àti bí mo ṣe ń rìn ní School"".\nAnifat sọ ipenija to tun koju gaan ni Fasiti to ti kawe gboye.",0,yoruba owo ṣẹlẹ ni Ibadan ti gbogbo eniyan sọ o ṣe pataki. (2026),0,yoruba dindinrin ni jonathan pe awon ara nijeria olohun din owo epo ku nigba ti ori wipe ti gba ijboba tan omugo le pe wa,0,yoruba ẹkọ́ ṣẹlẹ ni Eko ti gbogbo eniyan sọ o dara. (1996),0,yoruba "Lọsẹ yii, aya Adeyemo ni yoo maa kọ wa lẹkọọ nipa Isọri ọrọ ninu gbolohun Yoruba ati itumọ rẹ. Bakan naa ni yoo sọ fun wa orisi isọri ọrọ to wa, ba se n lo wọn ati anfaani wọn. Ẹ wa kọ ẹkọ pupọ nipa asa ati ede wa, ko maa baa parun.",0,yoruba ẹ jẹ́ á kíyèsíi kí a tètè tọ onímọ̀ ìlera lọ bí a bá ríi pé ikọ́ ń yọ wá lẹ́nu ó sì ti ń ṣe lemọ́ lemọ́ jù,0,yoruba "joko, Nitori eyi, ara eni lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.",0,yoruba agba a yi fi ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Bàbá lo ìgbà ọkọ.,0,yoruba "àìlẹ̀, Olùwo ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..",0,yoruba "Imado iba se bi elede aba'lu je, eru iba je oba eeyan o ni ku kan. #yorubaProverb #TweetinYoruba",0,yoruba ojú òní. ti Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbfi yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba "Sasa crisis in Ibadan: Ìbànújẹ́ ńlá ni ìṣẹ̀lẹ̀ Sasa jẹ́ fún mi - Makinde Ìbànújẹ́ ńlá ni ìṣẹ̀lẹ̀ Sasa jẹ́ fún mi ni koko ọrọ ti gomina Makinde ba awọn eeyan sọ. Gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde ti sọ pe gbogbo awọ to lọwọ ninu rogbodiyan to waye lọja Sasa nipinlẹ naa ni yoo foju wina ofin laipẹ. Makinde lo kede bẹẹ ninu fọran kan to fi lede loju opo Twitter rẹ, eyii to fi ba awọn eeyan ipinlẹ naa sọrọ. O ni ""mo ti paṣẹ pe ki wọn bẹrẹ iwadii lori ohun to fa ṣababi rogbodiyan naa, eyii to mu ẹmi awọn kan lọ."" Gomina ọhun sọ pe ""mo ṣabẹwo si ọja Sasa ati Ojo ni ijọba ibilẹ Akinyele, mo si ri awọn ti ọrọ naa kan, o jẹ ohun to ba mi ninu jẹ gidi pe awọn eeyan kan ba iṣẹlẹ naa lọ."" ""Ṣugbọn mo fẹ fi da yin loju pe, gbogbo ohun to yẹ ni a maa ṣe lori iṣẹlẹ naa, mo ti gbe iwadii dide lati mọ ohun to fa iṣẹlẹ naa, mo ṣi ṣeleri fun yin pe gbogbo awọn to lọwọ ninu rogbodoyan ọhun ni yoo foju wina ofin."" Makinde tẹsiwaju pe ijọba ohun yoo ṣe iranlọwọ fun gbogbo awọn to faragba ninu iṣẹlẹ ọhun. Ondo Fulani Herdsmen: Àgbe mẹ́ta ní àwọn Fulani darandaran tún pa Ọ̀wọ̀, Ondo Bakan naa lo kilọ fun gbogbo awọn to n dana ogun ẹlẹyemẹya nipinlẹ Oyo lati ṣora ṣe. Lẹyin naa lo dupẹ lọwọ gbogbo awọn oṣiṣẹ eto abo fun akitiyan wọn lati mu ki alaafia jọba nipinlẹ naa. A san owó f'áwọn sọ́jà tó dóòlà ẹ̀mí wa ní Sasa ká tó sá àsálà- Oníṣòwò Hausa Lati opin ọsẹ to kọja yii ni ija ti bẹ sile laarin awọn Yoruba ati Hausa ni ọja ata ti wọn n pe ni Sasa ni ilu Ibadan ni eyi to si ti bi iroyin lorisiirisi. Akọwe ẹgbẹ awọn oniṣowo ni Sasa, ti wọn pe ni Sasa Traders Association, Ilyas Bala Muhammed ba BC sọrọ ni kikun lori iṣẹlẹ naa. Iliyas ni pe ọpẹlọpẹ awọn ọmọ ogun ilẹ Naijiria ti wọn ni wọn gba owo lọwọ awọn lo ba awọn yanju eto aabowọn lati ribi salọ. Iroyin ti gbogbo ero ọja sọ nipe awọn ṣọja pese iranlọwọ fun awọn oniṣowo Hausa lati ribi sa lọ ṣugbọn a ko le fidi ẹ mulẹ boya tootọ ni wọn gba owo naa tabi bẹẹ kọ. Ki lo ṣẹlẹ ni Sasa gangan lọjọbọ to kọja? Akọwe ẹgbẹ oniṣowo Hausa ni Sasa, Iliyas ṣalaye fun BBC pe lootọ ni ọkunrin ọmọ Yoruba kan doloogbe ni ọja naa lọjọbọ. O ni eyi waye lataari ede aiyede laarin ọmọ Yoruba kan ati ọmọ Hausa kan. O ni iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ laari alaboyun ọmọ yoruba kan ati alagbase omọ Hausa kan ni eyi ti ọkunirn yoruba kan da si ọrọ naa pe ọrọ pẹlẹ ni ọrọ awọn alaboyun. Ni eyi ti alagbaṣe ọmọ Hausa naa si di ija laarin awọn ọkunrin mejeeji. Iliyas ni pe irọ ni pe ọmọ Hausa naa na ọmọ Yoruba ọhun loogun to fi ku. Akọwe awọn Hausa oniṣowo naa ni tootọ ni ọkunrin Yoruba naa gbe ẹmi mi lẹyin o rẹyin lẹyin ti wọn gbe e lọ sile iwosan fun itọju. Bala Muhammed bu ẹnu atẹ lu awọn agbofinro ati awọn oṣiṣẹ eleto aabo pe wọn ko pese aabo to peye nigba ti ọrọ daru tan. O ni niṣe ni awọn eleto aabo n woran laida si iṣẹlẹ naa. Bakan naa ni Bala tun fẹsun kan ijọba pe wọn ko tete dide si iṣẹlẹ naa bi o ti yẹ ni oju tirẹ. Ọpọlọpọ ile, ṣọọbu ati ọja ni wọn dan a sun ninu ọja Sasa. Awọn oniṣowo Yoruba ati ti Hausa naa lo si ti n ka iye adanu ti wọn ṣofo rẹ. Lori iro: Ká ni àwọn Òbí mi gbà fún mí, èmi àti Sunny Ade á jọ máa 'Compete- Baba Lórí ir Kini o n ṣẹlẹ ni Sasa bayii? Bayii ti ikọ BBC de si Sasa ni a ri i pe ohun gbogbo ti wa ni irọwọrọsẹ. Bẹẹ la tun ri awọn oṣiṣẹ eleto aabo pọ nibẹ loni ọjọ Aje ti a kan sibẹ. Gomina Seyi Makinde ti pe fun alaafia o si ti fi ofin konile-o-gbele sibẹ.",0,yoruba yẹ swift wò ọ̀kan nìyẹn,0,yoruba Gbé ààyè-iṣẹ́ fèrèsé kan sí òsì,0,yoruba àìmọ́. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tó gbogbo àwọn.,0,yoruba ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún gbogbo.,0,yoruba @user tanmọdé sóko/tanmọlọóko; tanmọóko; tan ọmọdé lọ sí oko #idahun #yoruba,0,yoruba "àtọ́wọ́dá, àwọn oníṣẹ́ ìṣẹ́ ni a ní nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò.",0,yoruba kakaaki. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò.,0,yoruba "@user ọ̀kín ni Ọlábísí, ọmọ́ dára tán, ẹwà tún ṣubú lù ú 😉",0,yoruba "Epo ní ìwúlò tó pọ̀ jọjọ, lẹ́yìn-in káfi se oúnjẹ nílé ìdáná. Nǹkan tí à ń fi epo ṣe kò l'óǹkà. #Epopupa #Yoruba #Epo",0,yoruba Kíni orúkọ tí à ń pe àbílé Àlàbá? #Ibeere #Yoruba,0,yoruba "Wọ́n fi ìgò òfìfo ráńṣẹ́ padà sí Ọba, láti fi hàn wípé, àwọn fi ìfẹ́ gba ẹ̀bùn rẹ̀. Tìmí Ẹdẹ ráńṣẹ́ sí Àṣegbé láti bèrè wípé, kíni ṣíṣe, kíni àìṣe? Àṣegbé wí pé, kí Ẹdẹ fi àpò owó mẹ́wàá àti ewúrẹ́ mẹ́wàá ráńṣẹ́, kí wọ́n sì gbà láti ju ọwọ́ ogun",0,yoruba mú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gblọ yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba yi kún fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó wáyé..,0,yoruba Àwọn gbàgede,0,yoruba ògúnfúnmitọ́ ogún gives me to raise,0,yoruba ajé ògúngúnnìsọ̀ kó wá bá mi gbélé mo fẹnu pe ìfà ìfà á wọlé tọ́ mi èjì ogbè á bá mi gbére wá àṣẹ wáà,0,yoruba "Atẹjade kan lati aafin ọba naa lo fidi ọrọ yi mulẹ. Ikede iyalẹnu yi jẹyọ pẹlu bi ayẹyẹ iwuye alaragbayida ti wọn yoo ṣe ti ṣe ku ọsẹ kan. Ooni: Mo ti fi ọ̀rọ̀ obinrin tó ń parọ́ ìfẹ́ mọ́ mi sun agbófinró Ọba Maha Vajiralongkorn,ti ṣe ẹni ọdun mẹ́rìndínláàdọ́rindi ba lẹyin ti baba rẹ ti awọn ara ilu fẹran gidi gaan papoda lọdun 2016. O ti kọ iyawo mta silẹ saaju asiko yi ti o si bi ọmọ meje. Gẹgẹ bi atjade naa ti ṣe sọ, o ni ọba Vajiralongkorn "" ti pinu lati mu agbega ba ọgagun Suthida Vajiralongkorn Na Ayudhya, to jẹ ẹni ayo rẹ si ipo olori ti yoo si di ipo yi mu gẹgẹ bi olori laafin'' Oluwo: Mo lè jẹ Ọba ní Ile Ife O ti pẹ ti awọn ara ilu ti mọ olori Suthida gẹgẹ bi wọlewọde Oba bo ti lẹjẹ wi pe wọn ko sọ sita pe awọn n fẹ ara wọn. Ọba Thailand n bu omi si ori aya'ba Suthida Niṣe ni wọn fi fọnran fidio igbeyawo wn han lori ẹrọ amohunmaworan orile-ede Thailand lọjọru nibi ti awọn ori ade ati ilẹkẹ peju sibẹ. Lọdun 2014 ni Ọba Vajiralongkorn yan Suthida Tidjai, to figba kan jẹ oṣiṣẹ ile iṣẹ ọkọ ofurufu si ipo igbakeji olori awọn ẹsọ Ọba. Nigba ti yoo fi di ọdun 2016, o fi oye ọgagun daa lọla. Ọba to jẹ saaju Ọba Vajiralongkorn,Ọba Bhumibol Adulyadej lo àádọ́rin ọdun lori itẹ eyi to mu jẹ Ọba to pe lori oye julọ lagbaye. O waja lọdun 2016.",0,yoruba Àkójú ọ̀rọ̀ yi kún fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde sí ara ilẹ̀. (Item 168),0,yoruba "Ọmọ inú odi, kì í kú sẹ́yìn odi. A ò ní kú láì t'ọ́jọ́. Ẹ kú ìsinmi ọjọ́ Àìkú o!",0,yoruba eyin orekelewa omoge ile kaaro ojire to mo faajie kan si arabinrin lati ra sokoto igbalode ti won pe ni pal,0,yoruba Bed Wetting: Tolulope Joseph ní ò lé ní ogún ọdún tí òun fi tọ̀ sílé kí ìwòsàn tó dé,0,yoruba "lọ. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Nitori eyi, ara eni lo ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba òun tí a kọ eḳọ nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó.,0,yoruba "Ní ọdún yìí ni a sààmì ọgbọ̀n ọdún ohun tí ó fa sábàbí ìpaninípakúpa ọjọ́ 4 oṣù Òkúdù àti láti ṣe ojúṣe wa láti rán àwọn ènìyàn létí , pẹ̀lú gbogbo ọ̀nà àgàbàgebè tí Beijing ń gbà láti fi eérú bo òtítọ́ mọ́lẹ̀ .",0,yoruba "Iroyin kan ni ọjọ aiku pe lo gbalẹ kan pe gbajugbaja olorin Raggae ọmọ Naijiria nni, Majek Fashek ti dagbere faye. Ohun ti iroyin naa, eleyii to ti farahan lori ọpọlọpọ awọn oju opo aiyelujara titi kan Wikipedia ṣalaye pe, Majek Fashek mi eemi ikẹyin rẹ ni ọjọ Aiku ni ilu London, ni orilẹede Gẹẹsi. Amọṣa, ohun ti alamojuto ẹgbẹ oṣere rẹ, Uzoma Omenka sọ ninu fidio kan, eyi to fi sita loju opo instagram Majek Fashek ni pe, ko si nnkan to ṣe Majek o. O ni ko ku, ṣugbọn ara rẹ ko le. Fidio naa eyi to fi sita ni nnkan bii agogo mejila oru ọjọ Aje, Uzoma Omenka ni ko yẹ ki ẹnikẹni maa gbadura iku fun agba onkọrin naa. nigba ti BBC Yoruba kan sii, O ni ohun to nile ni owo iranwọ fun itọju rẹ ati pe ọpọ awọn eeyan lo ti n pe lọtun losi lati igba ti iroyin naa ti jade. ""Majek ko ku o, ojojo diẹ̀ lo kan n ṣe ogun rẹ"" Ti a ba n sọ ninu awọn onkọrin ọmọ orilẹede Naijiria ti gbogbo agbaye mọ bi ẹnii mọ owo, ti orin rẹ si ti gbe ogo ba orilẹede Naijiria ni ọpọlọpọ igba, Majek Fashek jẹ ọkan pataki ninu wọn. Ọdun 1962 ni wọn bi Majek Fashek ni ilu Benin, ni ipinlẹ Edo. Ni aipẹ yii ni iroyin kan kọkọ jade pe arun jẹjẹrẹ mu Majek Fashek ti wọn si n beere iranlọwọ fun un, Iroyin iku rẹ kọkọ ti tan jade ni ọjọ diẹ sẹyin ki alamojuto ẹgbẹ akọrin rẹ, Uzoma Omenka to gbe fidio kan sita pe irọ ni ṣugbọn o fi idi rẹ mulẹ nigba naa pe lootọ ni aisan da agba akọrin naa dubu Amọṣa iroyin naa ṣebi ẹni pe ko dawọ duro. Lara awọn manigbagbe orin ti Majek Fashek gbe jade ni Send down the rain eyi to fun un ni inagijẹ The rainmaker. Awo orin Prisoner of Conscience and I&I Experience(1989),So long too long (1991) Orukọ abisọ rẹ gangan ni Majẹkodunmi Fasheke. Ile iwosan Queen Elizabeth Hospital, Woolwich ni o ti n gba iwosan ni ilu London.lẹ.",0,yoruba "Awọn ọmọ igbimọ iwadii ṣe abẹwọ sawọn ibi ti ikọlu ti waye ni Lekki Yatọ si pe wọn jijọ gba pe wọn yinbọn nibẹ, awọn oluwọde ati agbofinro Naijiria ko fẹnuko lori ohun to ṣẹlẹ ni pato lalẹ ọjọ naa. Ireti ni pe agbekalẹ igbimọ iwadii yoo yanju ọrọ naa paapa eyi to ni ṣe pẹlu iwa ipa lati ọdọ awọn ọlọpaa si araalu. Ṣugbọn ọrọ ko ri bẹẹ titi di bi a ṣe n sọrọ yi. Awọn akọroyin wa to wa ni Eko n jabọ fun wa bi nkan ti ṣe n lọ nibi ijoko igbimọ iwadii ti ijọba gbe kalẹ lati tọ pinpin ọrọ yi. Talo paṣẹ fawọn ọmọogun pe ki wọn lọ si Lekki Toll Gate? Yiyọju awọn ologun ni Toll Gate Lekki lasiko iwọde alalaafia ko dun mọ ọpọ ninu ti wọn si ti n beere pe talo paṣẹ ki wọn lọ sibẹ? ni ibeere nla lasiko yii. Gomina Babajide Sanwo-Olu Eko logunjọ oṣu Kẹwaa paṣẹ konile-o-gbele lati dẹkun ikọlu to n waye lawọn agbegbe kan ni Eko latari iwọde ENDSARS. Saaju asiko yii ti iwọde naa n lọ laisi wahala ni awọn janduku kan gba a sii Gbayawu ni Lekki Toll Gate wa tawọn eeyan si n kọja lai si idiwọ Wakati diẹ lẹyin to paṣẹ yi, awọn ọmọogun de si Lekki Tollgate nibi tawọn oluwọde patẹ si lati bi ọjọ meloo kan sẹyin. Ni idahun si idi ti awọn ologun fi wa nibẹ, Gomina Sanwo-Olu sọ fun ileeṣẹ iroyin Arise TV ni ọjọ Kejilelogun, oṣu Kẹwaa pe oun ko lagbara lati paṣẹ ki awọn ologun lọ si aaye iwọde. Amọ, ileeṣẹ ologun sọ fun igbimọ iwadii lọjọ Kọkanla, oṣu Kọkanla, pe Sanwo-Olu lo pe awọn lati wa sibẹ. Ọgagun Ahmed Taiwo ni Sanwo-Olu funrarẹ lo pe awọn lati wa sibẹ nitori ipa awọn ọlọpaa ko ka ohun to n ṣẹlẹ. Nibi ijoko igbimọ naa omiran to waye lọjọ Kọkanlelogun, oṣu Kọkanla ni aṣoju ologun to wa nibẹ ni iṣẹ ti wọn bẹ awọn kii ṣe lati tu awọn oluwọde ka. Bi ko ṣe pe ki ''awọn da alaafia pada si agbegbe Eti-Osa nibi ti Lekki Toll gate wa'' Gomina Sanwo-Olu ko ti i fesi sọrọ tawọn ologun sọ. Ṣe awọn ologun yinbọn to ni ọta ni tootọ abi bẹẹkọ? Ọpọ ẹsun ni awọn eeyan ti fi kan ọlọpaa ati ologun pe wọn yinbọn ọlọta lu awọn oluwọde. Ajọ ajafẹtọmoniyan Amnesty Internnational sọ pe eeyan mejila lo ku. Nigba ti igbimọ iwadii yoo fi bẹrẹ ijoko ileeṣẹ ologun lawọn ko yinbọn lu ẹnikankan ati pe ọta ti ko loro lawọn yin ni Lekki Toll Gate lu awọn oluwọde. DJ Switch to fi fidio iyinbọn lu oluwọde han ti sa asala fẹmi rẹ kuro ni Naijiria Lọjọ Kokanlelogun, oṣu Kọkanla ni ọgagun Taiwo sọ fun igbimọ naa pe awọn ọmọ ogun gbe ọta to loro ati eyi ti ko ni lọwọ. Wọn ni idi ni pe awọn janduku ti darapọ mọ iwọde naa lati fi da nkan ru. Lasiko ifọrọwanilẹnuwo, aṣoju ologun yi ni awọn janduku sọ oko lu awọn ologun to n kaakiri lagbegbe Oriental Hotel ki eeyan to de Lekki Toll Gate. Ọmọoogun kan,gẹgẹ bi o ti ṣe wi, farapa. O ni: ''Ki a to de Oriental Hotel ni wọn ti n sọ oko lu awọn ọmọogun ti wọn si fi ọta ti ko loro dawọn lohun pada. Wọn ṣe ọmọogun kan leṣe, Okuta ba a ni ete rẹ. Ti wọn ba sọ oko luwa, ohun ti a le fi da wọn lohun pada ni ọta ibọn ti ko loro.'' Ki lohun ti BBC jabọ? Lọpọ ijoko igbimọ ati lawọn igba mii ti wọn ba awọn akọroyin sọrọ, ileeṣẹ ologun n sọ pe BBC jẹri si i pe awọn yinbọn soke ni ati pe awọn ko yinbọn lu awọn oluwọde. Akọroyin BBC Pidgin, Damilola Banjo ninu iroyin to fi sọwọ ṣapejuwe ohun ti oju rẹ ri ni Lekki lasiko to wa nibẹ. #EndSARS : Àwọn ọ̀dọ́ dáná sun tírélà akẹ́rù tẹrùtẹrù ní Ekiti Kini Damilola Banjọ sọ? Damilola ni oun kuro nibi ikọlu naa lẹyin nkan bi iṣẹju marundinlọgbọn jabọ pe: ""Ki a to kuro ni Lekki, awọn ologun n yinbọn soke ti a si sa asala fun ẹmi wa. Mo ri arakunrin kan ti ko le e mi daadaa'' "" Mo lero pe ohun to fa eyi ni pe aya rẹ n ja nitori bi awọn ologun ṣe n yinbọn leralera ati pe gbogbo ayika ibẹ ni ko rọgbọ'' ''Wọn tẹ siwaju lati maa yinbọn fun nkan bi ogun iṣẹju ti a si daya delẹ ki awọn eeyan ma ba a tẹwa mọlẹ. Ọga mi ti a jijọ wa nibẹ sunmọ awọn ologun, to si sọ fun wọn pe akọroyin ni wa ki wọn to jẹ ki a jade lalaafia. O to nkan bi ogun si iṣẹju marundinlọgbọn ki a to ribi jade'' Ta lo pa CCTV? Ọrọ miran to tun mu awuyewuye wa ni ti CCTV ti a mọ si kamẹra to ka ohun to waye nibi ikọlu Lekki lalẹ ikọlu naa silẹ. Lasiko to n jẹri niwaju igbimọ ọga ileeṣẹ Lekki Concession Company to n mojuto Toll Gate, Abayomi Omomuwasan, sọ pe kamẹra naa sinmi lati maa ṣiṣẹ ni nkan bi aago mẹjọ alẹ Ninu idahun rẹ si ẹsun pe wọn mọọmọ pa ina lasiko ikọlu naa, ọgbẹni Omomuwasan sọ pe nitori aṣẹ konileogbele ti ijọba gbe kalẹ lawọn fi ni kawọn oṣiṣẹ awọn maa lọ sile. Nitori eyi o ni wọn ko le tan ẹrọ amunawa lẹyin igba ti ina ọba lọ. Eeyan meloo lo ku? Gomina Sanwo-Olu sọ fun CNN ni idahun si ibeere yi pe oku meji lo wa ni ile igbokupamọ si to si ni ki awọn araalu mu ẹri wa tabi ki wọn yọju ti wọn ba padanu mọlẹbi ninu iṣẹlẹ naa. Ṣugbọn ileeṣẹ ologun ni awọn ko pa ẹnikankan ni Lekki Toll Gate. Ọgagun Taiwo sọ fun igbimọ naa pe eeyan kan ku lopopona Admiralty Road ati pe iku rẹ ko waye latari iṣẹlẹ Lekki. O ni awọn ọlọpaa naa gbe oku eeyan kan wa lati adugbo Yaba nilu Eko bakan naa. Oluwarinu Odulala wa lara awọn to n ṣoju ọdọ to si kopa ribiribi ninu iwọde ENDSARS Titi di igba wo ni igbimọ yoo fi joko? Adajọ fẹyinti Doris Okuwobi lo n dari igbimọ yi. Awọn mii to pẹlu rẹ wa lati ajọ ajafẹtọmoniyan, ajọ to n mojuto ẹtọọmoniyan ni Naijiria, Human Rights Commission, Citizens Mediation Centre ati awọn aṣoju ọdọ meji. O ti le ni iwe ifẹhonuhan ọgọrun un le ni mẹwaa ti igbimọ naa ti gba. Ireti wa pe wọn yoo gbọ gbogbo ẹsun yi nisoju awọn agbẹjọro ati awọn olujẹri. Igbimọ ẹlẹni mẹjọ yii bẹrẹ lọjọ Kẹtadinlọgbọn, oṣu Kẹwaa ti wọn yoo si fi oṣu mẹfa ṣe iwadii lati gbẹjọ ifiyajẹniyan lọwọ ọlọpaa lọna aitọ. Bẹẹ naa ni wọn yoo daba ijiya to ba tọ fawọn ọlọpaa to ṣe aṣemaṣẹ pẹlu owo gba ma binu to ba tọ si awọn ti wọn fiya jẹ lọna aitọ.",0,yoruba Boko Haram: CAN àti àwọn ará Chibok ní kò sí orílẹ̀èdè tó yege nínú yíyí ọkàn aṣẹ̀rùbálú padà,0,yoruba "Awọn ikọ Senegal dunnu lẹyin ti wọn na Poland pẹlu ami ayo 2-1 Senegal nikan lorilẹ-ede lati ilẹ Afirika to jawe olubori ninu ifẹsẹwọnsẹ alakọkọ ni isori won, lẹyin ti wọn lu awọn ikọ agbabọọlu to wa lati ilẹ Afirika ni alubami ni isọri wọn. Akọnimọọgba ilẹ Senegal, Aliou Cisse, nikan lo jẹ akọnimọọgba alawọdudu ninu awọn orilẹ-ede mejilelọgbọn to n kopa ninu idije naa. Cisse ninu ọrọ rẹ sọ pe lootọ ni pe oun nikan ni akọnimọọgba to jẹ ọmọ ilẹ Afrika, amọ o wi pe idije erebọọlu wa fun gbogbo agbaye ni ati fun gbogbo eniyan, ti ko si niise pẹlu awọ ara. Ìran ni oúnjẹ ojú ni ọ̀rọ̀ ife ẹ̀yẹ Russia 2018 dì báyìí Iroyin sọ pe awọn akọnimọọgba to jẹ alawọ dudu ṣọwọn ni Idije Ife Ẹyẹ Agbaye, bi o tilẹ jẹ pe wọn fikun awọn orilẹ-ede to n kopa lati orilẹ-ede mẹrinlelogun si mejilelọgbọn. Nínú àwọn orílẹ̀èdè 32 tó ń kópa lọ́wọ́ nínú Ìdíje Ife Agbaye 2018, àkọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ̀ Senegal, Aliou Cisse nìkan ló wà láti Afirika. ‘ Ilẹ Adulawọ fẹran akọnimọọgba lati ilẹ okeere’ Ninu Idije Ife Agbaye ti 1998 ni orilẹ-ede Faranse, ko si akọnimọọgba to jẹ alawọdudu, bi o tilẹ jẹ pe awọn agbabọọlu lati ilẹ Afirika pọ ninu idije naa. Lati igba naa, akọnimọọgba meje nikan lo ti laaye lati kopa ninu Idije Ife Ẹyẹ Agbaye. Bakan naa, ninu Idije Ife Agbaye ti ọdun 2010 to waye ni orilẹ-ede South Africa, ko si akọnimọọgba alawọ dudu kankan. Ninu ọrọ rẹ, akọnimọọgba fun orilẹ-ede Democratic Republic of Congo, Florent Ibenge, sọ fun Ileesẹ Iroyin AFP pe oun to wọpọ n i ilẹ Afirika ni ki wọn maa lo akọniọọgba lati Ilẹ Gẹẹsi ati orilẹ-ede Amẹrika. Sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa ikọ̀ tí yóò gba ife ẹ̀yẹ àgbáyé 2018 pẹ̀lú eré ìdárayá tuntun ti BBC 'Mi ò ní wo bọ́ọ̀lù mọ́ ti Nàìjíríà bá fìdírẹmi ni Russia 2018'",0,yoruba èkó aṣà lo je gbogbo ise ibile tèmi.,0,yoruba "Mú àtòjọ àtòjọ-ètò inú onísọ̀rọ̀gbèsì ""Rọ́ọ̀nù Ìsàmúlò-ètò"" ṣíṣẹ",0,yoruba ewé olówójẹja etípònlà àwọn oníṣègùn á máa lò ó fi ṣe àyẹ̀wò oyún lára obìrin,0,yoruba Ẹ kú àṣálẹ́ o ẹ̀yin tèmi :),0,yoruba nípa ìṣẹ̀: ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó ṣe pàtàkì.,0,yoruba se se. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba da ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba nípa iṣẹ́: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Bàbá lo ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba a fi ọwọ́ ara wa fa aṣọ iyì ara wa ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ ìyẹn aṣọ èyí tó nípọn bí awọ erin a sì sọ ọ́ di fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́,0,yoruba Ọkan tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé.. A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ = slopes slope ó nira láti gun ibi gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ yẹn ️ it is difficult to climb the slopes,0,yoruba "ẹ̀ká ojú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìṣẹ̀: ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Ọkan tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.. Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba kí ẹsẹ̀ ọmọ maríwo ó pé wámúwámú ìpàdé di aago mẹ́sànán ajálẹ́,0,yoruba Ìfẹ̀hónúhàn tí ó wáyé ní gbàgede ìlú wà lára ìkéde gbogboògbò # saveLGBTinRussia tí wọ́n fi ń polongo ìyà tí ó rorò tí wọ́n fi ń jẹ àwọn ènìyàn aṣe - ìbálòpọ̀ - akọ - àti - akọ ní orílẹ̀ Chechnya .,0,yoruba "Eni ti yoo daso fun eni torun re laa ko wo, to difa fun pastor to ra oko baaluu aladani, to wa n wasu pe kawa to isura wa jo si orun :-(",0,yoruba Myth of Witchcraft: Ṣé ìwọ mọ̀ pé Olodumare lè lo Aje láti gbé ẹ lọ síbi ire?- Abiodun Fatomilola,0,yoruba "Ajé o! Mo pé ọ, wá jẹ́mi nípè. Àtà jèrè, wàràwàrà, àpamọ́wọ́ owó ni tèmi tìrẹ. Bẹ́ẹ̀ la á rí",0,yoruba "CAF kéde Asisat Oshoala, Rasheedat Ajibade, Chiamaka Nnadozie lára àwọn agbábọ́ọ̀lu obìnrin fún àmì ẹ̀yẹ 'CAF Awards' tọdún 2022",0,yoruba se. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìṣẹ̀: ti o lẹ.,0,yoruba e patewo fun ra yin e pegede e fi gbooro jeka,0,yoruba Rev Stephen Akinola: Ọmọ bíbí ìlú Igboho níí ṣe àmọ́ tó fi Portharcourt ṣe ibùjókòó,0,yoruba "Àwọn wo ni a máa ń pè ní """"""""""""""""apàlọ́ pa títà?"""""""""""""""" #Ibeere #Yoruba",0,yoruba "Aarẹ Buhari fi eyi lede gba ọwọ oluranlọwọ pataki ninu eto iroyin igbalode, Bahir Ahmad, eleyii to fi si oju opo Twitter. O ni '' Akeredolu ku orire iyansipo gẹgẹbi gomina fun ọdun mẹrin miran lati tukọ ipinlẹ Ondo''. Akeredolu ti ẹgbẹ oṣelu APC la Jedege mọlẹ pẹlu ibo 29,2830, ti Jegede ti ẹgbẹ oṣelu PDP si ni ibo 195,791. ''A kò gbà pé Eyitayo Jegede fìdírẹmi, Àjọ INEC ló ṣe aṣemáṣe'' Awọn ololufẹ ẹgbẹ oṣelu PDP ti ni awọn ko gba wi pe Eyitayo Jegede fidirẹmi, amọ ajọ eleto idibo INEC lo ṣe magomago fun wọn. Eyi ko ṣẹyin bi Ajọ INEC ṣe kede gomina ipinlẹ Ondo, Oluwarotimi Akeredolu gẹgẹ bi ẹni to jawe olubori ninu idibo sipo gomina nipinlẹ Ondo. Bakan naa ni alukoro ẹgbẹ oṣelu nipinlẹ Ondo, ni awọn ṣi n gba alaye lori esi idibo naa lọwọ nitorinaa awọn ko tii le fesi. ''Eyitayo Jegede naa ko i tii ṣetan lati sọrọ lori esi idibo naa, ti asiko ba to, yoo sọrọ'' Ololufẹ Eyitayọ Jegede miran to sọrọ ni oun ko tun ṣe oṣelu mọ lẹyin bi Eyitayọ Jegede ṣe fidirẹmi. Lasiko ti akọroyin BBC kaakiri agbegbe Eyitayo Jegede, ni ṣe lo pa lọlọ ti ko si si ẹni to n dunnu ni agbegbe naa. Ìfẹ́ tí mo ní sí aráàlú ló gbé mi wọlé lẹ́ẹ̀kejì - Gomina Akeredolu Gomina ipinlẹ Ondo, Oluwarotimi Akeredolu ti ni ifẹ ti oun ni si awọn araalu lo jẹ ki wọn dibo fun oun gẹgẹ bi gomina fun saa keji. Gomina Akeredolu sọ eyi lasiko to jawe olubori ninu didbo sipo gomina ni ipinlẹ Ondo. Akeredolu tun dupe lọwọ aarẹ Muhammadu Buhari ati igbakeji rẹ, Yemi Osinbajo fun atilẹyin wọn saaju ati lasiko idibo naa. Bakan naa lo dupẹ lọwọ gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu, gomina ipinlẹ Ekiti, Kayode Fayemi, Gomina ipinlẹ Ogun tẹlẹ, Ibikunle Amosun,gomina ipinlẹ Kogi, Yahaya Bello, gomina ipinlẹ Kebbi ati gomina ipinlẹ Jigawa. Bakan naa lo dupẹ lọwọ Lucky Ayedatiwa to dije gẹgẹ bi igbakeji gomina, to si rọ ki o maṣe da oun lẹyin o rẹyin. O tun dupẹ lọwọ awọn ti wọn jọ dije dupo labẹle pe wọn ba oun ṣiṣẹ. Ninu ọrọ tirẹ, Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ni ibi giga ni ipinlẹ Ondo n lọ, nitori naa ki wọn ma a gbadura fun un lati mu gbogbo ileri rẹ ṣẹ. Gómìnà Akeredolu la Jegede mọ́lẹ̀ wọlé ìbò gómìnà Ondo fún sáà kejì Gomina Rotimi Akeredolu ti wọle ibo gomina ipinlẹ Ondo to waye lọjọ Abamẹta, ọjọ kẹwaa, oṣu kẹwaa, ọdun 2020. Akeredolu to jẹ oludije labẹ ẹgbẹ oṣelu APC la oludije ẹgbẹ oṣelu PDP, Eyitayo Jegede to sun mọ ọ julọ ninu eto idibo naa mọlẹ. Eyi tumọ si pe Akeredolu ti wọle ibo gomina ipinlẹ Ondo bayii fun igbakeji. Akeredolu lo moke ninu ijọba ibilẹ to pọ julọ ni ipinlẹ Ondo nigba ti Jegede oludije PDP atawọn to ku si tẹ le e. Ninu esi idibo awọn ijọba ibilẹ ti wọn kọkọ ka, APC moke ninu ijọba ibilẹ mejidinlogun to wa ni Ondo. Akeredolu ati igbakeji rẹ Akeredolu lo gba ju bẹrẹ lati ijọba ibilẹ Akoko North West, Akoko North East, Akoko South East ati Akoko South West. coronavirus prevention badge update: Wo òótọ́ àti irọ́ tó wà nínú báàjì àyà náà Awọn yoku ni Ile Oluji/Okeigbo, Owo, Idanre ati Ondo East. Awọn ijọba ibilẹ ti PDP ti moke ni ijọba ibilẹ Ifedore, Akure North ati Akure South. A o maa mu ẹkunrẹrẹ iroyin naa wa fun yin ni kopẹ kopẹ. Nigeria movie industry: Àgbà òṣèré, Lere Paimo ní àìgbọràn ló ń da ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn",0,yoruba "Ní nígbà àkerekere, Baàlè ri Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀. ti Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba Ìjàm̀bá Àwọn Ológun Mauritania 28 tí wọ́n pa ní ọjọ́ Òmìnira tí a kò sọ,0,yoruba àwọn ìkòkò tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà.,0,yoruba àdùkẹ́ ọlọ́run ó ní jẹ́ kí á ké o èwo ni àdùké,0,yoruba "PDP kò gbàgbọ́ nínú ètò ìdìbò ìjọba ìbílẹ̀ típínlẹ̀ Imo fẹ́ ṣe lóṣù keje ọdún yìí Ọjọ́ kẹrìnlá, oṣù keje ọdún yìí ni wọ́n ń pinnu kí ìdìbò fún yíyan alága ìjọba ìbílẹ̀ nípínlẹ̀ Imo wáyé. Ọgbeni Damian Opara, tó jẹ̀ alukoro ẹgbẹ́ náà fún ipínlẹ̀ Imo, fi àtẹ̀jáde síta pé kí àwọn ọmọ ẹgbẹ́ rẹ fà sẹ́yìn nínú ètò ìdìbò náà O ní ìgbésẹ̀ ìdìbò náà ti ń ni ǹkan míràn nínú, àfi ti àjọ elétò idìbò INEC bá gba àṣẹ ilé ẹjọ́ tó ga jùlọ pé kí wọn sún un síwájú. PDP: A fẹ́ gba odindin Imo padà ni lọdún tó m bọ Ogbeni Deji Doherty tọ jẹ́ ọmọ ìgbìmọ̀ amúṣẹ́ṣe ẹkùn ìwọ̀ oòrùn Naijiria ṣalaye ìpinnu ẹgbẹ́ PDP pé ìdìbò àpapọ̀ ló jẹ PDP lógún bayìí, kìí ṣe tìjoba ìbílẹ̀. A kò tíì rì agbẹnusọ àpapọ̀ ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress bá sọ̀rọ̀ di ìsinyìí.",0,yoruba ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba aare esikis sir ema binu o se wan se ogun magbele fun yin ni etun ti kori si ono equatorial guinea abi,0,yoruba "Ọrọ di bo o lọ, yago fun mi nilu Ikẹrẹ-Ekiti, nipinlẹ Ekiti, lọjọ Isinmi, lasiko ti ija ṣẹlẹ laarin awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun. Iroyin ta a gbọ ni pe alẹ ọjọ Satide ni wahala naa ti bẹrẹ nigba ti awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun kan yinbọn pa ọkunrin kan ti wọn pe ni Ojuale. A gbọ pe nitosi Gbọngan ilu naa to wa ni agbegbe Odo Oja ni wọn ti yinbọn pa Ojuale, ti iroyin sọ pe ọmọ ẹgbẹ okunkun ni oun naa. Awọn iwe iroyin abẹle sọ pe botilẹ jẹ pe ọmọ ilu Ikẹrẹ ni Ojuale, ṣugbọn ilu Port Harcourt lo n gbe. aaaaaaaaaaaaaaa Ayẹyẹ igbeyawo ọrẹ rẹ kan la gbọ pe o wa fun, ki awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun to o yinbọn pa. Ko pẹ lẹyin ti wọn pa Ojuale, ni awọn ọmọ ẹgbẹ rẹ naa tu jade pẹlu oriṣiriṣi nkan ija oloro, ti wọn si bẹrẹ si ni kọju ija si awọn olugbe ni agbegbe naa. ""Bẹẹ ni wọn n yin ibọn lakọlakọ, eyi to mu ki awọn araalu o sa asala fun ẹmi wọn. Nigba to fidi iṣẹlẹ naa mulẹ fun BBC, agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ekiti, Sunday Abutu sọ pe lootọ ni iṣẹlẹ naa waye. O ni ṣugbọn, ọwọ ti tẹ afurasi 45 lori iṣẹlẹ naa, ti wọn si ti wa ni agọ ọlọpaa. hhhhhh Bakan naa lo sọ pe awọn ọlọpaa ṣi wa ni agbegbe naa lati tẹsiwaju pẹlu eto aabo titi ti alaafia yoo fi jọba. A gbọ pe awọn ara ilu Ikẹrẹ ti bẹ ijọba ipinlẹ Ekiti, lati tọpinpin bi ija laarin awọn ẹgbẹ okunkun ṣe n waye nigba gbogbo ninu ilu naa. Lori eyi, Abutu sọ pe lootọ ni, ti ileeṣẹ ọlọpaa si ti mu awọn ọmọ ẹlẹgbẹ okunkun kan, ṣaaju ikọlu to tun waye ni ọjọ Satide. Ninu iṣẹlẹ to waye lọjọ Satide mọju ọjọ Aiku yii, iroyin ti ao ti le fidirẹmulẹ sọ pe ko din ni eeyan mẹfa to kú.",0,yoruba "ìwájú. Ọba lo ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba nípa ài: ti o nuni ti o nuni ti o jare.,0,yoruba "ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "Ọpọlọpọ awọn ere itage ati sinima lawọn agba oṣere ni ilẹ Yoruba ti gbe jade eleyi to ti mi orilẹede Naijiria ati oke okun tititi. Ṣaaju asiko yii, itan ati agbekalẹ ere Yoruba maa n mu ọpọlọpọ lọkan to bẹẹ gẹ ti awọn ti kii ṣe ọms Yoruba. Bẹẹ, wọn ko si gbọ Yoruba pẹlu nigba naa maa n joko ti awọn eeyan to ba gbọ lati maa tu ohun ti wọn ba sọ nitori igbesẹ ṣisẹ n tẹle awọn ere sinima naa, a maa fa eeyan to ba n wo o lọkan, yala o gbọ ede Yoruba ti wọn n sọ ni tabi ko gbọ. Ni awọn nnkan bii ọgbọn ọdun si ogoji ọdun sẹyin, awọn ere manigbagbe kan to jẹ Yoruba pọ lọ biba, ṣugbọn mẹwaa ninu wọn la o maa gbe yẹwo ninu akọsilẹ yii. Ko si aniani bi eeyan ba sọ pe sinima ogbori ẹlẹmọṣọ wa lara awọn sinima to jade ni ilẹ Yoruba to si jẹ manigbagbe. Sinima ti ọwọja rẹ tan kalẹ kọja orilẹede Naijiria ni ti ọpọ ẹya ati ede si wo o. Iṣe ati itan ere naa pẹlu awọn oṣere to ṣe ni wọn dun un wo.Itan iṣẹdalẹ ilu Ogbomọṣọ ni, Ogbori Ẹlẹṣọ, ni ipa ti Lalude ko ninu ere naa , ti Lere Paimọ si ko ipa Ṣọun Ogunlọla nibẹ. Ere kan ti ọpọ ọmọ Yoruba, paapaajulọ awọn onworan sinima Yoruba ni sinima ""Ti Oluwa nilẹ"". Ninu sinima yii ni Alhaji Kareem Adepọju ti ọpọ mọ si Baba Wande ti di ilu mọọka. Sinima to kọ ẹkọ to si tun panilẹrin ni. Ti Oluwa nilẹ da lori pataki ti Yoruba so mọ awọn dukia ilu, paapaa ilẹ Oriṣa. Ohun to gbe soke ni bi Yoruba ṣe maa n bọwọ fawọn ohun iṣẹdalẹ rẹ pẹlupẹlu idukoko aṣa ọlaju. Awọn eeyan kan fẹ ra ilẹ fi ṣe owo nla ni wọn ba kan si oloye ilu naa kan, iyẹn Oloye Ọtun (Baba Wande) Wọn gbe owo gọbọi fun lẹyin o rẹyin gbogbo awọn to lọwọ si tita ilẹ naa loriṣa ilu naa pa. Adapọ awada laarin ẹkọ ti wọn fẹ fi sinima naa gbe jade tun jẹ ki ọpọlọpọ onworan o tun gbadun sinima naa pẹlu awọn eekan alawada bii Kayọde Ọlaiya (Adẹrupọkọ) Tunde Kelani lo dari ere naa naa lọdun 1993, Kareem Adepoju lo kọ ọ. Awọn agba oṣere bii Dele Odule, Lekan Oladapo, Yemi Shodimu, Yetunde Ogunsola, Oyin Adejobi, Gbolagbade Akinpelu, Jide Oyegunle, Akin Sofoluwe naa kopa ninu ere naa. Ọkan lara awọn iwe akagbadun ti Ọjọgbọn Akinwunmi Iṣhọla kọ ni ọdun 1974 ni ""O leku"". O le ku yii ni eekan onisinima, Alagba Tunde Kelani sọ di sinima ni ọdun 1997. Itan ere ifẹ laarin ololufẹ Aṣakẹ, Lọla ati Ṣade ti wọn fẹ fẹ Ajani ni nnkan bii aadọta ọdun sẹyin ni iwe ati sinima yii. Gbogbo ohun elo ti wọn si lo nibẹ lo ṣe afihan eyi. Sinima yii lo si ṣe agbende iro ti ko ju orokun lọ tawọn eeyan n lo ni aye igbaun pada sagbo faari eyi ti a wa n pe ni ole ku. Ajani jẹ akẹkọ ipele aṣekagba ni fasiti to n wa afẹsọna nitori ipe iya rẹ to n fẹ ko ṣe igbeyawo ni kiakia. Sinima yii rinlẹ lasiko to jade nigba naa. Ọkan lara awọn ere to gbilẹ ni nnkan bii ọgbọn ọdun sẹyin ni ere yii. Oloogbe Ajilẹyẹ lo ṣe. Nigba naa, awọn ere to ṣe afihan igbagbọ Yoruba ninu aye akamara ni oloogbe Ajilẹyẹ maa n ṣe nigba naa. Ija laarin awọn awọn ẹlẹyẹ funfun ati dudu ni sinima naa da le lori. Awọn agba oṣere bii Oloogbe Ajilẹyẹ, Oyiboyi, Kọledowo, oloogbe Oriṣabunmi, Abija ati bẹẹbẹl lọ lo wa ninu sinima yii. Ọkan lara awọn ere sinima to milẹ nigba to jade ree. Ere ifẹ ni Alagba Yẹmi Ayebọ maa n saba n ṣe nigba naa pẹlu awọn orin ifẹ ninu rẹ. Lẹyin ipapoda Ade Love, ko fi bẹẹ si awọn sinima ifẹ to ni alafibọ orin ninu mọ ki Yẹmi Ayebọ to de pẹlu sinima Yẹmi my Lover. Sinima naa da lori omidan Moji ati Yẹmi ṣugbọn ti o ba inira diẹ pade. Lọdun 1990 ni ere naa jade, awọn osere bii Abija, Yẹmi lukuluku, Thompson, Alabi yellow ati bẹẹbẹẹlọ. Ere miran niyi to tun gbajumọ lọpọ ọdun sẹyin. Alhaji Yẹkini Ajilẹyẹ lo gbe sinima naa jade nigba naa. Itan Ewurẹ abami kan to n hu iwa buruku ni sinima yii da le lori. Awọn agbagb oṣere bii Grace Oyin-Adejọbi (Iya Osogbo), Kọledowo, ati bẹẹbẹlọ. Ọkan lara awọn gbajumọ ere sinima to waye laarin ogun ọdun si ọgbọn ọdun sẹyin ni sinima Owoblow jẹ. Ọpọ onwoye sinima Yoruba lo si n sọ pe ere yii gan lo sọ Taiwo Hassan (Ogogo) ati Yinka Quadri(kura) di gbajugbaja. Sinima naa da lori ọdọkunrin kan to di janduku ati ọlọsha lẹyin ti wahala awọn ẹbi rẹ tii sita. Awọn agbofinro ran baba rẹ lọ sẹwọn, ileewe si lee jade nitori aile san owo ileewe. Wọle gbiyanju ohun gbogbo to lee ṣe lati tọju iya rẹ atawọn aburo rẹ ṣugbọn ko bọ si ki o to di ajẹgboro lẹyin ti wọn koo mọ ""roga"" ti ko si fẹ pada lọ ba iya rẹ mọ nitori ojuti. Awọn eekanosere to kopa ninu rẹ ni Racheal Oniga, Bayo Bankole, Adebayọ Salami (Ọga Bello), Adewale Ẹlẹṣọ, Kayọde Odumoṣu, Binta Ayọ Msgaji, Sam Loco Efe, Bimbọ Akintọla, Ọmọọba Leke Ajao Ere awada ni Larinlọọdu jẹ. ọkan lara awọn eekan alawada igba naa, Babatunde Omidina (Baba Suwe) ati aya rẹ oloogbe Monsurat Omidina (Mọladun). Gbajugbaja agbe sinima sita ni, Shan George, Jide Kosọkọ, Yọmi King (Ọpẹbẹ), Yẹmi Ẹlẹshọ, Dele Odul. BMuka Ray, Rẹmi Surutu, Doris Simeon, oloogbe Henrietta Kosokọ, oloogbe Alaaran, oloogbe Yọmi Ogunmọla, Gbenga Adewusi naa ba wọn lọwọ si sinima naa nigba naa. Itan rẹ da lori Baba onile kan (Baba suwe) Ara awọn sinima ti alagba Ọlaiya gbe sita ni. oloogbe Ajidara ko ipa manigbagbe ninu sinima yii. Sinima naa da lori fifi ipa wa owo pẹlu awọn alafibọ awada ninu rẹ. Awọn eekan oṣere bii Branch, Bimbọ ọshin, Ajidara, Ọlaiya ati bẹẹbẹẹ lọ. Ara awọn sinima ti Tunde Kelani gbe jade ni Saworo idẹ. Itan to yannana ipo eto oṣelu lorilẹede Naijiria nigba naa ni Saworoidẹ. Lasiko ti orilẹede Naijiria wa labẹ iṣejọba ologun to si n gbaradi fun ijọba alagbada ni. Awọn eekan oṣere bii Kọla Oyewọ, Lere Paimọ, Bukky Wright, Kunle Bamtẹfa, Kọla Ọlaiya (Adẹrupọkọ), oloogbe Bayọ Faleti, Ọjọgbọn Akinwunmi Ishọla, Ere yii lo gbe Kunle Afọlayan ati Kabirat Kafidipẹ jade faye ri.",0,yoruba Toò. Mo fi sílẹ̀ fún isẹ́jú méje sí mẹ́jọ nínú omi-gbóná. Ó kúkú tẹ̀. Ẹṣeun o. Ọbẹ̀ ilá ni tòní. Ẹ bámi ire o. #Eba #Gaari #Ijebu,0,yoruba yi yi ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba Igi àtòjọ-ẹ̀yàn ṣófo,0,yoruba RT @user: @user sebi eniyan mi ni won. Awon ti mo soro won fun yin. Awon wonyii gan-angan ni mo n so nipa won. Eniyan laso mi #Appr…,0,yoruba Àkóbì níjó òní nípa àìkú. Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.. Eyi ni adetokun ninu ilu.,0,yoruba láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ àti ìbi tí wọn wà.,0,yoruba "nípa àlùfáà. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba a yi fi ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó.,0,yoruba "Kọmiṣọna feto ilera, Ọjọgbọn Akin Abayọmi ṣalaye pe ọpọlọpọ awọn arinrinajo wọle lati oke okun lo jẹ pe iwe ẹri ayẹwo COVID-19 ti wọn n gbe kiri kii ṣe ojulowo. O ni ijọba ipinlẹ Eko ti n gbe igbesẹ lati rii daju pe ọwọ tẹ awọn eeyan to wa nidi iwa ibajẹ naa. Jude Chukwuka: Wò ó bí òwé Yorùbá ṣe yọ̀ lẹ́nu ọmọ Igbo Ọjọgbọn Abayọmi ni ọpọ awọn to n wọle lati ilẹ okeere lo ni ajakalẹ aarun naa, bẹẹ ni iye awọn to nii laarin wọn n pọ si ni. O ni laipẹ ijọba yoo fi panpẹ ofin ko gbogbo awọn to n ra tabi ta ayederu iwe ẹri ayẹwo COVID-19 naa.",0,yoruba ìlù ilẹ̀ẹ wa drums of our land,0,yoruba aṣiwèrè èyàn ló ńsọ pé irú òun ò sí irú ẹ̀ pọ̀ ju ẹgbàágbèje lọ only a deluded person will claim theres none li,0,yoruba "Awon oludije Ile igbimọ asoju sofin Eti Osa Awọn oludíje márùn-ún tó péju síbẹ̀ ní Olubankole Wellington (Banky W) láti ẹgbẹ́ òṣèlú Modern Democratic Party (MDP). #BBCRepDebate: Ìjíròrò náà fáwọn olùdìbò l'Eko ní ànfàni láti bèèrè ohun tó jẹ wọ́n lógún Awọn yoku ni Ibrahim Obanikoro lábẹ́ àsíá ẹgbẹ́ All Progressives Party (APC), Tessy Owolabi tí ẹgbẹ́ òṣèlú Social Democratic Party (SDP) ati Omotesho Tony Bakare ti People's Democratic Party. Ọ̀rọ̀ ẹkún omi Eti Ọsa ló jẹwa lógun - Àwọn olùdíje aṣojú-sòfin Bakan naa ni Ferdinand Ladi Adimefe tí ẹgbẹ òṣèlú Alliance for New Nigeria (ANN) ko gbẹyin nibẹ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Nínú ìfọ̀rọ̀jomitoro ọ̀rọ̀ tó wáye fún bii wákàti méji, gbogbo àwọn olùdíje ló sàlaàyé pé, ohun tó jẹ àwọn lógun jùlọ ní láti móju tó ọrọ̀ ẹ̀kún omíyale àgbàrá ya ṣọ́ọ̀bù tó ń da àwọn ènìyàn etí ọsà láàmú láti ọjọ́ pípẹ́ wá. Adimefe ti ẹgbẹ́ òṣèlú ANN sàlàyé pé òhun yóò kọ́kọ́ ṣe àgbékalẹ̀ ọ̀ná táwọn ọ̀dọ̀ yóò gbà ni ìmọ̀, lẹ́yìn èyí ni wọn yóò wá pèsè irinṣẹ́ ti wọn yoo lọ. Bakan náà, lori ọ̀rọ̀ àwọn ọ̀dọ́ tí kò níṣẹ́ lọ́wọ́, Adimefe ti ẹgbẹ́ òṣèlú ANN sàlàyé pé, òun yóò kọ́kọ́ ṣe àgbékalẹ̀ ọ̀ná táwọn ọ̀dọ̀ yóò gbà ni ìmọ̀ lẹ́yìn èyí ni wọn yóò wá pèsè irinṣẹ́ ti wọn yoo lo. #BBCRepDebate: Ìjíròrò náà fáwọn olùdìbò l'Eko ní ànfàni láti bèèrè ohun tó jẹ wọ́n lógún 'A ni òfin púpọ̀ ní Naijiria ṣùgbọ́n a kò bọ́wọ́ fún un ni' Ní ti Obanikoro, ti ẹgbẹ́ òṣèlú APC, ó ni ohun tó ṣe patàkì jùlọ ni láti tẹti sílẹ̀ fún ohun ti àwọn ènìyàn fẹ, èyí ni yóò sọ ohun ti àwọn yóò ṣe, tí ètò amúludùn kò sì ni wọn ni agbegbe Eti Osa. Ọ̀rọ̀ ẹkún omi Eti Ọsa ló jẹwa lógun - Àwọn olùdíje aṣojú-sòfin Ogbẹni Bakare ti ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ní ó ṣe pàtàkì láti jẹ aṣojú tòótọ, èyí ni yóò fún àwọn ènìyàn àti láti le dúna dúrà pẹ̀lú wọn. Ètò ijiroro náà fún àwọn olùdìbò ní ànfàni láti bèèrè ohun to jẹ wọn logun lọ́wọ́ awọn oludije to n gbero lati lọ soju wọn nile asoju-sofin ilẹ wa.",0,yoruba @user Shey awon fulani adaran lo tun wa jo'le abi awon hoodlums. #SundayIgboho #Fulaniherdsmen #StaySafeNigeria #Yoruba,0,yoruba "tí Ọmọ fè joko, Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba "Àwọn alágbàwí èdè gbà wí pé lílo ìlànà Látíìnì , tí ó jẹ́ ìṣọwọ́kọ láti ilẹ̀ òkèèrè , fún kíkọ àwọn èdè Ilẹ̀ - Adúláwọ̀ sílẹ̀ , fi ilẹ̀ náà sínú ipò ẹrú .",0,yoruba "owó àkokò, Ọba ri Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "àìkú. Nitori eyi, ara eni lo ni ìgbà mi owó àkokò, Baàlè ri Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba Semo kì í ṣe oúnjẹ ìbílẹ̀ https://t.co/XvGBxkywct,0,yoruba ọba. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa òkè: ti o nuni ti o dara.,0,yoruba "Ẹ̀yin ará Benin ẹ kú ilé o, vhojehee! #Benin",0,yoruba RT @user: #TweetinYoruba Ikilo pataki fun eyin ti eba fe gbe Iyawo aloku si ile. https://t.co/b2gzF96M2S,0,yoruba ọmọ ri pe lẹ ìkòkò wey ti o nuni ti o nuni ti o nuni ti o ní wúlò.,0,yoruba àṣà ìdílé. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba Alábàágbé àti alájọṣe iyùn ni àwọn ewé inú omi tí ó máa ń bá a kó ohun aṣaralóore pamọ́ àti da èérí ara nù .,0,yoruba "Nígbà tí Bàbá fè mú, Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..",0,yoruba "yì í tún ṣe àwọn iṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba Omoluabi wa ni ọ̀ṣun ìlú ni nfàn ojú kakaaki.,0,yoruba "RT @user: @user @user @user @user hmm.oruko omo si ni ijanu omo,se eyi wa ni itumo si iwuwasi awon omo ode…",0,yoruba "ÒWE/ PROVERB Ẹni tó bá ṣ'ẹ́ni Lẹ́hìn ọrùn, èèyàn ò lè gbà kí ó fọ́ èèyàn lójú. Ó sunwọ́n kí èèyàn fi ààlà sí àárín ẹni tó fẹ́ràn láti ma ṣe ni ní aburú. ¦ ¦ He who breaks one's neck bone, cannot be allowed to make one go blind. Always give evil people some distance",0,yoruba kan kò le fi ara jé iwa rere.,0,yoruba "Awuyewuye ti kọjáa ti gbàgede orí ẹ̀rọ - alátagbà , ó kàn dé ilé - ìwé àti àjọ ìlú .",0,yoruba ọjà òyìngbò kò mà mà mọ̀ pẹ́nìkan ò wá o bí a bá ṣẹ̀ yín o ẹ̀yin àgbààgbà ẹ yé forí jìn wá o,0,yoruba "Ikọlu wáyé láàrin àwọn ọmọ ogun Nàìjìríà àti Shiite Fọ́fọ́ ni gbogbo àwọn ìlooro kọ̀ọ̀kan kún fún òkúta àti agolo gáàsì ní ìlú Abuja lẹ́yìn ìkọlù tó wáyé láàrin àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà àtàwọn afẹ̀hónú hàn tó n bèèrè fún ìtúsílẹ̀ adarí ẹgbẹ́ Shiite, Sheikh Ibrahim Zakzaky. Se ni àwọn ọmọ àwùjọ mùsùlùmí yìí ńju òkúta bá àwọn ọlọ́pàá tí àwọn òsìsẹ́ aláàbò sì fín gáàsì padà tí wọ́n fi mú púpọ̀ lára àwọn afẹ̀hónú náà. Ìsekúpani darandaran; ọlọ́pàá mẹ́rin forí káásà ní Benue Ọlọọpa mẹrin ti papoda lẹyin ikọlu awọn agbebọn si ibudo awọn ọlọọpa ni ipinlẹ Benue, ti eniyan mọkanla si ti di awati. Isẹlẹ naa waye nigba ti awọn ọlọọpa n wa ọkọ kaakiri ni agbeegbe Anyibe titi to fi de ijọba ibilẹ Ayilamọ ni ipinlẹ Benue. Ẹ ka ẹkunrẹrẹ rẹ ni bii Awọn nkan miran ti ẹ ni lati mọ loni Gbọ iroyin iṣẹju kan BBC Fidio wa fun toni Sàká: Oun tí orí bá yàn fún ẹ̀dá ni kó ṣe Sàká: Oun ti orí bá yàn fún ẹ̀dá ni kó ṣe",0,yoruba Eḳọ tí a kọ eḳọ nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba RT @user: .@user A kú ojó méta o. Sé àlàáfíà ni? Gbogbo ilé n kó? #TweetinYoruba https://t.co/sL4t52EjfW,0,yoruba "àkerekere. Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.",0,yoruba "RT @user: E seun a dúpé o.. E k'àárò.. """"""""""""""""""""""""""""""""@user: Ẹkáàárọ̀ o. Ẹkú ewu òru. ṣé àláfíà ni?""""""""""""""""""""""""""""""""",0,yoruba @user Ọ̀rẹ mi àtàtà. Báwo ni òtútù? Ṣé ẹ ti kó gbogbo yìnyín tó rọ̀ sí iwájú ilé kúrò àbí? :),0,yoruba "Igba mi owó àkokò, Ọba lo ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..",0,yoruba "Chef Michael Elegbede lo se ọbẹ àjẹpọ́nnulá fun BBC Yorùbá loni. Àwọn èròjà ti o nílò wà ni àrọ́wọ́tó rẹ. Gbìyànjú láti sè é fún àwọn ará ilé rẹ lópin ọ̀sẹ̀ yìí ki wọn jẹ àjẹpọ́nnulá ọbẹ̀ tó dùn. Ẹja èpìyà, epo, irú, edé gbígbẹ, àlùbọ́sà, áyù, ẹtalẹ̀, tàtàṣé, ẹ̀fọ́ tẹ̀tẹ̀ àti rodo ni àwọn èròja ti o nilo lati fi rò ẹfọ rẹ ki o le fi gbadun iṣu sísè. Awọn èròjà aṣaralóore pọ ninu ọbẹ ẹfọ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Alase wa gbamọran pe ki ẹ fi ara balẹ wo ojú ẹja epiya ti ẹ fẹ ra pe ara rẹ ń dán, oju rẹ mọ́ rkekete",0,yoruba "Àkọ́kọ́, Ìyá joko lòdì Ìle-Ìfẹ̀. Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..",0,yoruba se joko. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba "@user: @user Ojumore lo Mon mi lo niooo"""""""""""""""" àti èmi náà, ojúmọ́ aláyọ̀ ni o",0,yoruba "lòdì Ìjẹ̀. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba (1). Kí ni òróró? (2). Kí ni òróòro? #Ibeere #Yoruba,0,yoruba "@user @user @user Ẹ má lajú sílẹ̀ kí tàlùbọ̀ kó wọ̀ ọ́. Ẹ rí i dájú wí pé ẹ dá àwọn ọmọlọ́mọ tí ó wà ní àhámọ́ ọlọ́pàá sílẹ̀ kí wọ́n máa lọ sílé wọn tàràrà. Wọn kò jalè, wọn kò hu ìwà láabi. Ẹ̀tọ́ wọn ni wọ́n ń jà fún! https://t.co/WHEfXwRbRM",0,yoruba Èyí ni òun tí a kọ eḳọ nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Bàbá lo ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú.,0,yoruba "Orúko mi ni Oladayo Oluwaseun omo wọn ní Igogo obiri ni Ipinle Ekiti. Èdè Yorùbá niyi púpò, ó sì dùn ni kika #TweetinYoruba",0,yoruba láti lé ẹ̀mí ibi dànù lílo òògùn ẹbu àsèjẹ tàbí àgbo àwọn ìṣe ìṣègùn yìí ti wà ní ilẹ̀ yorùbá láti ayébayé tí wọ́n sì ń gbòòrò si ní ọjọ́ sí ọjọ́ ìgbà sí ìgbà nínú ara ati ninu ẹ̀mí,0,yoruba 🐝 kùn ún yùnbùnyùnbùn {oyin/agbọ́n/ẹ̀fọ́n kun ọmọ náà yùnbùnyùnbùn\yùnbùn} 🐜 bò ó ṣíbáṣíbá {èèrá bo ìtọ̀ ọ̀mùtí ṣíbáṣíbá/ṣíbá} 🐍 ṣán an ṣókí {ejó ṣán àgbẹ̀ ṣókí} ................ #learnyoruba #Yoruba #language #InYoruba,0,yoruba o lẹ. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ài: ti o ní wúlò.,0,yoruba YouTube naa ní ègé olóótọ fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó wáyé.,0,yoruba ni ohun tí ó tó gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ àti ìbi tí wọn wà.,0,yoruba àìmọ́. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó wáyé..,0,yoruba "Agbẹnusọ fun gomina ọhun, Isa Gusau sọ fun awọn oniroyin pe awọn alfa naa to jẹ ọmọ Naijiria, ti gbe ni ilu Makka fun ọpọlọpọ ọdun. Gusau ni, awọn alfa ọhun lo n fi tọsan toru gbadura ni Ka'aba. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: O ṣalaye pe ẹni to dagba julọ ninu awọn alfa naa ti lo ogoji ọdun ni Ka'aba. Agbẹnusọ fun gomina naa ni ""Ka'aba jẹ ibi mimọ julọ to wa ni moṣalaṣi Al-Haram ni Makkah."" O sọ siwaju si pe, idi ti ijọba ọhun fi gbe igbesẹ lati bẹ awọn alfa naa lọwẹ wa lati ran awọn ọmọ ologun Nigeria lọwọ ninu ija wọn pẹlu ẹgbẹ Boko Haram. Gusau ṣalaye pe ijọba ipinlẹ Borno nilo adura gidigidi lasiko yii ki alafia le jọba ni ipinlẹ naa. Igbesẹ yii lo waye lẹyin ọjọ diẹ ti ọga agba fun ajọ ologun Naijiria, Tukur Buratai ni oirilẹ-ede yii nilo adura lati koju ẹgbẹgun Boko Haram.",0,yoruba Omoluabi wa ni àìmọ́ lo je ti ibile. A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà.. A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba "Ọṣẹ ìwẹ̀ oní èròjà àtọwọ́dá ni àwọn èèyàn wa yàn láàyò, wọn gbàgbé pé erùpẹ̀ ni wá, ohun ìṣẹ̀dá t'ó ti ilẹ̀ wá l'ó yẹ ara wa. #Yoruba",0,yoruba Àkóbì níjó òní nípa ìbàdandun ìlú lo je gbogbo ise ibile tèmi.,0,yoruba fi ti o nuni ti o nuni ti o nuni ti o dara.,0,yoruba ilera ṣẹlẹ ni Lagos ti gbogbo eniyan sọ o dara. (2025),0,yoruba "Gbajugbaja oṣere tiata, Eniola Badmus ti di aṣjoju ajọ LAWMA to n ri si gbigba ipinlẹ Eko mọ. Eniola fi oriṣiiriṣii fọto bi wọn ṣe sọ di aṣoju ajọ LAWMA soju opo Instagram rẹ. Gbajugbaja oṣere naa ṣalaye pe aṣọ ti oun wọ lọ si ibi ayẹyẹ ''Headies award'' lo sun oun de bi ibi ire bayii. ''Ori ayelujara mi titi lori aṣọ ti Eniola wọ lọ si ibi ami ẹyẹ Headies Award niluu Eko, ọpọ lo sọ pe mo da bi oṣiṣẹ LAWMA pẹlu aṣọ ti mo wọ lọ si ibi ayẹyẹ naa. Mo gbagbọ pe ifẹ tawọn eeyan ni si mi lo jẹ ki wọn sọ pe mo dabi oṣiṣẹ LAWMA to n ko idọti loju titi. Ṣugbọn ọrọ ti wọn sọ ni bii oṣu meji sẹyin bayii ti ja si oriire fun mi. Nkan iwuri lo jẹ fun mi pe mo ti di aṣoju ajọ LAWMA nipinlẹ Eko. Mo ṣetan lati lo ẹbun ti Eledua fun mi lati ṣiṣẹ pọ pẹlu ajọ LAWMA,'' Eniola ṣalaye. Eniola dupẹ lọwọ ijọba ipinlẹ Eko fun anfaani ti wọn fun mi lati ṣiṣẹ pọ gbe ipinlẹ Eko ga si. O tun dupẹ lọwọ awọn ololufẹ rẹ bakan naa, o rọ wọn lati ṣiṣẹ pọ pẹlu ijọba gbe ipinlẹ Eko ga si. Eniola ti darapọ mọ Woli Arole, Bolanle Ninalowo ati Tobi Bakre gẹgẹ bi awọn oṣere to jẹ aṣoju ajọ LAWMA nipinlẹ Eko.",0,yoruba "tí Ìyá fè fi, A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..",0,yoruba iṣẹ́ aláwọ̀. Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.,0,yoruba ní òní nìkan ṣoṣo múrí mẹ́ta náírà lẹ ti gbọ̀n yọ kán mo ti sọ títí pàbo ni ó ń jásí kí ló dé ndan wọ́n bí ṣómi mẹ́ja ni,0,yoruba "Gbajugbaja oṣere tiata Ibrahim Chatta, ẹniti o ṣẹṣẹ ṣe ajọyọ ọjọ ibi aadọta laipẹ yii ti kede pe o seese ki oun fi adagba ere ṣiṣe rọ laipẹ. Ibrahim Chatta kede bẹẹ ninu ifọrọwerọ kan to se laipẹ yii pẹlu ileesẹ iroyin ayelujara Ibrahim Chatta ni ọdun marundinlogoji ni oun fi ṣe iṣẹ tiata, ninu eyi ti oun ti la ọpọlọpọ iṣoro kọja, papa julọ nigbati oun ṣẹṣẹ bẹrẹ ere tiata. Chatta ni oun ko ni iwe ẹri ile ẹkọ kankan nitori oun kọ lo si ile ẹkọ ri. Chatta ni lẹyin igbati oun di olokiki ninu ere tiata, ni oun ṣẹṣẹ ka iwe kẹfa tan, ti oun si wa ni ile iwe ti wọn ti ń ko nipa iṣe olukọni ni ilu Ikire. Chatta ni Ọlọrun nikan lo gbe ori oun soke nitori pe lẹnu iṣẹ tiata ni oun ti di ilumọọka, ti oun si di olokiki. Chatta fikun pe bo tilẹ jẹ wi pe ọmọ atapatadide ni oun, amọ ọpọlọpọ igba ni oun ma n lọ ṣe igbaradi ere tiata lai si owo lapo oun. O ni koda nigba mii, iṣoro ati gẹ irun kikun ori oun maa n buru nitori aisi owo lapo oun. Ibrahim Chatta ni ""iriri aye kan o le ti ni titi, ko ti ni pa, ṣugbọn ọgbọn lo ma n fi kọ ni"". Osere tiata naa ni awọn iriri oun ninu ere tiata lo jẹ ki oun fẹ fi adagba ere ṣiṣẹ silẹ, ṣugbọn oun ko ni kuro ninu ere tiata patapata. Ibrahim Chatta ni o ti to akoko ti oun gbọdọ sinmi nidi isẹ ere tiata, ti awọn ogo tuntun ti oun kọ niṣẹ tiata yoo si maa ṣe ere lọ. O fikun pe idunnu oun ni lati ri wi pe ere tiata goke agba ni orilẹede yii. Ibrahim Chatta tun tọka si awọn agba oṣere ti wọn ti fi adagba ere tiata rọ. Fun apẹẹrẹ Olu Jacobs, Oga Bello, Jide Kosoko ati awọn miran ti wọn ko fi gbogbo ara ṣe sinima agbelewo mọ. O ni lọwọlọwọ, iṣe agbẹ wa lara okoowo ti oun dawọ le, ti oun si ni ileesẹ ti oun ti n ya sinima. Ibrahim ninu ifọrọwerọ naa ni ""idunnu ọkan mi ni ki sinima agbelewo di nkan ti gbogbo agbaye yoo maa wo. Sugbọn a gbọdọ ri pe awọn oṣere tuntun mọ ohun ti sinima ati ere tiata jẹ, nitori ọpọlọpọ awọn oṣere tuntun ni wọn ko se jina to lati ṣe ere tiata.",0,yoruba "Ina ti jo ile oludije sipo gomina nipinlẹ Osun labẹ asia ẹgbẹ oṣelu Accord, Akin Ogunbiyi. Iroyin ni aarọ kutu ọjọ Isinimi ni ina ọhun dede ṣẹyọ, to si ba ile naa atawọn dukia mii to wa ninu ọhun jẹ ni Ileogbo, to wa ni ijọba ibilẹ Ayedire. Ile ọhun, to dojukọ ọọfisi ijọba ibilẹ Ayedire ni Ogunbi sọ pe oun ko mọ ohun to ṣokunfa bi ina ṣe sọ nibẹ. Nigba ti BBC Yoruba kan si Ogunbiyi, agbẹnusọ rẹ, Steven Owolabi ṣalayae pe ile ijọsin ni oludije naa wa ki wọn to ke si pe ina ti sọ ninu ile rẹ. O ni “Lootọ ni ina jo ile naa, amọ a ti yanju gbogbo rẹ.” “A ko mọ ohun to ṣokunfa ina naa titi di asiko yii, bẹẹ ina ọhun kii ṣe ina kekere.” “Inu yara rẹ ni ina naa ti bẹrẹ, gbogbo yara naa lo jona, bẹẹ naa ni awọn iwe kan to ṣe pataki ba ina ọhun lọ.” Owolabi ṣalaye siwaju si pe “Ọna ile ijọsin ló wa ki wọn to ke si pe ile rẹ ti n jona, adupẹ lọwọ Ọlọrun pe kii ṣe oru ọganjọ ni ina ọhun ṣẹyọ, ohun ti a n sọ bayii kọ ni a ba maa sọ... nitori ko si nnkankan to ṣeku ninu yara yẹn.” O pari ọrọ rẹ pe ko si ẹnikẹni to farapa ninu ijamba ina ọhun.",0,yoruba áwọn iṣẹ́ tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa aráyé: ti o dara.,0,yoruba "Ìlú yorubá lo ni àṣà yorubá eyti o gbe lori iwa rere. Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Ìran Yorùbá ní Ìpínlẹ̀ Kogi ni àwọn ará Ọkùn. Wọ́n tàn kiri ní Yagba-West, Yagba-East, Mapomuro, Kabba-Bunu, Ijimu àti ní àwọn àgbègbè Lokoja. Wọ́n ń sọ ẹ̀ka èdè bíi Ìyàgbà, Òwe, Ìjímù, Búnù àti owowo. Ṣùgbọ́n, Ọkùn ni ojúlówó èdè wọn.",0,yoruba "Èkó ni ìlú tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Alàji lo ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba a ní láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìwà: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba wo fun ipilẹ̀ ti o nuni ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọmọ lo tun se lọ.,0,yoruba "Lọjọ Ẹti ọjọ kẹsan osu kẹin ọdun 2021 ni Arẹmọ Phillip, ọkọ Ọbabinrin ilẹ Gẹẹsi, Queen Elizabeth II jade laye. Lati igba ti wọn si ti kede ipapoda rẹ l'awọn eekan lagbaye ti n daro rẹ. Awọn eekan ọmọ Naijiria pẹlu ko gbẹyin. Aarẹ Muhammadu Buhari to wa ni asiko isinmi ni ilu London fi ọrọ ibanikẹdun rẹ ranṣẹ lorukọ orilẹede Naijiria si Ọbabinrin lori ipapoda ọkọ rẹ, Arẹmọ Phillip. ""Iku Duke ti Edinburgh jẹ opin ijọba kan. Arẹmọ Phillip jẹ ọkan lara awọn gbajumọ ti gbogbo oju mọ jakejado agbaye ati ti a o maa ranti ipa ti o ko ninu ajọ Commonwealth. President Muhammadu Buhari extends his condolences to Her Majesty the Queen over the death of her husband Prince Philip who passed on peacefully at the age of 99. Gẹgẹ bi aarẹ ṣe sọ ọ, Arẹmọ Phillip ko ipa ribiribi ninu ṣiṣe ẹyinju aanu paapaa itọju awọn ẹranko ti Ọlọrun da ati fun idagbasoke awọn ọdọ ni orilẹede to le ni aadoje lagbaye. ""Apẹrẹ manigbagbe ọkọ ni o jẹ to ti fẹ Ọbabinrin lati ọdun 1947,"" to si ni eyi jẹ iwuri lọpọlọpọ fun gbogbo igbeyawo ni oniruuru ipele ti wọn ba wa"". Bakan naa, aarẹ Buhari ba ijọba ilẹ United Kingdom kẹdun, ajọ Commonwealth fun bi wọn ṣe ""padanu eekan agbaye yii"". Adari agba ajọ katakara lagbaye, WTO, Ọmọwe Ngozi Okonjo Iwealla ti ba Ọbabinrin ilẹ gẹẹsi, Olotu ijọba ilẹ Gẹẹsi, Boriis Johnson, idile ọba at'awọn eeyan ilẹ Gẹẹsi daro Arẹmọ Phillip, Duke of Edinburgh. Ni pataki julọ Ọmọwe Iwealla na ọwọ ibanikẹdun rẹ si Ọmọba William, Duke of Cambridge leyi to ti ni ko mọkan ko si ṣe bi akin ni ipapoda Arẹmọ Phillips. Ninu ọrọ tirẹ, igbakeji aarẹ Naijiria nigba kan ri, Atiku Abubakar sapejuwe iku Arẹmọ Phillips gẹgẹ bi eyi to mi gbogbo agbaye lọkan. O ni gbogbo agbaye yoo ma ṣeranti awọn iṣẹ aanu ti Arẹmọ Phillip gbe ṣe nigna aye rẹ eleyi to ni o mu ki o jẹ baba isalẹ awọn ajọ ẹlẹyinju aanu to to ẹgbẹrin Bakan naa ni Alaaji Atiku Abubakar tun yombo ipa to ko nipa sinsin ilẹ baba rẹ gẹgẹ bi ologun koda o ni gbogbo agbaye ko ni gbagbe aduroti rẹ fun Ọbabinrin Elizabeth keji. Igbakeji aarẹ tẹlẹ naa wa gbadura pe ki Edua o duro ti idile ọba nilẹ Gẹẹsi ati gbogbo awọn eeyan ilẹ naa Minisita orilẹede Naijiria fun ọrọ ilẹ okere, Geoffrey Onyeama naa sọrọ loju opo ileeṣẹ to n ri si ọrọ ilẹ okere wipe ibanikẹdun ohun lọ sọdọ Ọlọlajulọ Ọbabinrin Elizabeth, idile rẹ ati gbogbo eeyan Great Britain lori ipapoda Duke ti Edinburgh.",0,yoruba "Seyi Makinde: Tí aráàlú bá kọ̀ mí bíi gómìnà, ẹ̀rù kò bà mí láti fipò sílẹ̀",0,yoruba "RT @user: @user Asiko laye, ka tun ran ra wa leti, e tun te fun awon miran lati ri http://t.co/jWbn8yQg",0,yoruba "Ní ibòmíràn, ó di ago méjìlá òru kí òrùn ún tó wọ̀. Kódà àwọn ibìkan wà tí òrùn kìí wọ̀ fún oṣù mẹ́fà tí òkùnkùn náà sì nṣú f'óṣù mẹ́fà!",0,yoruba "joko, Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde sí ara ilẹ̀.",0,yoruba "Agbabọọlu mẹrinla lo ti gunlẹ si ibudo igbaradi naa Agbabọọlu ikọ Arsenal, Alex Iwobi lo lewaju awọn agbabọọlu to kọkọ gunlẹ si ibudo naa lọjọ aje. Awọn agbabọọlu to sẹsẹ darapọ mọ wọn nibẹ ni Francis Uzoho, Elderson Echiejile, Stephen Eze, Joel Obi, Shehu Abdullahi, John Ogu, Moses Simon, pẹlu Kenneth Omeruo. Wọn si n reti balogun ikọ Super Eagles, Mikel Obi Awọn agbabọọlu ti wọn ti gunlẹ sibẹ saaju ni Troost Ekong, Ola Aina, Tyronne Ebuehi, Brian Idowu ati Leon Balogun. Lowurọ ọjọ isẹgun lawọn agbabọọlu mẹjọ darapọ mọ awọn mẹfa to ti wa nilẹ bayii ni ibudo igbaradi naa. Awọn agbabọọlu mejidinlọgbọn ti wọn n gbabọọlu jẹun lorilẹede Naijiria ati nilẹ okeere ni olukọni ikọ naa, Gernot Rohr ransẹ pe lati kopa ninu ifẹsẹwọnsẹ meji ọtọọtọ ti yoo waye lọjọ ẹti laarin orilẹede Naijiria ati Poland pẹlu eleyi ti yoo waye laarin orilẹede Naijiria ati Serbia nilu London. Ikọ agbabọọlu Super eagles yoo maa koju Poland and Serbia gẹgẹbii ara igbaradi fun idije ife ẹyẹ agbaye Ikọ agbabọọlu Super eagles yoo maa koju Poland gẹgẹbii ara igbaradi fun idije ife ẹyẹ agbaye ti yoo waye losu kẹfa ọdun 2018 lorilẹede Russia. Orilẹede Naijiria yoo maa koju Argentina, Croatia, Iceland ni ipele akọkọ idije naa.",0,yoruba lo joko. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ẹkọ́: ti o nuni ti o jare.,0,yoruba pataki. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba Olusegun Obasanjo: Màá fi ìyókù ayé mi sin Ọlọ́run áti ènìyàn,0,yoruba "mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Baàlè joko. Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba Ènìyan ti nilo ẹka fun ẹkọ́ tabi ìbadandun.,0,yoruba "Odu ni Kayode Fayemi jẹ nidi iṣejoba ṣugbọn nnkan yato lasiko to pada wa yi Láì tíì ṣe ibura wolẹ́ sí ilé ìjọba, o ti n pinnu láti sàn owó oṣù oṣiṣẹ láàrín oṣù mẹfa. Ọ ni bi ìṣẹ́ òun òṣì ti peleke láàrin àwọn ará ìlú ko ṣẹyin bí ìjọba Fayoṣe tí kùnà láti san owó oṣù àwọn oṣiṣẹ. Ìkéde yí jé òun ti o mú àriwisi otooto wà láàrin àwọn ará ìlú àti àwọn amòye. Nínú èsì tí rè, Ọgbẹni Kola Bankole to je onimo nipa eto inawo so pe òun tó dáa ní kí ìjọba san owó ní kété ti oṣù bá parí fún àwọn oṣiṣẹ ṣugbọn ọ ti ya ju bi Fáyẹmí ti ṣe n ṣé ìlérí yí. ''Ko ti mò ipò tí akoto owó ijoba ipinle wa, bawo lo ti se fe san owo nigba ti ko ti mo awọn gbese to wa ni ile ati iye owo ti o''n wole fun ijoba ipinle ohun?'' Àwọn olóṣèlú a má ṣé ìlérí tí wọn kò ní lè mú ṣẹ fún ará ìlú lọpọ ìgbà Ọgbẹni Kola ní lootọ ni pé Fáyẹmí tí je Gómìnà nígbà kan rí ṣugbọn bí nnkan ti ṣe n ló lẹnu ọjọ mẹta yí tí owó tó yẹ kí ìjọba àpapọ pin fun àwọn ìjọba ìpínlẹ̀ kò ti ni iyanju, yóò ṣòro kí Fáyẹmí le mú irú ìlérí bẹẹ ṣé. ''O kàn n sọ ọrọ òṣèlú ní. Sisan owo oṣù kọja afẹnuso. O gbọdọ ṣe àyẹwò dáadáa kí ọ sí mó irú owó tí ìjọba ti tẹlẹ fi sinu akoto ìjọba bi bee kọ, oun ati awọn osise yoo pada gbena wo oju ara wọn''. Ìyà yìí pọ̀jù Suleiman Akingbolu tó jẹ́ oṣiṣẹ ìjọba ìpínlẹ̀ ní ìlú Ekiti ni kò bá dá ti Fáyẹmí ba le mú ìlérí yí ṣé nítorí ará n ní àwọn oṣiṣẹ. O ni ''ko yẹ ki awọn olosẹlu maa ka sisan owo osu gẹgẹ bi aseyori nitori ẹ̀tọ́ ni ki wọn gba owo lẹyin isẹ.'' Nígbà tí BBC béèrè pé báwo ní ìgbé ayé tí ṣe rọrùn laigba owó oṣù, Suleiman ní ìpeníjà nlá ní eyi jẹ fun awọn oṣiṣẹ. Ìpínlè Èkìtì wà lára àwọn ìpínlẹ̀ tí o n gba owó tó kéré jù láti ọdọ ìjọba àpapọ̀ ''Nnkán rọrùn díẹ fún àwa ti a n ṣé iṣẹ àgbẹ diẹdiẹ ṣugbọn fún àwọn tí kò ní ọnà míràn ìnira nlá ní àìrí owó oṣù gbà je'' Ìwádìí ilé iṣé BBC ṣé àfihàn pé oṣù kẹwa ọdún tó kọjá ní Gómìnà Fayoṣe san owó oṣù oṣiṣẹ ijoba ibile àti àwọn olùkọ kẹyìn. Ni ti awọn oṣiṣẹ ìjọba ìpínlè àti olùkọ ilé ẹkọ gírámà, Oṣù kíni ọdún yi ni wọn gbà owó oṣù kẹyìn.",0,yoruba fẹ. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ẹkọ́: ti o lẹ.,0,yoruba Ìle-Ìfẹ̀. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó ga jù.,0,yoruba "Nígbà àkerekere, Ọba lọ. Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..",0,yoruba ǹjẹ́ ọ̀làlà awo ọ̀bẹ àwa ṣọdún yìí a óò ṣe tèmíì tayatọmọ tọkọtayo ▼ ▲,0,yoruba ka ma so pe olori olori o da iwo to n so pe olori o da ipa kilo ti ko gaan nibi pe ko le da iwo ti o le je omo eyin r,0,yoruba "Ni iwaju bareke awọn ologun ni adugbo Mile 2 ni iṣẹlẹ yi ti waye lọjọ Ẹti. Ninu atẹjade ti ajọ to n mojuto iṣẹlẹ pajawiri nilu Eko fi sita lorukọ ọga agba Femi Osanyintolu, wọn ni epo bẹntiro ni ọkọ naa gbe lasiko to dẹgbẹ lulẹ. Osanyintolu ṣalaye pe epo naa ti da silẹ lasiko tawọn de ibi iṣẹlẹ naa ati pe awọn ṣi dawọ duro lati da epo naa si ọkọ mi. O ni idi ni pe awọn fẹ kan si ẹni to ni ọkọ agbepo naa ki awọn to bẹrẹ si ni da epo inu rẹ kuro. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn tó wà nínú ìjàmbá ọkọ̀ órí afára Otedola ń lọ ìpínlẹ̀ míì láti Eko ni - LASTMA Ileeṣẹ to n risi irinkerinko ọkọ oju popo ni ipinlẹ Eko, LASTMA ti sọ pe arinrin ajo ni awọn eeyan to wa ninu ijamba ọkọ to waye lori afara Otedola ni owurọ Ọjọbọ. Ọga agba ileeṣẹ naa, Olajide Oduyoye lo fi idi ọrọ naa mulẹ fun BBC. O ni awọn eeyan to wa ninu ọkọ akero funfun naa n rin irin ajo lati ipinlẹ Eko lọ ipinlẹ mii ni. O fi kun pe ""Awọn eeyan na n kuro ni ilu Eko ni, a ko mọ ibi gan ti wọn lọ, boya ipinlẹ Ogun ni wọn lọ tabi Oyo, a ko lee sọ, ṣugbọn ohun ti a mọ ni pe wọn n rinrin ajo kuro ni Eko ni."" Ni ti pe awọn eeyan naa tapa sofin to tako irinajo lati ipinlẹ kan si omiran lasiko Coronavirus yii, Oduyoye ni ofin naa yoo ṣoro lati tẹle. ""Nitori ọpọ awọn eeyan lo n ṣiṣẹ ni Eko ti wọn si n fi ipinlẹ Ogun ṣebugbe, papa lawọn agbegbe kan bi Berger, Mowe ati Ibafo. O ni ọpọ ninu awọn eeeyan to n yọlẹ rin irinajo lati Eko lọ ipinlẹ mii lo ma n parọ pe ile wọn ni wọn n lọ jẹ ko ṣoro lati mọ awọn to n lọ ipinlẹ mii. Oduyoye pari ọrọ rẹ pe iṣẹ LASTMA ni lati dari ọkọ ni igboro ilu Eko, ti ala iṣẹ iṣẹ wọn si pin si agbegbe Berger, nitori naa o ṣoro lati mu awọn eeyan to ba n lọ ipinlẹ miran. Ènìyàn kan kú, méje farapa nínú ìjàmbá afárá Otedola ní Eko Eniyan kan ti gbe ẹmi mi, ti eniyan meje si faragba ninu ijamba ọkọ to waye lori afara Otedola ni ipinlẹ Eko laarin ọkọ agbepo ati ọkọ igbooro ti eniyan mẹwa. Ileeṣẹ to n risi irinna ọkọ ni ipinlẹ Eko, LASTMA to fi iroyin naa lede, sọ pe aago mẹjọ aabo ni ijamba ọkọ naa waye laarọ Ọjọọbọ. Ọkọ Golf naa wa lara awọn ọkọ to lugbadi ijamba ọkọ naa, amọ ajọ LASTMA ni ko si ẹni to farapa ninu ọkọ naa. LASTMA ni gbogbo awọn oṣiṣẹ ajọ pajawiri lo ti wa nibẹ lati tete bojuto awọn eniyan naa. Bakan naa ni wọn ti gbe awọn ọkọ to ni ijamba kuro ni oju ọna, ki awọn ọkọ to n lọ, to n bọ ba a le ri ọna kọja. Ni bayii, wọn ti ṣi ọna silẹ fun awọn eniyan lati kọja, amọ sunkẹrẹ fakẹrẹ wa diẹ ni opopona naa. Bẹẹ ni Ajọ LASTMA wa kesi awọn eniyan lati ṣe jẹjẹ ni oju popo.",0,yoruba "Ọrọ ti gbajumọ oṣere, Iyabọ Ojo fi bẹrẹ ninu fidio kan to n ja ranyinranyin lori ayelujara ree ninu eyi to ti n fi iha to kọ si beeli ti wọn fun Baba Ijẹṣa han. Baba Ijesha ni eekan oṣere ti awọn ọlọpaa fi si ahamọ lori ẹsun iwa aṣemaṣe pẹlu majesin, tii se ọmọdebinrin adẹrinposonu nni, Princess. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ni ọjọ Aje, ọjọ kẹtadinlogun oṣu karun un ọdun 2021 ni adajọ Majisireeti agba kan ṣilẹkun anfani beeli silẹ fun Baba Ijẹṣa lori ọrọ ailera ara rẹ. Akungba Suicide: Ẹbí, ọ̀rẹ́ àti ọ̀gá iléẹ̀kọ́ sọ̀rọ̀ lórí irú èèyàn tí Feranmi Fasunle jẹ́ Iyabọ Ojo ni o fihan gbangba pe ọpọ ọmọ orilẹede Naijiria ni iwa imọtaraẹnikan ni ironu wọn. Eyi lo si faa ti ọpọ maa fi n de ijọba ti iwa kiko ọrọ ilu si ikawọ arawọn. O ni oun ko ti jami lori ọrọ ọmọdebinrin ti wọn fẹsun kan baba Ijẹṣa pe o ṣe aṣemaṣe pẹlu. O fi kun pe bi ọpọ ba ri ohun to ṣẹlẹ si ọmọdebinrin naa gẹgẹ bi eyi ti ko kan wọn",0,yoruba "A bí Kudirat Abiola ni ọdún 1951 ní ]ilú Zaria, òun ni ìyàwó keji ti Abiola fẹ́ tó si bi ọmọ mẹ́fa. Alhaja Kudirat Abiola pé ọdún mẹ́tàlélógún lónìí to wọ káà ilẹ̀ sùn, ọ̀pọ̀ ló gbàgbọ́ pé ìkú rẹ̀ kìí ṣe àmúwá ọlọrun nítori àwọn agbanípa ló pa a, nígbà ti ìjọba fi ọkọ rẹ̀ sẹ́wọ̀n. Wọn mú ọkọ rẹ̀ nígbà ti wọn rii pe oun ló ń jawé olúbori nínú ìdìbò àpàpọ̀ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà lọdun 1993. 'Ẹ dá owó padà f’áwọn ẹbí MKO Abiọla' A bí Kudirat Abiola ni ọdún 1951 ní ilú Zaria, òun ni ìyàwó keji ti Abiola fẹ́, tó si bi ọmọ mẹ́fa. Bí o tilẹ̀ jẹ́ pé oríṣirísi ìwádìí ló wáyé lẹ́yìn ikú Kudirat, ní ọ̀pọ̀ ọdún lẹ̀yìn ti ó ti kú, gẹ́gẹ́ bí ohun ti ìròyìn sọ, wọn pàṣẹ fún ènìyàn ẹlẹni mẹ́fà kan láti parí iṣẹ́ ọhun ni. Wọ́n pa Kudirat sínú ọkọ rẹ̀ pẹ̀lú ìbọn, bẹ́ẹ̀ ni awakọ̀ rẹ̀ náà bá ìṣèlẹ̀ yìí lọ pẹ̀lú, ṣùgbọ́n olùrànlọ́wọ́ pàtàkì rẹ̀ tí wọn fẹ̀sùn kàn pé ó lọ́wọ́ nínú iku rẹ̀, to wà nínú ọkọ pẹ̀lú rẹ̀, kò fi ara pa rárá. Lẹ́yìn ikú Kudirat Abiola ní wọn yíi orúkọ ilé iṣẹ́ rẹdíò tí wọn pé ni Radio Democracy, ti wọ́n ṣẹṣe dá sílẹ̀ ní Norway, pada sí Radio Kudirat. Eyi waye pẹ̀lú àtilẹ̀yin àwọn orilẹede bii Amẹríkà, ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì, Swedish, Danish àti ijọba Norway, lọna áti fí òpin si ìṣèjọba ológun ní Nàìjíríà pada, sí Radio Kudirat. Ní ọdún 1998, òpópónà kan ni New York náà tún yi orukọ pada láti máà jẹ́ Kudirat Abiola Corner. Lọ́dún 1998 bákan náà, Hamzat Al-Mustapha fara hàn nílé ẹjọ́ pẹ̀lú ọmọ ààrẹ ológun àna Abacha, Mohammed ti wọn fi ẹsùn ikú Kudirat Abiola kan. Níbi ìgbẹ́jọ́ náà àwọn ti wọn jẹ́rìí pé àwọn ní àwọn pa Kudirat ni Sergeant Barnabas Jabila sọ pé àṣẹ Al-Mustapha ni àwọn tẹ̀lé. Ní ọgbọ̀n ọjọ́ nínú oṣù kẹfà ọdún 2012, wọ́n dá ẹjọ́ ikú fún Hamza Al-Mustapha àti Alhaji Lateef Shofolahan lóri pípa Kudirat Abiola. Ọlórí ẹ̀sọ́ ààrẹ ni Al-Mustapha jẹ́ nígbà ti Shofolahan jẹ olùránlọ́wọ́ pàtàkì fún olóògbé náà. Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú",0,yoruba ọ̀tunọ̀tun lọ́jọ́ ń yọ ọ̀tunọ̀tun la ó ma bọ́jọ́ yọ,0,yoruba "Balogun ni lati ogoji ọdun sẹyin ti oun ti jẹ ọkan gboogi fun idile ọba ni ko ti si ẹni to n ta oye ni ilu Ibadan. O ni ẹgbẹrun meji naira si ẹgbẹrun marun naira ni awọn ti wọn ba fi jẹ oye ni ilu Ibadan ma n san, amọ awọn n gbọ pe Olubadan n ta oye fun awọn eniyan ni ọgbọn miliọnu naira. Otun ni ohun ti wọn ma n ṣe ni Ibadan ni wi pe, wọn ma n fi oye fun awọn ti wọn ba ni orukọ rere ni awujọ, bi wọn ko tilẹ ni owo lọwọ. Amọ, O ni ohun ti oun gbọ ni wi pe ẹni ti o ba ni owo julọ ni Olubadan n fun ni oye, bi ko tilẹ ni orukọ rere. Lori ẹsun wi pe wọn fẹ yọ ọba Olubadan ni ipo, Otun ti ilu Ibadan ni awọn ko sọ wi pe awọn fẹ yọ Olubadan. Ati wi pe ẹṣẹ si awọn afọbajẹ, iyẹn Balogun ati olori ile Olubadan ni ilu Ibadan ko lee sọ wi pe ki wọn yọ ọba bi o tilẹ jẹ pe wọn ni aṣẹ lati yọ Olubadan ni ipo. O fi kun un wi pe ẹṣẹ si ilu ni awọn fi le yọ Olubadan ni ipo, ati wi pe tita oye ilu Ibadan ja si ẹṣẹ si ilu, amọ awọn ko ni i lọkan lati yọ Olubadan nipo. Balogun fi kun un wi pe yiyọ Olubadan ni ipo lee ba ilu Ibadan jẹ, eleyii ti awọn ko fẹ ko ṣẹlẹ. Amọ gbogbo igbiyanju wa lati jẹ ki Olubadan fi ero rẹ lede lori ẹsun ti wọn fi kan an naa lo ja si pabo. Agbẹnusọ fun Olubadan, Adeola Oloko ko gbe ẹrọ ibanisọrọ rẹ, bakan naa ni oluwoye igbesẹ, Yanju Adegboyega naa ko gbe ẹrọ ilewọ rẹ.",0,yoruba alákòó. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Bàbá lo joko.,0,yoruba Lo ìyítumọ̀ tí àkọsílẹ̀ náà sọ ní pàtó,0,yoruba "Oludamọran pataki fun aarẹ lori ọrọ iroyin, Femi Adesina lo sọ fawọn ọmọ Naijiria nile ati nilẹ okere pe iroyin ofege lawọn kan n gbe kiri. End of Twitter post, 1 Ọgbẹni Adesina ni awọn ọmọ ẹgbẹ IPOB ko ni ohun kan ṣe pẹlu Aarẹ Buhari lati igba to ti de si ilu Yokohama lorilẹede Japan. Femi Adesina ni awọn ma ri ma sọ eeyan kan lo gbe iru iroyin yii kiri pẹlu ayederu fọnran lati tan ọpọlọpọ jẹ. Oludamọran aarẹ kilọ fawọn to n gbe iroyin ofege kiri pe ki wọn jawọn lapọn ti ko yọ nitori ọrọ Naijiria ti kọja iru iwa bẹẹ. O ni Buhari ṣetan lati ṣe nnkan iwuri fun gbogbo ọmọ Naijiria nibi apero to da lorim igbasoke ilẹ Afirika ẹlẹẹkeje iru rẹ TICAD7. Gomina ipinlẹ Eko, Kwara, ati Borno lo kọwọ rin pẹlu aarẹ lọ si orilẹede Japan.",0,yoruba @user Ẹnu mi rína ni :),0,yoruba "Laisi aato isejọba lati isalẹ pẹpẹ, ohun to nse orilẹede Naijiria ko lee dawọ duro Ọgagun agba ileesẹ ọmọogun oriilẹ lorilẹede Naijiria nigbakanri, Alani Akinrinade lo sọ ọrọ yii nilu Osogbo. Ọgagunfẹyinti Alani Akinrinade salaye wi pe pẹlu bi gbogbo awọn alẹnulọrọ lorilẹede Naijiria se npe fun aato isejọba ẹlẹkunjẹkun, federalism, ko daju pe eyi lee dẹkun wahala to n koju orilẹede Naijiria ni pato. ""Eto isejọba to wa nilẹ lorilẹede yii faaye gba gbigbe asiwere sori aga isejọba ti yoo si sọ gbogbo nkan bii ọgọsan miliọnu awọn ọmọ orilẹede yii to ku di asiwere pẹlu."" Ọgagunagba Akinrinade ni ọrọ orilẹede Naijiria ti di ti amukun, ẹru ẹ wọ to ni oke lẹ n wo, ẹ o wo isalẹ. Ipade lori ibagbepọ ẹya gbogbo lorilẹede Naijiria ko ye maa waye lati dẹkun wahala rẹ O ni o di igba ti orilẹede Naijiria ba tun isejọba rẹ to de isalẹ pẹpẹ ki o to lee di wipe atunto isejọba ẹlẹkunjẹkun tawọn eeyan n pe fun kẹsẹjari. ""Bawo leeeyan se fẹ maa gbe ni awujọ ti olukaluku sa ti n fi ikilọ ati gbedeke lelẹ ni gbogbo igba. Se a o lee fi ọwọ ara wa sisẹ jẹ ni. Se gbogbo wa ni yoo maa lọ ta epo ni ẹkun aringbungbun gusu ilẹẹwa eleyi ti awọn babanla wa ko se."" ""Ilẹ Yoruba gbọdọ jawọ ninu eto aragbe ti o nwaye lorilẹede Naijiria lọwọ ti kaluku n n gbe ẹnu si ohun to n ro jade ni ilẹ onilẹ."" O bu ẹnu atẹ lu ọrọ kan ti wọn ni minisita fun iwakusa ati ohun alumọni ilẹ lorilẹede Naijiria, Kayọde Fayẹmi sọ wipe, orilẹede Naijiria yoo sun kuro lori gbigbe ara le owo epo rọbi si owo iwakusa ati alumọni ilẹ. Ọgagunfẹyinti Alani Akinrinade ni eyi yoo tun bẹrẹ si ni 'gbẹ koto kaakiri ileto ati abule lati lee tun maa da ija ati wahala ọrọ ayika silẹ.'",0,yoruba awon ofin ti awon ile igbimo asofin ti ijoba apapo ba gbe kale ni a npe ni ise awon ofin ti ile igbimo asofin ijoba ipinle ni a npe ni ofin awon ofin ti awon ijoba ibile nse ni a npe ni ofin abele sugbon oti mo bayii,0,yoruba ègé olóótọ fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó wáyé.,0,yoruba RT @user: Ó yẹ kí a kọ ọ́ b'ó ṣe yẹ kítumọ̀ tí a fẹ́ lè hàn gbangba kedere. @user @user #EdeAbinibi #Yoruba #bloggerkiniyorubase…,0,yoruba ebi ò ní pa kóówá tọmọtọmọ o àmínàṣẹ,0,yoruba Èkó yii nípa ọsẹ àsa ni nfàn ojú kakaaki. Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba RT @user: O ma se o! Mi ò ri #tweetyoruba losé tó kója... E jé ka tun se #tweetyoruba lòjó mìí. Jooo,0,yoruba "Fayẹmi tun lo asiko naa lati fi iwe ẹri ti INEC fun han Aarẹ Muhammadu Buhari Fayẹmi sọrọ naa lẹyin to ṣe abẹwo si Aarẹ Muhammadu Buhari nile aarẹ to wa nilu Abuja. Fayẹmi ni 'oun yoo 'se iwadi eto iṣakoso ipinlẹ Ekiti labẹ iṣakoso Gomina Ayọdele Fayoṣe to n kogba wọle, fun anfaani eto iṣejọba to mọyan lori. O ni 'oun yoo wadi iye to wọle si apo ijọba ati idi ti owo awọn oṣiṣẹ ko fi jẹ sisan. Fayẹmi, to ti figba kan jẹ minisita fun idagbasoke iwa kusa ati irin tutu, tun lo asiko naa lati fi iwe ẹri moyege ti ajọ eleto idibo Naijiria, INEC fun lẹyin eto idibo to ti jawe olubori han aarẹ Muhammadu Buhari. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ile Igbimo Asofin Ekiti: ìjòkó jẹ́? A ko fẹ́ kú o Bi o tilẹ jẹ pe o sọ pe oun yoo yẹ awọn iwe akọsilẹ ijọba, Fayẹmi ni afojusun oun ki i sẹ lati tanna wadi Fayose tabi igbakeji rẹ, Olusọla Ẹlẹka. O ni afojusun igbesẹ naa ni lati ri i daju pe awọn ko ṣe aṣiṣe t'awọn to kọja sẹ. Ati lati fun awọn eniyan ipinlẹ Ekiti ni eto iṣejọba to dara. Bakan naa ni Fayẹmi ni oun ti bẹrẹ si ṣe awọn to yẹ ni imurasilẹ fun eto igbajọba. Fayẹmi ni oun ti bẹrẹ si ṣe awọn to yẹ ni imurasilẹ fun eto igbajọba. Ati pe ohun yoo ṣe igbelewọn awọn dukia ti Ekiti ni, to fi mọ awọn ohun to n nawo le lori. Igbakeji niyi ti ikede yoo jade lẹyin eto idibo gomina to waye nipinlẹ Ekiti lọjọ kẹrinla, oṣu Keje, ọdun 2018, nipa ṣiṣe iwadi eto iṣakoko Gomina Fayose. Ajọ to n gbogun ti iwa ijẹkujẹ ni Naijiria, EFCC, ti kọkọ fi ikede kan sita loju opo Twitter lati wadi mago-mago to waye lori idasilẹ ile adiyẹ kan ti ijọba ipinlẹ ekiti ṣe lasiko ti Fayose fi kọkọ ṣe gomina laarin ọdun 2003 si 2006. Ṣugbọn ajọ EFCC pada pa ikede naa rẹ.",0,yoruba Fi líǹkì ojú-ìwé lọ́wọ́lọ́wọ́ ránṣẹ́,0,yoruba bóbìnrin ò dán ilé ọkọ méjì wò,0,yoruba a yi fi ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọmọ lo aye àìlẹ̀.,0,yoruba "Ìran eégún dunjú, iwì ẹnu eégún dùn ún gbọ́ sétí, ṣé ti tijó àjó tàkìtì t'ó bálù mu ni k'á sọ, àbí ti orin kíkọ tòun èyí-ò-jọ̀yìí àrà. Egúngún ló ni k'á pidán, k'á jó, àti k'á p'ẹ̀ṣà. #Yoruba #araorun https://t.co/xNTphaoiU5",0,yoruba fijilante yinbon pa adamu niluu kaiama ni ipinle kwara o ti dero ogba ewon alaroye,0,yoruba "Wọn fẹsun kan Ihetuge Ifeanyi pe o ji ẹrọ ibaraẹnisọrọ ti iye owo rẹ to N950,000. Adajọ ile ẹjọ naa, O.L. Oke ni ki ọdaran ọhun lọ fi ẹwọn jura fun ọdun mẹrin gbako lẹyin to jẹwọ pe oun jẹbi ẹsun naa ti wọn kan an. Ṣugbọn Adajọ ọhun fi kun un pe o lee san owo itanra ti iye rẹ to N150,000 dipo ko lọ fi aṣọ penpe roko Ọba. Ọkunrin naa di ẹni to n kawọ pọn rojọ niwaju adajọ lẹyin ti wọn fẹsun ole jija, ile fifọ ati igbimọpọ hu iwa ọdaran kan. Agbofinro to gbe ọrọ naa lọ silẹ ẹjọ, E.O Adaraloye sọ pe Ifeanyi atawọn miran ti wọn ti na papa bora huwa ọdaran naa ni nnkan bi aago mẹta oru ni adugbo Femi Oni, to wa ni opopna Arinko, ni Otta, iyẹn ni ipinlẹ Ogun. Adaraloye sọ pe Ifeanyi atawọn ẹmẹwaa rẹ fọ ile ọkunrin kan ti orukọ rẹ n jẹ Olayinka Odunniyi, ti wọn si ji ẹrọ ilewo iPhone atawọn ẹrọ ilewọ olowo gọbọi miran. O ni iwa ti wọn hu lodi si ofin to rọ mọ iwa ọdaran ipinlẹ Ogun ti wọn gbe kalẹ lọdun 2006. Níbo ni owó Crowd 1 ti wá? Níbo ni owó Crowd 1 ń lọ? ni ìbéèrè tí spọ̀ ń bèèrè",0,yoruba JAN MOIR: Meghan's got all she wanted and Harry's given up so much https://t.co/JivC6MyyUg via @user 🤔👸🏽😒 Àpọ́nlé ò sí fún obìnrin tí ò ládé orí. / There is no honour for a woman with no crown (her own husband). #Yoruba 👑😬,0,yoruba "se, Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gblọ yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi.",0,yoruba Mo fi ìkíni ọlọ́yàyà ránṣẹ́ síi yín o... 😊 Ṣé ẹ gbádùn òpin ọ̀sẹ̀ t'ó kọjá? Gbogbo ìdáwọ́lé wa lọ́sẹ̀ yí á yọ'rí sí rere lágbára Ọlọ́run! 🙏 #yoruba #iwure #adura #ojumoire #oseayo #oseaseyori #owurolojo #ojoaje #omooodua #metrovibes #kaarọoojiire https://t.co/RyVcwRkwQq,0,yoruba "Jọwọ dariji mi, Yoruba mi ko dara. Nwa fun awọn onijo lati jo Crypto Crawl fun aye lati win 200 #XRP. Fi fidio ranṣẹ si ati taagi @user lati gba 5 #XRP Ipenija 200 #XRP 'fidio ti o dara julọ' pari ni Oṣu Kẹwa Ọjọ 31 #Africa #Yoruba #global #dance #fun https://t.co/TcLGP0Nuki",0,yoruba iṣẹ́ ṣẹlẹ ni Lagos ti gbogbo eniyan sọ o dara. (2022),0,yoruba "RT @user: Ki olodumare to wa si ipa rere """"""""""""""""@user: @user Ibo la fẹ́ gbé e gbà?""""""""""""""""",0,yoruba Osun Crisis Update: Bola Tinubu ní wọn kò pé òun sí ìpàdé náà ni òun kò ṣe báwọn péjú síbẹ̀.,0,yoruba oruko temi ni abiola omo shabi omo bibi ilu eko epe ni awa ti wa won bi mi si ebute metta,0,yoruba "Ileeṣẹ ọlọpaa gbe Tajudeen Oladunni, ẹni aadọta ọdun; Saburi Lawal, ẹni ọdun mẹtadinlogoji; Ojo Joshua, ẹni ọdun mẹẹdọgbọn; Adekunle Olanrewaju, ẹni ọdun mejidinlogoji. Pẹlu Olagunju James, ẹni ọdun mẹrinlelogoji; Rasaq Yahya, ẹni ọdun mejilelọgbọn ati Olaide Olawuyi, to jẹ ẹni ogun ọdun lọ si ile ẹjọ lori ẹsun mẹfa ọtọọtọ to da lori i iditẹ, ṣiṣe dukiya lofo ati iṣekupani. Fulani-Yoruba Crisis: Oba Soun ló fí mi jẹ ọba Sabo ni Ogbomọṣọ- Alh Haruna Bala Abdulsala Adajọ I.O Osho ko gba ẹbẹ awọn afurasi naa lati gbe ẹjọ naa lọ sile ẹjọ mii. O paṣẹ pe ki ileeṣẹ ọlọpaa da iwe ipẹjọ wọn pada si ọọfisi awọn agbefọba nipinlẹ Ọyọ fun amọran to peye lori ẹjọ naa. Arabinrin Osho wa sun igbẹjọ ọhun siwaju di ọjọ kọkanla, oṣu Karun un, ọdun ti a wa yii. Saaju ni agbẹjọro fun ijọba, Foluke Oladosu ti kọkọ sọ fun ile ẹjọ naa pe awọn afurasi naa lẹ idi apo pọ lati ṣiṣẹ laabi. Ọladoṣu ni l'ọjọ kejila, oṣu Keji, ọdun yii, ni nnkan bi i aago mẹwa owurọ ni awọn afurasi ọhun ṣekupa Arakunrin Adeola Shakirudeen lẹyin ti wọn luu bi i ejo aijẹ. Bakan naa ni ileeṣẹ ọlọpaa fi ẹsun kan awọn eeyan naa pe awọn afurasi ọhun tun ṣekupa awọn eeyan mọkanlelọgbọn miran. Femi Falana, Endsars: Awolowo kò fáààyè gba kí èèyàn máa yàgò fún Màálù nígboro Wọn fi kun ọrọ wọn pe awọn afurasi naa dana sun ile meji kan to jẹ ti Arakunrin Adelabu Ibrahim, ti wọn si fi dukiya ti o to bi i aadọta milliọnu naira ṣofo. Ileeṣẹ ọlọpaa tẹsiwaju wi pe, awọn afurasi naa tun dana sun ile kan to jẹ ti Osuolale Akindele, ti wọn si ba dukiya ti o to ogun milliọnu naira jẹ. Ileeṣẹ ọlọpaa ṣe alaye pe awọn ẹsun naa tako agbekale ofin ọdun 2000, eyii to n risi iwa ọdaran nipinlẹ Ọyọ. #EndSars Ogbomoso: Èmí kò ní kí wọ́n pa ọlọ́pàá tó pa Isisaka, ṣùgbọ́n...- Ramota, Iya Isi",0,yoruba adetola ni oruko mi abi mi si ebutemetta isaleeko ni agbe bi baba mi ebutemetta ni agbe bi iya mi omo igbomina ni mi,0,yoruba "Oludije ẹgbẹ oṣelu PDP ninu idibo aarẹ dun 2019 Naijiria n tako ijaweolubori aarẹ Buhari Igbẹjọ yi n waye lẹyin ti Atiku kọwe kotẹmilọrun lori idajọ ile ẹjọ kotẹmilọrun to ti waye ṣaaju. Ẹgbẹ oṣelu PDP lo kede ọrọ yi loju opo Twitter wọn ti wọn si ni ''asiko to bayi lati doola Naijiria'' Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹgbẹ alatako naa ni awọn ṣetan lati tako esi idibo to gbe aarẹ Buhari wọle lọdun 2019. Ninu iwe kotẹmilọrun ti wọn fi ṣọwọ sile ẹjọ to ga julọ, wọn ni igbimọ igbẹjọ idibo naa ṣe aṣiṣe ninu idajọ wọn. Bakan naa ni wọn sọ pe aarẹ Buhari ko sọ ootọ fun INEC nipa iwe ẹri rẹ to fi kalẹ. Loṣu kẹsan, igbimọ olugbẹjọ idibo fọwọ rọ ẹsun ti Atiku gbe wa si iwaju rẹ pe ko fi ẹsẹ mulẹ to. Atiku ati ẹgbẹ oṣelu PDP ni awọn fẹ ki ile ẹjọ to ga julọ wọgile idajọ ile ẹjọ kotẹmilọrun, ki wọn si kede Atiku gẹgẹ bi aarẹ.",0,yoruba "Ọdẹ ni bàbá Ṣọ̀ún Ogunlọlá, ọmọ Ìbàrìbà sì ni. Ó dẹ̀ igbẹ́ dé Ìrẹ̀sà níbi tí ó ti fẹ́ ọmọ Arẹ̀sà; Èsúu. #Ogbomoso",0,yoruba Ọ̀yọ́ jẹ́ ilẹ̀ agbègbè tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa òkè: ti o.,0,yoruba ni ìgbà mi owó àkokò eyti o gbe lori ọ̀run dídì.,0,yoruba ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìṣẹ̀: ti o nuni ti o nuni ti.,0,yoruba "Wọn fẹsun kan awọn ọmọogun Cameroun pe wọn nwọ Naijiria lai gbasẹ́ Eyi lo si mu ki awọn asofin agba orilẹede Naijiria kesi minisita fun ọrọ aabo lati farahan niwaju igbimọ rẹ ko lee salaye lori isẹlẹ naa. Lọjọ kẹẹdọgbọn osu kinni ọdun 2018 ni ọgọrin awọn ọmọogun orilẹede Cameroon tasẹ agẹrẹ wọ aala ilẹ Naijiria lẹkun Danare-Daddi/Danare-Bodom ni ibi ti wọn ti ji awọn eeyan marun gbe. Ọpọlọpọ awọn eeyan agbegbe guusu Cameroun lo ti wọ Naijiria nitori wahala abẹle to n sẹlẹ lorilẹede wọn Igbesẹ yi si lawọn sẹnatọ ọhun ri gẹgẹbi iwa titapa si ofin orilẹede Naijira. Bakanna lawọn asofin agba yi tun kesi ileesẹ ọmọogun Naijiria lati tubọ se alekun awọn ọmọogun ti yoo maa daabo bo aala ilẹ Naijiria ati awọn ẹnu ibode rẹ gbogbo. ọkan-o-jọkan awọn asofin to sọrọ nibi ijoko ile lọjọru ni wọn koro oju si ohun to sẹlẹ yi. Bi awọn eeyan se n wọ awọn ileto to wa ni aala Naijiria ati Cameroun se n pọ sii ni wahala abo pẹlu n yọju Ninu ọrọ rẹ, Sẹnatọ Sam Egwu ni, o yẹ ki ile o bi minisita fun ọrọ abo nipa idi ti yoo fi la oju rẹ silẹ ti orilẹede miran yoo fi wọ orilẹede Naijiria, ti yoo si maa tẹẹ basubasu. Ọrọ asepọ laarin orilẹede mejeeji yii ti n ni gbọnmisi-omi o too ninu lẹnu lọwọlọwọ yii, eyi ti ko si sẹyin wahala abẹle to n waye lorilẹede Cameroun nitori bi ẹkun guusu orilẹede naa se n beere fun ominira. Isẹlẹ yi ti sọ eeyan bii ẹgbẹrun mẹwa ni guusu Cameroon di alarinkiri ati atipo lawọn ileto kaakiri ipinlẹ Cross rivers lorilẹede Naijiria.",0,yoruba "Reno Omokri , olùrànlọ́wọ́ ààrẹ àná , fi ẹ̀sùn kan Ezekwesili wí pé ẹgbẹ́ olóṣèlú APC ni ó ń lò ó fi ba ìjọba tí ó wà lórí àpèré jẹ́ àti láti “ yẹpẹrẹ """""""" ìjọba Ààrẹ Jonathan , nípa èyí náà ni ó fi lànà fún APC láti “ gba ọ̀pá àṣẹ . """"""""",0,yoruba Àwọn ọmọ ìlú orí ayélujára fajúro sí ìṣẹ̀lẹ̀ náà lórí ẹ̀rọ alátagbà :,0,yoruba "Èkó yii nípa ọ̀rọ̀ ìlú ni nfàn ojú kakaaki. Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba àlùfáà. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa aráyé: ti o pẹ jú nìlọ̀ ni ọ̀nà tí ẹ̀ọ́ kan máa ń gbé ìyẹ̀ alẹ́.,0,yoruba "Bákan náà ni ìgbìmọ̀ aláṣẹ ọ̀hún tún ni òun kò fọ̀wọ́ sí ẹgbẹ́ akẹ́kọ̀ọ́ kankan ni il'é ìwé náà tó fi mọ́, ASUU, NASU, SSANU, NAAT. Àtéjáde tó jẹyọ láti ọwọ́ agbẹnusọ ilé ìwé náà Bode Olofinmaugun ló fẹ̀sùn kan pé òun fura pé àwọn kan dìde láti da ètò ẹ̀kọ́ rú ni ilé ìwé náà tí wọ́n sì ń fi ẹ̀mí àti dúkíà àwọn ènìyàn sínú ewu láti bi ọ̀sẹ̀ kan sẹ́yìn. Ẹ̀wẹ̀, ó rọ gbogbo akẹ́kọ̀ọ́ láti kúrò nílé ẹ̀kọ́ ní kíákíá. Sáájú ni ìpàdé laáárìn àwọn ìgbìms olórí ẹgbẹ́ òsìṣẹ́ ilé ẹ̀ka náà àti àwọn ìgbìmọ́ aláṣẹ ilé ẹ̀kọ́ náà forí sọ́pọ́n, bí àwọn asójú ẹgbẹ́ tó wá fún ìpàdé náà ṣe bínú jáde kúrò nínú ìpàdé ọ̀hún bí wọ́n ṣe kọ̀ látiṣe ǹkan tí wọ́n ń bèèrè fún. aaaaaaaaaaaaaaa Ìròyìn tún fi yé ni pé, àwọn èèkàn mííràn tó tí bá gómìnà ṣe ìpàdé pẹ̀lú bínú jáde nínú ìpàdé náà nítórí bi gómìnà ṣe fi ààké kọ́rí lórí ọ̀rọ̀ náà tó sì ks láti ṣe ǹkan tí wọ́n ń fẹ́, lára rẹ̀ ní owó oṣù mẹ́tà tí wọ́n jẹ lọ́dún 2019, owó oṣù mẹ́rìnlá tí wọ́n yọ nínú owó oṣù ati owó ìfẹ̀yìn tì. Budo Ikoko water problem: Ìyàwó wa ti sá lọ kúrò ní Asa nítorí àìsí omi- Alhaji Sunmonu Àwọn olórí òṣìṣẹ́ ní ilé ìwé náà lásìkò tí wọ́n ń bá àwọn oníròyìn sọ̀rọ̀ jẹ́jẹ̀ẹ́ pé àwọn kò ní sinmi ìfẹ̀hónú hàn títí tí ìjọba yóò fi ṣe ǹkan tí àwọ́n ń fẹ́. Bákan náà ní wan bu ẹnu àtẹ́ lu ìgbìmọ̀ aláṣẹ ilé ẹ̀kọ́ náà tí kò le san àwọn owó tí wọ́n yọ nínú owó oṣù pàda láti ọdún 2018. Àtẹ̀jádé ìjọba apapọ̀ lórí ọ̀rọ̀ Pantami fihàn pé wọ́n ń káànú ìgbésùnmọ̀nmí- PDP Ẹjọ́ ń bẹ lọ́run fún gbogbo ẹ̀yin tí kò wàásù fáwọn tó ń tẹ lé yín lórí Instagram àti Facebook- Mike Bamiloye Olólùfẹ́ Naira Marley kọ sẹ́nu tírélà nítorí ₦500 tó fẹ́ gbà lọ́wọ́ rẹ̀ Adunni Olorisa, obìnrin òyìnbó tó di ìyàwó òrìṣà nílẹ̀ Yorùbá títí di ọjọ́ ogbó Àwọn agbébọn ti pa mẹ́ta nínú àwọn akẹ́kọ̀ọ́ fásitì Greenfield tí wọ́n jí gbé ní Kaduna ‘Jí foonu ọkọ rẹ̀ wò, kóo fi ẹ̀wọ̀n jura’ Àwọn òṣìṣẹ́ fásitì EKSUK gbé iléèwé tì pa nítorí àjẹẹ́lẹ̀ owó oṣù, àjẹmọ́nú Nnkan ko rọgbọ ni saa yii ni fasiti ipinlẹ Ekiti, EKSU pẹlu gbọnmọgbọnmọ wahala oṣiṣẹ nibẹ. Lọwọ yii awọn oṣiṣẹ fasiti ipinlẹ Ekiti ko tii jami lori iyanṣẹlodi ati iwọde ti wọn n gunle nibẹ lati beere fun awọn ajẹẹlẹ owo oṣu wọn kan eyi ti awọn alaṣẹ ẹgbẹ oṣiṣẹ nibẹ ni awọn n beere fun. Ẹnu iloro ọgba fasiti naa to yẹ ko jẹ abawọle sinu awujọ ikẹkọọ ni wọn ti sọ di ibudo igbafẹ nibi ti wọn ti gba awọn onilu ti wọn si n jo. Oniruuru orin ọtẹ ati eebu lo n gbode nibẹ ti wọn n kọ tako ijọba ipinlẹ naa atawọn alaṣẹ fasiti ọhun, ti awọn oṣiṣẹ naa si n jo lati wọde fun ajẹẹlẹ owo oṣu ati ajẹmọnu gbogbo ti wọn n beere fun. Iwọde wọn yii ko jẹ ki ohunkohun tabi ẹnikẹni wọle tabi jade lẹnu iloro ileewe naa to si ti mu ki ẹkọ kikọ. aaaaaaaaaaaaaaa Ọkan lara awọn oṣiṣẹ fasiti naa, Ọgbẹni Azeez Aguda to ba awọn oniroyin abẹle kan sọrọ ṣalaye pe ohun ti wọn n ja fun ni sisan ajẹẹlẹ owo oṣu wọn fun oṣu ikeje, ikẹjọ ati ikẹsan ọdun 2018. Wọn tun n beere fun dida owo alajẹṣẹku kọpuretifu ati owo ifẹyinti wọn pada, igbayegbadun awọn oṣiṣẹ ati dida awọn oṣiṣẹ ti wọn ys niṣẹ pada. Akomolede ati Aṣa lori BBC Yoruba: Ẹ̀yà Ara Ifọ̀ ní olùkọ́ Adedokun kọ́ wa",0,yoruba "Gbajúgbajà ife ẹ̀yẹ mẹtalelogun ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ni Serena Williams ti gba ninu ìdíje tẹniisi lágbáyé. Agba ọjẹ elere idaraya tẹniisi sọ eleyi di mimọ, lẹyin ọjọ marun un ti aìsàn ibà yọwọ́ rẹ láwo ìdíje Madrid Open. Igbesẹ yii ti jẹ ki ọpọlọpọ maa ro pe Serena tun lee ma kopa ninu idije French Open ti yoo bẹrẹ lọjọ kẹtadinlọgbọn osu yii. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Serena ti gba ife ẹyẹ Italian Open nigba mẹrin ọtọọtọ. Serena ti sọ tẹlẹ l'ọjọbọ ọṣẹ to kọja wipe, oun nilo akoko diẹ si ki oun to le ṣetan fun idije tẹniisi ori amọ. Serena ti jáwé olúborí lẹ́ẹ̀rìn ọ̀tọ̀ọ̀tọ́ nínú ìdíje Italian Open Ní oṣù kẹta ni Serena pada sori papa, ni idije tẹniisi to wáyé ni Indian Wells ati Miami, léyìn tó bímọ. Gbajúgbajà ife ẹ̀yẹ mẹtalelogun ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ni Serena Williams ti gba, ninu ìdíje tẹniisi lágbáyé.",0,yoruba 2023 Elections: Gọngọ sọ! Adarí ìpolongo ètò ìdìbò Tinubu fi ẹgbẹ́ òṣèlú APC sílẹ̀,0,yoruba Àlàyé bí Ọlọ́run Olódùmarè ṣe dá ayé gẹ́gẹ́ bí ọjà tí ọmọ aráyé wá ná ni ẹsẹ̀ Ifá yìí ń sọ fún wa. Wọ́n sì lá ò mọ Ọlọ́run. #YorubaMoOlorun,0,yoruba 2022 Prophecies: Àwọn ólọ́pàá Ghana kìlọ̀ fáwọn òjíṣẹ́ Ọlọ́run làti ṣọ́ ẹnu wọn nípa sísọ àsọtẹ́lẹ̀ fún ọdún 2022,0,yoruba ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jẹ́ dára jù...,0,yoruba "RT @user: #KOKOINUIWEIROYIN: APO IKOWOSI ILE OKERE, EGBE OSELU PDP PE FUN FIFI OWO SIKUN OFIN MU ASIWAJU BOLA AHMED TINUBU",0,yoruba Kí ni à ń pè ẹranko inú àwòrán yìí lédèe Yoòbá? #ibeere #Yoruba https://t.co/daLKZuWQHP,0,yoruba "Àìtètè mú olè, olè á mú olóko.",0,yoruba "Muhammadu Buhari pada si Naijiria Ni bi aago mẹfa kọja ogun iṣẹju ni ọkọ baalu to gbe aarẹ balẹ si papakọ ofurufu Nnamdi Azikwe ni olu ilu orilẹede Naijiria, Abuja nirọlẹ ọjọ Aiku. End of Twitter post, 1 Ọjọ kẹẹdọgbọn oṣu kẹrin to lọ ni Aarẹ Buhari rinrin ajo lọ si ilẹ Gẹẹsi lẹyin to ṣabẹwo si ilu Maiduguri tii ṣe olu ilu ipinlẹ Bornu. '500 level'' ni mo wà nígbà tí mo di adélé Ọba' Helen Paul sọ idi tó fi gba orúkọ ní kékere Ṣaaju abẹwo rẹ si ilu Maiduguri, Aarẹ Buhari kọkọ wa si ipinlẹ Eko nibi ti o ti ṣi awọn akanṣe iṣẹ kan ti ijọba ipinlẹ naa ṣe. Ẹwẹ, oludamọran aarẹ lori ọrọ iroyin, Femi Adesina sọ oko ọrọ sawọn oniroyin ori ayelujara kan to ni wọn ti n kọroyin pe Aarẹ Buhari lọ gba itọju nilẹ Gẹẹsi ni. Ọgbẹni Adeṣina beere lọwọ wọn bo ya wọn o tọrọ aforiji lọwọ Aarẹ Buhari ati aw\pm ọmọ orilẹede Naijiria nibayii ti aarẹ ti pada si Naijiria.",0,yoruba Bí Ògbómọ̀ṣọ́ ṣe di Ògbómọ̀ṣọ́ #Ogbomoso,0,yoruba láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba ní nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o nuni ti o ṣe pataki.,0,yoruba "RT @user: Amin Ase!""""""""""""""""""""""""""""""""@user: Àtùpà ayọ̀, ire, ògòo ayé mi á bùyọ, kì yóò kú. #Fitila #Yoruba""""""""""""""""""""""""""""""""",0,yoruba @user ṣàngbà fọ́! Àjà ò fura àjà jìn! iná wá bọ́ sórí aṣọ gbáà.,0,yoruba "BBC African Footballer: Salah gba àmì ẹ̀yẹ̀ lẹ́ẹ̀kan síi Mohammed Salah lo tun gbami ẹyẹ BBC Salah to jẹ ọmọ orilẹede Egypt to si n gba bọọlu fun ikọ Liverpool nilẹ Gẹeṣi naa lo gba ami ẹyẹ ọhun lọdun to lọ. Salah to jẹ ọmọ ọdun mẹrindinlọgọn gba ami ẹyẹ naa mọ Medhi Benatia, Kalidou Koulibaly, Sadio Mane ati Thomas Partey lọwọ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Nigba ti o n ba BBC sọrọ, Salah ni inu oun dun lati gba ami ẹyẹ naa lẹẹkan si. Koda o ni inu oun yoo dun gan an t'oun ba tun le rii ami ẹyẹ naa gba lọdun to mbọ. Ami ẹyẹ BBC Salah gba goolu mẹrinlelogoji sawọn fun Liverpool ni saa ere bọọlu afẹsẹ̀gba to lọ, lẹyin to kopa ninu ifẹsẹwọnsẹ mejilelaadọta. O tun fakọyọ ninu idije Champions League bi Liverpool ti kopa ninu aṣekagba idije ọhun.",0,yoruba "fè se, Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa aráyé: ti o ní wúlò.",0,yoruba ìròyìn. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba "Ko si si idi meji ti wọn so mọ ọrọ yii ju edeaiyede lori ikọlu awọn ajeji lorilẹede South Africa lọwọlọwọ. Amọṣa, Ijọba apapọ orilẹede Naijiria ti wa bọ sigboro aye bayii lati da omi tutu si iroyin naa eyi ti wọn pe ni iroyin ẹlẹjẹ. Ni ọjọ Satide ni minisita fun eto iroyin ati aṣa gbe atẹjade kan jade pe ko si ohun to jọ ibugbamu ado oloro ni ileeṣẹ aṣoju ijọba orilẹede South Africa ni Naijiria to wa nilu Abuja. O ni fidio ibugbamu ado oloro ti awọn eeyan kan n gbe kiri lori itakun ayelujara kii ṣe ti ileeṣẹ aṣoju ilẹ South Africa bi ko ṣe ti ibugbamu to waye ni ibudo Emab Plaza, nitosi Banex, nilu Abuja loṣu kẹfa ọdun 2014. Lai Mohammed to di iroyin ofege naa ru iṣẹ ọwọ awọn alatako ṣalaye pe ọgbọn ati da omi alaafia iṣejọba ru ni awọn to gbero fidio naa n da. Alhaji Lai Mohammed wa rs awọn ọmọ orilẹede Naijiria lati maa woye gbogbo iroyin ti wọn ba n ri gba lori ayelujara nitori oye lagba n wo.",0,yoruba "Ọ̀pọ̀ ìgbà láwọn èèyàn máa ń lọ lúwẹ̀ẹ́ nínú adágún odò ní ilé ìtura Ní kété tí wọn sì rí òkú ọkùnrin náà ni wọ́n késí àwọn ọlọ́pàá, tí wọn yọ òkú náà, tí wọ́n sì gbée sílé ìwòsàn ní ọjọ́ kejọ̀, osù kẹrin tí ìsẹ̀lẹ̀ náà wáyé. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Sòwòrẹ́: Èmi kò leè bá jẹgúdújẹrá APC àti PDP se pọ̀ Alukoro iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní ìpínlẹ̀ Èkó, tó fìdí ìsẹ̀lẹ̀ náà múlẹ̀ ní, wọn kò tíì mọ ẹnití ọkùnrin naa jẹ́ àti ibití ó ń gbé, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò rí ojú ọgbẹ́ ní ara òkú náà. ""Ní kété tí ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣẹlẹ̀ ni obìnrin tí wọn dìjọ wá ti fẹsẹ̀ fẹ́ẹ, tí wọn kò sì rí ẹ̀rọ ìbáraẹnisọ̀rọ̀ alágbèéká ní ara òkú náà láti mọ ẹni tó jẹ́. A sì ti gbé òkú náà sí ibùdó ìgbókùúsí tó wà ní ilé ìwòsàn ìjọba ní ìlú Badagry.""",0,yoruba àgbà ri pe ṣe iyalẹnu wey ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba ibile. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìṣẹ̀: ti o nuni ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ài: ti o nuni ti o ní wúlò.,0,yoruba ìbadandun. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba "Fox is called """"""""""""""""Kọ̀lọ̀kọ̀lọ̀"""""""""""""""" in Yorùbá. #YorùbáAnimals #fox #yorubalessons #yorubaforbeginners #InYoruba #LanguageLearning #Yorùbá #WordOfTheDay #IYIL2019 https://t.co/kWTirpSfz5",0,yoruba "Abẹwo ti a ṣe si awọn ibudokọ kan l'owurọ Ọjọbọ lo fi idi ẹ mulẹ pe pupọ ninu awọn awakọ naa ni ko tii gbọ nipa aṣẹ ile ẹjọ lori awọn alakoso to n gba owo lọwọ ni ibudokọ. Lori iro: Ká ni àwọn Òbí mi gbà fún mí, èmi àti Sunny Ade á jọ máa 'Compete- Baba Lórí ir Bo tilẹ jẹ pe pupọ ninu awọn awakọ naa ni ko fẹ fi oju han tabi da orukọ wọn; Awọn ti o ba wa sọrọ labẹ aṣọ ṣalaye fun akọroyin wa pe gbogbo ohun ti yoo mu itẹsiwaju ati irọrun ba iṣẹ ọkọ wiwa ni awọn fi ọwọ si. Ọkan lara awọn awakọ naa to n na agbegbe New Garrage si Iwo Road ṣalaye pe oun ko gbagbọ wi pe o ṣeeṣe ki awọn maa ṣiṣẹ awakọ nipinlẹ Ọyọ ki ẹnikẹni ma si gba owo Ibudokọ lọwọ wọn. O ni nitori gbogbo ibi ni wọn ti n gba owo lọwọ awakọ lorilẹ-ede agbaye, ọna ti wọn fi n gba a kan yatọ sira wọn ni. Idahun si awọn ibeere ti a bi awọn awakọ to n na Challenge, Mọlete, Gate titi de Mọkọla Roundabout naa tun fi idi ẹ mulẹ wi pe pupọ wọn ninu ko tii gbọ nipa aṣẹ ti ile ẹjọ pa. Bẹẹ si ni a ri melo kan lara awọn alakoso ibudokọ naa ti wọn ba iṣẹ wọn lọ ni awọn agbegbe ti a de l'owurọ Ọjọbọ. Oladele Ogbeyemi Albert: Irin tí mò ń lò máa ń bá mi sọ̀rọ̀ nínú ẹ̀mí kí ń tó gbẹ́ wọn sóh Titi di asiko ti a kọ iroyin yii, gomina ipinlẹ Ọyọ, Onimọẹrọ Ṣeyi Makinde ati igbimọ alakoso ibudokọ nipinlẹ Ọyọ ko ti i fesi lori aṣẹ ti ile ẹjọ pa. L'ọjọ kẹtadinlogun, oṣu keji, ọdun 2021 ti agbekalẹ awọn alakoso ibudokọ pe ọdun kan gerege ni ile ẹjọ giga ipinlẹ Ọyọ wọgile e pẹlu alaye wi pe igbesẹ naa ko ni atilẹyin ofin. Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Bolanle Adekanmi kọ́ wa nípa oríṣíi Àròkọ Yorùbá tó wà",0,yoruba ìwé orisirisi lo je gbogbo ise ibile tèmi.,0,yoruba "Will be referred to as, """"""""""""""""ọmọ ọbàkan"""""""""""""""". A rival wife, is referred to as """"""""""""""""orogún"""""""""""""""" or, ọbàkan (on a lighter tone). Children of the agbo ilé, are referred to as, ọmọ bàbá/ìyá lágbájá (son/daughter of so so and so). Cousin related description: ọmọ àbúrò/ẹ̀gbọ́n bàbá/ìyá mi",0,yoruba "Ajọ to n se akoso eto igbohunsafẹfẹ nilẹ United Kingdom ti kesi ileesẹ mohunmaworan pasitọ kan ni Naijiria, Chris Oyaklome lati sanwo itanran. Ileesẹ mohunmaworan naa, Loveworld Television Network, ni wọn ni ko san owo itanran ẹgbẹrun lọna marundinlaadoje pọnun 125,00. Ẹsẹ ti wọn ka si ọrun ileesẹ agbohunsafẹfẹ naa ni pe o gbe eto kan sita lori ọrọ ẹsin, ninu eyi ti wọn ti n sọ awọn ofege iroyin nipa arun Coronavirus lai daabo bo awọn onworan wọn. Ajọ naa ni igba keji ree laarin ọdun tileesẹ naa yoo tako ofin to rọ mọ gbigbe ojulowo iroyin lai ni abula sori afẹfẹ, eyi to n tako iroyin gidi nipa arun Coronavirus. ""A ri awọn iwa riru ofin yii bii eyi to gbopọn pupọ ati iwa asise mase to n foju han lọpọ igba eyi to mu ka ta ileesẹ igbohunsafẹfẹ naa loji owo."" Ileesẹ ijọ UK to n sakoto awọn ileesẹ igbohunsafẹfẹ naa ni oun to n kọ oun lominu ni pe igba akọkọ kọ ree tileesẹ amohunmaworan Loveworld yoo tasẹ agẹrẹ si ofin awọn. O ni irufẹ iwa arufin naa ti kọkọ waye lọdun 2020, tileesẹ tẹlifisan Loveworld si fi ọwọ gbaya pe oun yoo mu ibọwọ fun ofin lọkunkundun lai se bẹẹ.",0,yoruba ọdún ìbílẹ̀ àti ìṣẹ̀ṣe yóò mú kí ọrọ̀ ajé orílẹ̀èdè wa ó lọ sókè lálá,0,yoruba ènìyàn: ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba a ní nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ àti ìbi tí wọn wà.,0,yoruba "Àkóbì níjó òní nípa àbá èwe. Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.. Eyi ni adetokun ninu ilu.",0,yoruba yóò ri A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba ìròyìn. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba Ilé - iṣẹ́ UK Nílé pe àìfúni ní ìwé ìrìnnà náà padà .,0,yoruba Kílódé tí #BokoHaram o kọlu #aso #rock. Kí wọ́n yé pa àwọn aráàlú tí ọ̀ mọwọ́-mẹsẹ̀.,0,yoruba Ìròyìn tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ẹkọ́: ti o jare. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò.,0,yoruba ìdílé. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ài: ti o pataki.,0,yoruba agbègbè tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tó gbogbo àwọn aráyé.,0,yoruba Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìṣẹ̀: ti o ṣe pataki.,0,yoruba ènìyàn ni ó pa Bàbá lo tun se lọ.,0,yoruba "Àwòrán láti ọwọ́ọ Miccaela , Wikimedia Commons .",0,yoruba ìròyìn tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ẹkọ́: ti o nuni ti o nuni ti o ní wúlò.,0,yoruba "Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ""Ẹni tí kò ṣe bíi aláàárù l'Oyingbo... Wọn maa n ti ilu kan lọ si ekeji lati wa ti aje ṣe, ti ọpọ ajeji si maa n di ọmọ onilu lẹyin o rẹyin nigba ti Ọba oke ba bukun wọn. Sugbọn nigba miran, ọpọ ọmọ Yoruba to ba wa isẹ aje lọ silu miran kii gbagbe ile nitori igbagbọ wọn ni pe ọmọ to ba sọ ile nu, o so apo iya kọ. Koda, wọn a maa figba gbogbo ranti pe ko si ibi to dabi ile. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Bẹẹ lọrọ ri pẹlu ọkunrin kan ti wọn n pe ni Adegbọrọ to n gbe ni ilu Ibadan. Lasiko ti nnkan le koko fun Adegbọrọ, ti ko ri ba tise, ti ko ri ọna gbegba, ti isẹ n sẹ ẹ gidi, lo ba ronu jinlẹ lori ọna abayọ si ipọnju to ba a yii. Adegbọrọ di igba ati agbọn rẹ, to si gba ilu Eko lọ lati wa isẹ Aje ṣe, ko le e riba ti se, ko si ri ọna gbegba. Nigba to de ilu Eko, ọja Oyingbo lo balẹ si, to si n sisẹ alabaru nibẹ, bo se n fi ori rẹ gbe apo ata, lo n gbe apo ẹwa, irẹsi, apo elubọ, Sẹmo, agbado ati bẹẹ bẹẹ lọ. Ìtàn Mánigbàgbé: Ìtàn Adegbọrọ kọ́ wa láti ṣiṣẹ́ kára pẹ̀lú ìforítì Nigba to ya, pẹlu aforiti ati iṣẹ aṣekara, to si mọ baa ṣe n pọn omi silẹ de oungbẹ, Adegbọrọ fi owo pamọ, to si ra ọmọlanke lati maa fi ṣe aaru dipo ori to fi n ru ẹru. Bakan naa ni eyi yoo mu ki owo to n pa wọle ru gọgọ si. Laipẹ laijinna, Ọba oke bukun Adegbọrọ, to si ra ọmọlanke bii meje kun eyi to ni. Awọn ọmọlanke naa si lo fi n haya fun awọn alabaru miran lati maa sisẹ. Ọjọ n gun ori ọjọ, osu n gori osu, Adegbọrọ lo ọdun mẹjọ ni sja Oyingbo, to si di gbajumọ nidi isẹ wiwa ọmọlanke. Asiko yii si lo ra ọkọ akẹru to si lọ kọ ọkọ wiwa. Adegbọrọ n mojuto isẹ ara rẹ funra ara rẹ, ti ko si fi ọwọ mẹwẹẹwa jẹun. Nigba ti yoo si fi lo ọdun mẹrin nidi fifi ọkọ ko ẹru, Adegbọrọ tun ra ọkọ akẹru mẹfa sii, eyi to tun gba awọn awakọ si lati maa fi bawọn eeyan ko ẹru. Nigba to ya, Adegbọrọ ranti pe ile ni abọsinmi oko, to si gba ilu Ibadan, tii se ilu abinibi rẹ lọ lati kọ ile. Ile awodamiẹnu, ile awosifila si ni Adegbọrọ kọ si adugbo ọja Ọba. Ìtàn Mánigbàgbé: Ìtàn Adegbọrọ kọ́ wa láti ṣiṣẹ́ kára pẹ̀lú ìforítì Asiko yii ni irawọ Adegbọrọ bẹrẹ si ni tan, ti ogo rẹ n bu yọ nilu Ibada. Ọpọ eeyan si n tọ ọ wa pe ko sọ asiri owo rẹ fun awọn nitori awọn naa fẹ dabi rẹ, se aye ki bani ri wahala ẹni, sokoto to balẹ nikan ni ọmọ araye n ri. Adegbọrọ wa da wọn lohun pe ti wọn ba fẹ lowo, ki awọn naa kalọ si ọja Oyingbo. Ki wọn wa fi ori ru aaru, amọ ọpọ wọn lo fi ọwọ osi ta ika oṣi danu pe, laalae, awọn ko le e ṣiṣẹ aaru gbigba. Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ""Ẹni tí kò ṣe bíi aláàárù l'Oyingbo... Idi si re e ti Adegbọrọ naa fi maa n da wọn lohun pe: ""Ẹni ti ko ba ṣe bii alaaru l'Oyingbo, ko lee ṣe bii Adegbọrọ l'ọja Ọba"". Eyi to tumọ si pe, ikoko ti yoo jẹ ata, idi rẹ yoo kọkọ gbona, ti a ko ba si jiya to kun agbọn, eeyan ko ni jẹ aye to kun aha. Awọn ẹkọ ti itan Adegbọrọ kọ wa:",0,yoruba a ò ṣe bí ìṣẹ̀dá wa ṣe gbà bíi wọn là ń ṣe a dẹ̀ lá ò sí lábẹ́ wọn mọ́ a lá a ti gba,0,yoruba ìròyìn. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni A tí.,0,yoruba "Gbọ́ orin Fẹlá, kí o mọ́ ìtumọ̀ lady. Ò bà mí lọ́kàn jẹ́ nítorí wípé àwọn ọmọge ìsẹ̀hìn pátá ti di Lady. Lady ò ní àṣàa wa, British ni Lady.",0,yoruba ki odun tuntun ye wa sowo ki oye wa si omo ki o gba wa lowo akindanidani oba nebukudeneza ilu nijeria ki jamba boko haramu dekun,0,yoruba "Ajọ tó ń gbógun ti ìwá àjẹbánu àti gbigbọ́ ẹ̀sun ara ìlú ní ìpínlẹ̀ Kano ló fẹ̀sún kan Emir tí wọn si dábàá pé kí Emir lo rọ́kun nílé. Ajọ tó ń gbógun ti ìwá àjẹbánu àti gbigbọ́ ẹ̀sun ara ìlú ní ìpínlẹ̀ Kano, ló fẹ̀sún kan Emir tí wọn si dábàá pé kí Emir lo rọ́kun nílé. Olóri oṣisẹ̀ láàfin Emir, Munir Sanusi tó jẹ́ri si gbigba ìwé ẹsùn náà, sọ pe, ìjọba ní ki Emir fesi láàrin wákàti mẹ́rìnlélogun lóri ẹ̀sùn náà. ''A ti gba ìwé ẹ̀sún náà, ìjọba si ti bèèrè fún èsì láàrin wákàtí mẹ́rinlélógún. Awọn ìjòye Emir ń fojú sùnukùn wó ẹ̀sùn náà"".",0,yoruba "Ẹni burúkú lè bẹ èpè l'ọ́wẹ̀ sínú ayé ẹnìkan tàbí sínú ìdílé kan gẹ́gẹ́ bí ègún. Ègún yìí ò sì ní jẹ́ kí ayé ó gún régé àti rọrùn f'ẹ́ni tí a gé ègún náà fún. Kò le è ṣe kí ó máà rí bẹ́ẹ̀, nítorí ègún kì í dára nínú iyán. #OgunIleAye #EgunIdile #Yoruba",0,yoruba "Fọnran kan to jade laipẹ yii nibi eto ti Foluke Daramola ṣe lo ṣafihan bi Pa Kasumu ti ri nitori aisan to ti n ba a finra lati ọjọ pipẹ. Amọ nigba to n ba awọn akọroyin sọrọ, Pa Kasumu ni oun ko nilo owo lati ọdọ awọn ololufẹ oun bi ko ṣe adura nitori aisan to n da agọ ara oun laamu ti kọja ọrọ oogun oyinbo lilo. Pa Kasumu ni oun wa ni ipagọ adura ile ijọsin kan nibi t'oun ti n gbadura fun iwosan agọ ara oun, o ni oun si maa wa nibẹ ti eto naa yoo fi pari. Ọgbẹni Odumosu to ti n ṣaisan lati bi ọdun mẹwaa sẹyin ṣalaye pe ijọ RCCG ni ṣọọṣi akọkọ ti oun yoo lọ fun ẹbẹ adura lati igba ti aisan naa bẹrẹ. O ni ṣọọṣi ti oun n lọ ni Sabo, Yaba naa n gbadura fun oun. Pa Kasuma tun fi kun ọrọ rẹ pe irọ ni iroyin tawọn eeyan kan n gbe kiri pe oun ti ni ipenija pẹlu oju oun. O ṣalaye pe awọn dokita sọ f'oun pe oun ni aarun rọpa rọsẹ eleyi to ṣakoba fun apa kan ara oun, ti o si tun ba oju oun. O ni iyawo oun atawọn ọmọ ni wọn n ṣe itọju oun lati igba ti aisan yii ti bẹrẹ. Ọkan lara awọn ọmọkunrin Pa Kasumu, Bode Odumosu naa sọ pe adura ni baba oun nilo bayii pẹlu ipo to wa. Lọdun 2017 ni iroyin kan jade pe aisan to n ṣe Pa Kasumu tun n le sii lẹyin to pada si Naijiria lati orilẹede India nibi to ti lọ gba itọju.",0,yoruba "Àkọ́kọ́, Ọba joko lòdì Ìbàdàn. Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.. A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..",0,yoruba "Ẹyin obinrin kan ti wọn ko pamọ lati ọgbọn ọdun sẹyin ti di ọmọ to jẹ ibeji. Iṣẹlẹ naa waye ni ipinlẹ Tennessee ni orilẹ-ede America. Igbagbọ wa pe ẹyin ọmọ naa ni eyi ti wọn ko pamọ fun igba pipẹ julọ, to si tun pada di ọmọ. Lati ọjọ kejilelogun, oṣu Kẹrin, Ọdun 1992, ni wọn ti ko wọn pamọ sinu eroja nitrogen. Iya awọn ọmọ tuntun naa, Rachael Ridgeway, to jẹ iya ọlọmọ mẹrin, bi awọn ibeji tuntun naa ni ọjọ kọkanlelọgbọn, oṣu Kẹwaa, dun 2022. Tọkọtaya kan ti wọn ko darukọ wọn, lo ni awọn ẹyin ọmọ naa ti wọn kojọ fun eto IVF, ki wọn le ri ọmọ bi. Ọjọ ori tọkọtaya ti wọn ko darukọ naa jẹ aadọta ati mẹrinlelọgbọn lasiko ọhun. Lati ọdun 1992 si ni wọn ti ko wọn pamọ si ibudo ilera kan ni Guusu America titi di ọdun 2007, nigba ti tọkọtaya naa yọnda wọn fun NEDC niluu Knoxville, Tennessee, ki tọkọtaya mii to nilo rẹ le lo o. Ni ajọ NEDC si ni awọn onimọ nipa ọ̀lẹ inu obinrin ti gbe wọn jade kuro ninu amu nkan tutu, ti wọn si gbe wọn sinu obinrin mii ni ibẹrẹ ọdun yii. Ninu atẹjade kan ti wọn fi sita, NEDC sọ pe ireti awọn ni pe iroyin yii yoo fun awọn eeyan mii ni igboya lati gba ẹyin ẹlomiran lo. Awọn ibeji yii ni ọmọ akọkọ ti tọkọtaya Ridgeway bi pẹlu ilana IVF, lẹyin ti wọn ti kọkọ bi ọmọ mẹrin. Ọkọ iyawo, Philip Ridgeway sọ pe ọmọ ọdun marun-un ni oun wa “nigba ti Ọlọrun da awọn naa, Lydia ati Timothy. “O si ti n pa wọn mọ lati igba naa titi di asiko yii.” Ọgbẹni Ridgeway sọ pe awọn ibeji naa ni ọmọ wọn to dagba ju, botilẹ jẹ pe awọn lo kere ju. Ọjọ ori awọn ọmọ mẹrin ti wọn bi tẹlẹ wa laarin ọdun kan si ọdun mẹjọ. Bi ida mẹrindinlogoji ninu ọgọrun, ni ẹyin ọmọ ti wọn ba gbà lo fi maa n di alaaye ọmọ ni America. Ẹyin ọmọ le wa fun ọpọlọlọ ọdun, ti wọn ba ti gbe e sinu eroja nitrogen. Koda wọn n fi ẹyin to ti lo ju ogun ọdun bi ọmọ. Iye owo IVF kan ni America wa laarin ẹgbẹrun mejila Dọla, ẹyin rira si wa laarin ẹgbẹrun lọna ogun si marundinlogoji Dọla. Ni Naijiria, owo IVF kan lati fi bimọ wa laarin miliọnu kan si miliọnu meji Naira. O si le ju bẹẹ lọ, nitori ileewosan kọọkan lo ni iye to n gba, eto ọtọọtọ si lo wa. Awọn mii le lo ẹyin ti wọn, awọn miran le lo ẹyin ẹlomii. Owo kekere kọ ni awọn to ma n fi ẹyin wọn silẹ ma n gba gẹgẹ bi owo iṣẹ.",0,yoruba RT @user: @user e e ni binu ni. Ejo won ko! Won n ran Oloun l'eti ni. Gbogbo laala wa a kuku ja s'ope ni oruko Jesu!,0,yoruba Irúfẹ́ Fáìlì: “%s”. Ó léwú láti ṣí “%s” bó ti jẹ́ wí pé ó ní agbára láti ba àwọn àkọsílẹ̀ rẹ jẹ́ tàbí kó já wọ ibi-ìkọ̀kọ̀ rẹ. Dípò èyí o lè ṣàgbéwọlé rẹ̀.,0,yoruba "owó àkokò, Ọmọ lo ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba Ìbàdandun ni ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn. (Item 53),0,yoruba "àìlẹ̀, Baàlè ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa òkè: ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba omi ìnira ọrọ̀ ajé orílẹ̀èdè nàìjíríà ń ṣe òjòjò owó oṣù òṣìṣẹ́ ò tó nǹkankan rà oúnjẹ hán gógó ta la á gbà wá,0,yoruba "Ọba se. Nitori eyi, ara eni lo ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba eku ojomu ayo ẹkú ọjọ́ gbọọrọ,0,yoruba 2023 General Elections: Ẹ gba ìpínlẹ̀ Eko kúrò lọ́wọ́ àwọn àjòjì - Atiku sí Bode George,0,yoruba abọ́jú irúngbọ. A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba "Ìgò ọtí méje àti sìgá ṣokùnfà ẹjọ́ ikú Ninu idajọ ti wọn gbe kalẹ ni ile ẹjọ giga to wa ni Ekiti, adajọ to pe orukọ ẹni ti wọn f'ẹsun kan naa gẹgẹ bii Babatunde jẹbi ẹsun ole jija ati nini ada ati okọ nigba ti wọn mu u wipe o jale. Adajọ ni iku ki wọn ye igi fun ni Babatunde yoo ku, nitori wipe o pẹlu awọn adigunjale mẹrin kan ti wọn tun gba foonu alagbeka oniyebiye lọwọ awọn eniyan. Ilé ẹjọ́ Èkìtì d'ájọ́ ikú f'ọ́kùnrin tó jí ọtí méje áti páálí sìgá Amọ, idajọ iku naa ti fa ọpọlọpọ ariyanjiyan laarin awọn ọmọ orilẹede Naijiria, ti awọn miran si n pe fun idajọ iku fun awọn oselu ti wọn n lu owo ilu ni ponpo ati awọn asebajẹ lawujọ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:",0,yoruba jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa òkè: ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba "àkerekere. Nitori eyi, ara eni lo ni ọ̀gbọ́n.",0,yoruba "Ìlú Ọ̀yọ́ jẹ́ ilẹ̀ agbègbè tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "dídì yìí ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Dokita mẹjọ lo ti ba arun lassa lọ ni Naijiria Alaga ẹgbẹ CAN ni ipinlẹ Ondo, Ẹniọwọ Ayo Ọladapo lo fi lede ninu lẹta ti wọn fi ransẹ si awọn adari ẹsin ni ipinlẹ naa lati se idanilẹkọọ fun awọn ara ile ijọsin wọn. Agbegbe Ọsẹ ati Ọwọ ni ipinlẹ Ondo ni aisan naa ti n ja rainrain nilẹ. Bakan naa, ni iroyin ni Adari Ile Iwosan Ijọba, FMC Ọwọ fi lede wi pe ko si aye fun awọn alaisan nitori ibi ti wọn ko awọn to ni aisan iba ọrẹrẹ si naa ti kun fọfọ. Ọna marun un lati dèna Lassa Fever Aisan iba ọrẹrẹ jẹ aisan ti ko ni ẹrọ, amọ ti o ni itọju ti ẹni to ba ni aisan naa ba tete lọ si ile iwosan lati fi ara rẹ han. Awọn gaari ti wọn n da silẹ lo n fa eku to ni aisan lassa lati tọ si ori garri yii, eleyi ti yoo fa aarun Lassa fun gbogbo ẹni to ba jẹ garri naa",0,yoruba ọmọ ri pe dara gan wey ti o tẹ.,0,yoruba A-fún-irúgbìn l'ẹni t'ó gbin nǹkan. @user,0,yoruba ègé olóótọ fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó wáyé.,0,yoruba ti iya nla ba gbeni san ile kekeke yoo ma wa gun ori eni,0,yoruba "Ní igba mi owó àkokò, Ọmọ lo mú.",0,yoruba "Arab àti Europe, ẹ ṣé o, ibi ẹ bá wa dé la wà yìí o :( #Africa",0,yoruba "Ọba Adewale lo fi ọrọ naa lede loju opo Instagram rẹ, nibi to ti sọ pe oun ni alaṣẹ lori gbogbo awọn oriṣa. Gẹgẹ bo ṣe sọ, o ni ""emi ni adari ati alaṣẹ lori gbogbo oriṣa ilẹ Yoruba ati kaakiri agbaye."" Bí o bá bá ààrùn ìpẹ́pẹ́ gbígbẹ lára arẹwà obìnrin rẹ̀, kí loó ṣe? Eégun àti orò, bí wọ́n ṣe jọ bí Ẹ̀ṣà Egúngún nílẹ̀ Yorùba rèé Kabiesi naa tẹsiwaju pe ""aafin Ọba jẹ aafin Ọlọrun nile aye, eyii to n tumọ si Ọlọrun Iwo."" ""Emi ni ojulowo Oluwo nitori Ọlọrun Eledumare gangan ni Ọlọrun Iwo, emi Ọba Abdulrasheed Adewale Akanbi Tẹlu 1 si ni aṣoju Ọlọrun ninu ẹran ara gẹgẹ bii Oluwo."" Oluwo ṣalaye pe aafin oun ní ilu Iwo ni aafin Ọlọrun nile aye ko sì sí Ọba miran mọ nitori Ọba kii pe meji laafin. O ni orogun ni awọn oriṣa jẹ si Ọlọrun nitori ko ṣeṣe ki eeyan ki Ọlọrun lara oun ko tun lọ foribalẹ fun awọn oriṣa miran. Ọpọ awọn ololufẹ rẹ lori ikan Instagram lo ti n fi erongba wọn lede lori ọrọ naa. Àṣírí tú! Ikọ̀ ìwádìí BBC ṣí àwọn tó ń jí ìkókó gbé sí gbangba",0,yoruba Ènìyan ti nilo iyalẹnu fun ìwà tabi ibini.,0,yoruba "Bakan naa ni oju opo yii maa ṣagbejade mẹwaa loke tente lara awọn orin, ere idaraya, awọn oṣere ati fiimu wọn gangan to fi mọ ifọrọwanilẹnuwo to fakọyọ. Labẹ isọrii awọn mẹwa to pọju tawọn eeyan n bi google leere nipa wọn ju, awọn olorin ọmọ Naijiria bii Rema, Naira Marley, Omah Lay ati ajaweolubori eto ile Ẹlẹgbọn agba (Big Brother Naija Lock down Season 5), Laycon naa wa nibẹ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹni akọkọ lorii ila awọn ti wọn n wa ju lori google ni aarẹ tuntun ti wọn dibo yan l'Amẹrika, Joe Biden, lẹyin naa ni Rema ati Naira Marley tẹle e. Gbajugbaja oṣere fiimu Hausa, Rahama Sadau ni o wa nipo kẹrin. Ninu oṣu kọkanla ni Rahama gbayi lori google tori awọn fọto rẹ to fọnka sorii ayelujara. Awọn fọto yii da wahala silẹ gẹgẹ bi awọn eeyan ṣe ni o lodi si ilana ""Prophet Mohammed"" ti awọn mii si ni awọn o rohun to buru nibẹ. Maryam Sanda, obinrin ti wọn fẹsun kan pe o pa ọkọ rẹ lọdun 2017, ti ile ẹjọ si dajọ iku nipa yiyẹgi fun un nibẹrẹ ọdun yii, naa wa lara awọn ohun ti wọn n wa loju opo agbaye yii. Gẹgẹ bi google ṣe sọ ọ, Maryam Sanda ni ẹni ikẹẹsan lori ayelujara ni Naijiria lọdun yii, tawọn eeyan fẹ mọ nipa rẹ Wo ẹkunrẹrẹ oniruuru isọri ohun tawọn eeyan n wa ati awọn to gba ipo kinni gẹgẹ bi google ṣe gbe e jade: Awọn eeyan ti wọn n wa nipa wọn ju (Nigeria): Nkan gboogi mẹwa tawọn eeyan n wa lọdun yii ni Naijiria lorii Google: Iru ounjẹ, nkan mimu ati ipanu tawọn eeyan n beere ju nipa rẹ ni Naijiria lorii Google: Awọn orin mẹwaa tawọn eeyan tẹ soju opo Google lọdun 2020: Awọn ibeere bii ""bawo ni wọn ṣe n ṣe burẹdi jẹ ọkan lara ibeere to wa loke ohun tawọn eeyan n bi Google ju lọdun 2020. Awọn ibeere ọhun ni:",0,yoruba "Ní igba mi owó àkokò, Olùwo ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé. ti Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba ní ègé olóótọ fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìṣẹ̀: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn.,0,yoruba "Gẹ́gẹ́ bíi ìtàn àtẹnudẹ́nu Ọ̀wọ̀, bí ọba bá ti jẹ ní Ọ̀wọ̀, ọba náà yóò mú orúkọ ńlá kan láti Benin, láti fi kún orúkọ rẹ̀. Ìdí èyí ni láti tún bọ̀ fi gba iyì láàárín lójú àwọn ọmọ ìlú Ọ̀wọ̀. Àwòrán 1&2 - Ọlọ́wọ̀ Àwòrán 3&4 - Ọba Benin https://t.co/4BmyGWrFgP",0,yoruba "Lọjọ Abamẹta ni ẹgbẹ agbabọọlu Manchester City ko ba gba ife ẹyẹ idije Premier League ti saa bọọlu yii to ba jẹ pe wọn lu Chelsea ni papa iṣere Etihad. Ṣugbọn Man City ni lati duro di ọjọ mii ki wọn to le gba ami ẹyẹ naa nitori Chelsea ti ẹyin gbe ru wọn. Raheem Sterling lo kọkọ gba goolu sawọn Chelsea ni abala akọkọ ifẹsẹwọnsẹ naa. Lẹyin naa ni Manchester City tun ri pẹnariti eyi ti wọn gbe fun Sergio Aguero wi pe ko gba. Ṣugbọn akọ ni Aguero fi gba pẹnariti ọhun eyi ti golu Chelsea mu lai laagun rara. Abala keji ere bọọlu naa ni Chelsea ni sọji mọ Man City lọwọ. Hakim Ziyech lo kọkọ da goolu ti Sterling gba wọle pada, ki Marcos Alonso to fi ọba le. Ni bayii, Man City ṣi le gba ife ẹyẹ EPL lọjọ Aiku ti Aston Villa ba lu Manchester United ni Villa Park. Lọjọ kọkandinlọgbọn oṣu karun un lawọn mejeeji yoo jọ pade ninu ifẹsẹwọnsẹ aṣekagba idije Champions League.",0,yoruba "Ẹgbẹ CAN kọminu lori kikuna ileesẹ alaabo lati pẹka awọn apanijaye gbogbo to n da omi alaafia orilẹede Naijiria ru Ninu atẹjade kan to fi sita eleyi to tẹ BBC Yoruba lọwọ, ẹgbẹ CAN ni pẹlu bi nkan se ri bayii lori ọrọ abo lorilẹede Naijiria ti fihan wipe awọn ileesẹ alaabo rẹ nilo awọn ẹjẹ tutu to ni iran tuntun ti o lee da alaafia pada si agbami ọrọ abo orilẹede Naijiria ti ko duro deede ni lọwọlọwọ. Ẹgbẹ naa koro oju si kikuna ti awọn ileesẹ alaabo n kuna lati pẹka awọn apanijaye gbogbo to n da omi alaafia orilẹede Naijiria ru ki o to di wipe wọn se ọṣẹ wọn. CAN ni gbigba awọn osisẹ tuntun fun ipo adari lẹka abo yoo mu iran tuntun ba ọrọ abo ""A ko faramọ aato igbimọ eleeto abo to gaju lorilẹede Naijiria lọwọlọwọ yiieleyi to fi si ọdọ awọn ẹlẹsin kan ati ẹya kan lorilẹede yii. Orilẹede to kun fun ẹya ati ẹsin pupọ ni orilẹede wa, a si n ke si Aarẹ Muhammadu Buhari wipe ko gbọran si ohun ti ofin to de pinpin ipo lorilẹede Naijria, Federal character commission act sọ pẹlu gbogbo awọn iyansipo ati eto rẹ gbogbo."" Bakannaa ni ẹgbẹ CAN tun bu ẹnu atẹ lu bi awọn ọmọde ti ko tii to ibo o di se n forukọsilẹ lati dibo pẹlu ipe si ajọ eleto idibo orilẹede Naijiria, INEC lati tete wa wọrọkọ fi sada lori ọrọ naa eleyi ti wọn ni o n waye kaakiri bayii ti eto iforukọsilẹ awọn oludibo tuntun n lọ lọwọ. Minisita fun eto iroyin lorilẹede Naijiria, Alhaji Lai Mohammed, ti ni ko sọrọ lori ipe ti ẹgbẹ ọmọlẹyin Kristi lorilẹede Naijiria, CAN pe wipe ki Aarẹ Muhammadu Buhari o se atunto awọn adari ileesẹ ọmọogun rẹ pẹlu awọn ẹjẹ tuntun ti yoo le mu ayipada ati igbona ọkan ba eto abo ati igbesẹ gbigbogun ti awọn adukukulaja. Alhaji Lai Mohammed ni 'mi o lero wipe mo fẹ sọ ohunkohun lori ọrọ ti CAN sọ.' Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹ si:",0,yoruba Ìyalẹnu ti wa ni àlùfáà lo je gbogbo ise ibile tèmi.,0,yoruba "Kò sóhun tó ń jẹ́ pẹ́lú dìbò ko sebẹ̀ láàrín àwọn aṣojú-dìbò wa -PDP Eto idibo abẹnu ẹgbẹ oṣelu PDP lati yan oludije fun eto idibo sipo aarẹ orilẹede Naijiria n waye lọwọ ni gbagede isire indoor sports hall papa isire MKO Abiola nilu Abuja. Awọn alaṣẹ ẹgbẹ oṣelu PDP to ba BBC sọrọ ni eto gbogbo ti to fun ayeyọri ẹgbẹ naa ati pe ko ni si wahala lẹyin eto naa. Bakan naa ni wọn tun ṣalaye pe awọn alaṣẹ ẹgbẹ oṣelu naa ko mọ si oro owo re e ibo ree ti iroyin rẹ n kaakiri pe o n waye laarin awọn oludije ati aṣoju lawọn ẹgbẹ oselu lọwọ yii. Okan lara àwọn ọmọ igbimọ majẹkobajẹ ẹgbẹ naa lati ipinlẹ Ọyọ ṣalaye pe ohun to jẹ awọn Oludije ẹgbẹ oṣelu naa ni lati yan oludije ti yoo ṣoju awọn ọmọ Naijiria ti yoo si mu igba pada si rere fun orilẹede Naijira. Bakan naa ni aarẹ ile aṣofin agba Naijiria nigba kan ri Sẹnetọ David Mark pẹlu fi gbogbo awọn ọmọ ẹgbẹ PDP lọkan balẹ pe didun lọsan yoo so fun wọn ati pe o da oun loju pe ko ni si wahala, ikunsinu tabi edeaiyed kankan lẹyin abajade idibo naa. Bakan naa ni gomina ipinlẹ Bayelsa, Duoye Diri pẹlu kin ọrọ naa lẹyin ti wọn si ni eto gbogbo ti to bayii ko si si oun to n jẹ ayipada ọjọ eto naa nitori awọn ti ṣetan bayii.",0,yoruba @user Ọmọ kíni? Ọsún tàbí Ọ̀sun (Ọ̀ṣun)?,0,yoruba Lekan Salami Stadium: Ìjọba Oyo fèsì padà lórí aríwísí pé omi wọ pápá tí Makinde fi N5.3bn tún ṣe,0,yoruba ọsẹ àsa. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba ọ̀gbọ́n. Ọmọ lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó ṣe pàtàkì.,0,yoruba ìyà ń bẹ fún ọmọ tí ò gbọ́n ẹkún ń bẹ fún ọmọ tó ń sá kiri,0,yoruba Ìlú yorubá lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa òkè: ti o ní wúlò.,0,yoruba Ìlú tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó wáyé..,0,yoruba won je ayo na ti ni aja kini anfani ninu ki a binu si eni ti olorun gbega iparun ni eda to ba se iru eyi wa,0,yoruba "fè se, Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí.",0,yoruba "Ọdún 38 ni ìyá mí fi ṣiṣẹ́ ní UCH, màá kọ́ ibùdó ìtọ́jú àrùn jẹjẹrẹ ní ìrántí rẹ - Ọọ̀ni alarun jẹjẹrẹ sile iwosan nla UCH nilu Ibadan.Ọba Ogunwusi seleri bẹẹ lasiko to n gbalejo awọn ọmọ igbimọ alasẹ ile iwosan naa, ti onisegun agba, Ọjọgbọn Jesse Abiodun Otegbayo ko sodi wa si aafin rẹ.Ọọni salaye pe ọdun mejidinlogoji ni iya oun, Wuraola Ogunwusi fi ṣiṣẹ nile iwosan UCH, ti iṣẹ takuntakun to ṣe nibẹ ko si parẹ titi di oni. ""Laipẹ laijinna ni maa kọ ibudo itọju awọn alarun jẹjẹrẹ, ti wọn yoo ti maa gba itọju kímò, maa si pe orukọ ibudo naa ni Wuraola Chemotherapy Cancer Centre, lati ma ṣe jẹ ki orukọ iya mi parẹ."" Ọdún 38 ni ìyá mí fi ṣiṣẹ́ ní UCH, màá kọ́ ibùdó ìtọ́jú àrùn jẹjẹrẹ ní ìrántí rẹ - Ọọ̀ni Arole Oodua tun woye pe gẹgẹ bii ojulowo ọmọ Yoruba ọpọ egboogi ibilẹ lo wa fun iwosan arun Coronavirus atawọn aisan asekupani miran eyi to yẹ ka tẹwọ gba fun itọju awọn alaisan naa pẹlu oogun oyinbo."" Awọn Ọjọgbọn lorisirisi ti pejọ si fasiti Afe Babalola nilu Ado Ekiti lati ṣe ẹkunrẹrẹ iwadii lori awọn ewe ati egbo to le wo awọn aisan asekupani bíi Coronavirus, awọka, aromọleegun, arun jẹjẹrẹ ati bẹẹ bẹẹ lọ, ti wọn yoo si jẹ kijọba apapọ ati ajọ Nafdac mọ nipa bi awọn oogun ibilẹ naa yoo ti wulo si ati ipese wọn. ""O wa dupẹ pupọ lọwọ igbimọ alasẹ ile iwosan UCH fun abẹwo wọn, eyi to jọ oun loju lasiko Coronavirus yii. Ọọni, Aláàfin, Ojisẹ Ọlọ́run àti oniṣẹ ìwádìí fi Ògún gbari pé òògùn ìbílẹ̀ le wo Covid-19 Madagascar herbal cure: Ọọni, Aláàfin, Ojisẹ Ọlọ́run àti oniṣẹ ìwádìí fi Ògún gbari pé òògùn ìbílẹ̀ le wo Covid-19 Laipẹ yìí ni Minisita fún ètò ìlera ní Nàìjíríà, Dókítà Osagie Ehanire kéde pé, ìjọba kò tako àmúlò òògùn ìbílẹ̀ fún ìwòsàn àrùn Coronavirus.Arun aṣekú pani ọ̀hún, sì ni abiku rẹ ti sọ àwọn oníṣègùn jákèjádò àgbáyé di èké, tí wọn si ni àwọn ko ri ìwòsàn fún ajakalẹ-arun Covid-19 náà.Níwọ̀n ìgbà tó jẹ́ pé, àwọn ibi taa fi ojú si lagbaye lórí wíwà ìwòsàn fún àrùn yìí, ọna kò gba ibẹ lọ, lo mú ki awọn ọmọ ilẹ̀ Áfíríkà kan dìde láti wá ìwòsàn pẹ̀lú oògùn ìbílẹ̀. Orílẹ̀ èdè Áfíríkà bíi Madagascar Cameroon àti Nàìjíríà sì ti ń fi ogun rẹ gbari pé, àwọn òògùn ìbílẹ̀ kan leè wo àrùn Coronavirus, tí Madagascar sì ti ń lo òògùn ìbílẹ̀ tiẹ̀ fún ìwòsàn àrùn náà. Ní orílẹ̀ èdè Nàìjíríà, àwọn ọba alaye bíi Ọọni tilu Ilé-Ifẹ̀, Ọba Adeyeye Enitan Ogunwusi, Ọjaja Kejì àti Aláàfin tilu Ọ̀yọ́, Ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi Kẹta, to fi mọ ojisẹ Ọlọ́run bíi Fada Anselm Adodo àti oniṣẹ ìwádìí Isegun bíi Ọjọgbọn Maurice Iwu, lo fi ọwọ gba àyà pé, òògùn ìbílẹ̀ yóò ṣe ìwòsàn àrùn Coronavirus. Ọọni ti Ilé-Ifẹ̀, ọba Adeyeye Ogunwusi Wo bí o ṣe leè ṣe ìjìnàsíraẹni ní ibiṣẹ́ lásìkò Coronavirus yìí Arole Oodua, ọba Ogunwusi kéde síta Laipẹ yìí pé òun ti ṣe àwárí ìwòsàn fún àrùn Coronavirus. Bẹẹ si ni ninu fídíò kan tó gbé sójú òpó Facebook rẹ, ní ọba Ogunwusi tí ń ṣe àfihàn àwọn egboogi ìbílẹ̀ kan tó lè wo àrùn Coronavirus san, àti bí àwọn èèyàn ṣe leè lo. Fídíò náà sì ni àwọn ènìyàn tó lè ní ẹgbẹ̀rún lọ́nà àádọ́ta wò, tí àwọn bíi ẹgbẹjọ si ṣe alábàápín rẹ. Ọọni ni ""Mo ti dán àwọn òògùn ìbílẹ̀ náà wò, mo ti lo fún alárùn Coronavirus kan, tí wọn sì ni ajẹbiidan ni òògùn ìbílẹ̀ náà."" Ọba alaye náà wá ń rọ àwọn oniṣẹ ìwádìí ni Nàìjíríà àti ní àgbáyé, láti fi àmúlò oogun ìbílẹ̀ yìí mọ Isegun òyìnbó. Aláàfin ti Ọ̀yọ́, Ọba Lamidi Adeyemi Ọba Adeyemi, lásìkò to ń ṣe ifilọlẹ ìwé kan tí ẹnikan kọ nípa Ayinla Ọmọwúrà, kéde pé òògùn ìbílẹ̀ wa dáadáa tó lè wo ajakalẹ-arun Coronavirus, èyí tó ti sẹ orunkun àwùjọ àgbáyé. Alaafin ni àwọn òògùn ìbílẹ̀ wà dáadáa láyé àtijọ́, tó ń wo àwọn àrùn bíi ìgbóná tàbí Sanponna àti atọgbẹ, tí àwọn oníṣègùn ìbílẹ̀ náà sì ní agbára láti fi ohùn lásán ransẹ sì ẹni tó wà nílẹ òkèèrè, tí ohun tí wọn ba sọ, yóò sì máa ṣẹ lójú ẹsẹ. Niyi Akinmolayan tó ṣe fíìmu àwòrán-dèèyàn Cartoon nípa COVID-19 tó la ayé já ní N ""Kò sí àìsàn tàbí àrùn ni orílẹ̀ ayé tí àwọn baba wa kò leè wòsàn, mo sì mọ pe àwọn agbára náà sì wà síbẹ̀ títí di òní."" Fadá Anselm Adodo Ojisẹ Ọlọ́run kan nínú ìjọ Kátólíìkì, tíì tún ṣe olùdarí fún ilé ìwòsàn ìbílẹ̀ nipinlẹ Edo, Fadá Anselm Adodo tí fi ìkéde kan síta lójú òpó Facebook rẹ, ní Ọjọ́bọ, ọjọ́ Kokandinlogbon oṣù kẹrin ọdún 2020 pé, ibùdó ayẹwo òun ti gbé òògùn ìbílẹ̀ kan jáde, tó le wo àrùn Covid-19. Fada Anselm ni òògùn ìbílẹ̀ náà lo dára julọ fún ìwòsàn àrùn Coronavirus, tá sì tún leè pèsè òògùn naa ni irọrun ni abẹle, ká sì pín kàkàkí. O ni èròjà CVD PLUS tó wà nínú rẹ lo ń gbógun ti àwọn kòkòrò àrùn tí a kò leè fojú rí, tó sì tún ń mú agbega bá àwọn ọlọ́pàá tó ń dáàbò bo ara, èyí tó lè ṣe iranwọ láti bá àwọn àrùn to jọ mọ Coronavirus ja. ""Mo ti gbé oogun náà fún àjọ Nafdac, tí wọn si ni àwọn yóò ṣe ìwádìí oogun náà bo ṣe pegede si."" Ọjọgbọn Maurice Iwu Ọjọgbọn kan nilẹ Nàìjíríà, Maurice Iwu tí kéde ni osu kejì ọdún pé òun ti ṣe àwárí òògùn tó lè wo àrùn Coronavirus. Iwu ni òun ti sepade pẹ̀lú Minisita fún imọ ṣayẹnsi àti iṣẹ ẹ̀rọ pẹ̀lú Minisita feto ìlera láti sọ fún wọn pé, òun ti rí àwọn egbògi kan tó leè ṣe ìwòsàn fún arun Coronavirus tàbí arun-karun tó bá ń ṣe idiwọ fún mimi jalẹ. ""Méjì nínú èròjà mẹta tí mo rí náà, wá lara awon èròjà tí àjọ Nafdac tí fi ọwọ si ṣáájú, pé ó dára fún lilo àwọn èèyàn."" Maurice Iwu ni àwọn ewéko náà tí òun ṣe àwárí wọn náà, ní àwọn ọmọ ilẹ̀ China tí lo fún ìwòsàn àrùn Coronavirus yìí kan náà. Coronavirus in Lagos: Ayẹwò kò dáwọ́ dúro botílẹ̀ jẹ́ pé èròjà ayẹwò (Reagents) kò si mọ́- Kọmísọ́nà ìròyìn Ayẹwò kò dáwọ́ dúro botílẹ̀ jẹ́ pé èròjà ayẹwò (Reagents) kò si mọ́ Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ni ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta ènìyàn ni àwọn n ṣe àyẹ̀wò coronavirus fún lójoojúmọ lójúnà àti mú àdínkù bá ìtànkálẹ̀ ààrùn coronavirus. Kọmísọ́nà fún ètò ìròyìn ni ìpínlẹ̀ Eko Gbenga Omotsho ló sọ eyí lásìkò to n ba BBC News Yoruba sọ̀rọ̀. Sáájú ní ọjọ́ ajé ni gómìnà ìpínlẹ̀ Eko Babajide Sawnwo-Olu ti kéde pé èròjà èlò ti wọ́n fi n ṣe àyẹwò ààrùn Coronavirus ko si ni ìkáwọ́ àwọn mọ́ àti pé, o tó ènìyàn ẹgbẹ̀run mẹ́ta tó wà nilẹ̀ bayìí ti kò si bi wọ́n a ṣe ṣe àyẹ̀wò fún wọ́n Wo bí o ṣe leè ṣe ìjìnàsíraẹni ní ibiṣẹ́ lásìkò Coronavirus yìí Ìdí nìyí ti BBC ṣe wádìí lọ́wọ́ kọmísọna, lórí ìgbésẹ̀ ti ìjọba n gbé ti ọ̀rọ̀ ààrùn Coronavirus kò ṣe ni bẹ́yìn yọ ni ìpínlẹ̀ Eko. Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ Gbenga Omotosho ní, báyìí ìpínlẹ̀ Eko ti ranṣẹ́ si gbogbo àwọn to n tàá èròjà àyẹ̀wò náà tàbi to lé rìí, láti kan si ijọba, o ní gbogbo àwọn orilẹ̀-èdè ti o ṣeese ki wọ́n ni náà ni ìjọba ti kan si. O rọ gbogbo àwọn ti wọ́n n ta àwọn ǹkan wọ́n yìí láti maa rò pé àsìkò láti pawó rẹpẹtẹ rèé. ""Ọdún yìí kii ṣe ọdun ti ènìyàn n wá èrèọjà rẹpẹtẹ bíko ṣe, asíkò láti wà láàlafíà."" kọmísọ́nà lo sọ bẹ́ẹ̀ O ní bi kò ṣe si èròjà àyẹwò yìí, eyi ko dá àyẹwò dúró, sùgbọ́n ka ni a wà lọ́pọ̀ ni ayẹwò ko ba jù bẹ́ẹ̀ lọ. Kọmísọ́nà túnn rọ gbogbo ará ilú láti móju to àwọn àfin ti ìjọba là silẹ̀, kí àwọn ènìyàn maa lo ìbomu wọ́n , ki wọ́n máa fọ́wọ́ déédé àti pé o ṣe pàtàkì ki wọ́n sa fun ìpéjọpọ̀ àwọn ènìuyàn tó pọ̀. Agbófinró, tó bá wa ọkada àbí kẹkẹ maruwa l'Eko, o rugi oyin - Sanwo-Olu Lagos Okada ban: Ìjọba Eko ní òun yóò pèsè ọkọ ti yoo rọpo ọkada ati kẹkẹ láìpẹ́ Ijọba ipinlẹ Eko ti sọ pe agbofinro kankan ti ọwọ ba tẹ pe o n ṣe ọkada tabi wa kẹkẹ maruwa yoo foju wina ofin. Ikilọ yii lo waye nibi ipade to waye nile ijọba ipinlẹ naa ni Marina, leyi ti Gomina Babajide Sanwo-Olu sẹ alaga rẹ. Ijọba naa ni o lodi si ofin fun ẹnikẹni to jẹ agbofinro, yala ọlọpaa ni tabi ọmọ ologun lati maa ṣe iṣẹ okada tabi wa kẹkẹ ẹlẹsẹ mẹta lawọn agbegbe ti ijọba ti fofin de. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kọmiṣọna fun ọrọ to n lọ, Gbenga Omotoso sọ fun awọnn oniroyin lẹyin ipade naa pe, ijọba Eko ko ni fọwọ yẹpẹrẹ mu ọrọ naa lọna ati le ọkada ati kẹkẹ maruwa jinna rere si awọn agbegbe ti wọn ti fofin de wọn. O ni, o jẹ ohun to ba ijọba ninu jẹ pe awọn agbofinro lo n ru ofin ti ijọba gbe kalẹ lori ọkada ati kẹkẹ maruwa nipinlẹ ọhun. Omotoso ṣalaye pe, awọn eleto abo lee wa alupupu wọn lawọn ibi ti wọn ti fofin de ti wọn ba wa ninu aṣọ iṣẹ nikan, kii ṣe ki wọn maa lo aṣọ ara lati gbe ero nitori wọn jẹ ọlọpaa tabi ọmọ ologun. O ni ""A ti ṣagbeyẹwo ofin to de kẹkẹ maruwa ati ọkada, agbofinro to ba wọ aṣọ iṣẹ to si n wa alupupu rẹ nikan la gba laaye lati lo lawọn ibi ti a fofin de."" Omotoso tẹ siwaju pe ""Agbofinro ti ọwọ ba tẹ pe o n ṣe iṣẹ ọkada tabi wa kẹkẹ ẹlẹsẹ mẹta lawọn ibi ti a ti fofin de, yoo foju wina ofin."" Kọmiṣọna naa ni ijọba ipinlẹ Eko ko ni yi ipinnu rẹ pada lori bo ṣe fofin de ọkada ati kẹkẹ maruwa ni ipinlẹ ọhun, ṣugbọn o sọ pe ""Titi Oṣu Kẹrin ọdun, ijọba yoo pese awọn ọkọ ti yoo rọpo ọkada ati kẹkẹ ẹlẹsẹ mẹta."" Nipa afara Eko to di titi pa, o ni igbesẹ naa ṣe pataki nitori ọna ati daabo bo ẹmi awọn to n gba ori afara naa, ati pe, ijọba n ṣeṣẹ takuntakun lati mu aye dẹrun fun awọn eeyan ipinlẹ naa. Ọjọ kinni, Oṣu Keji ọdun 2020 ni ijọba ipinlẹ Eko labẹ iṣakoso Gomina Babajide Sanwo-Olu gbẹsẹle ọkada ati kẹkẹ maruwa lawọn ijọba ibilẹ kan, leyi ti inu ọpọ awọn olugbe ipinlẹ naa ko dun si. Stolen phone: Fóònù mi ni mo lọ́ tún ṣe lọlọ́pàá bá he mí pé mo jí fóònù",0,yoruba "10. Ǹjẹ́ o lè sọ èrèdíi tí a fi pe foam ni fóòmù, bank ní báǹkì àti ọ̀rọ̀ bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ̀? #ibeere #Yoruba",0,yoruba lọ́rọ̀.. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọba lo lọ.,0,yoruba "ìgbà àkerekere. Nitori eyi, ara eni lo ni àṣà yorubá eyti o gbe lori àìmọ́ kọ.",0,yoruba "RT @user: Ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà láti ọdún 1999 sí ọdún 2003, Dókítà Olufẹmi Okunrounmu, bàbá àti ìyá wọn bí wọn ní ọjọ kọkọnla, oṣ…",0,yoruba "ní àìlẹ̀, Ọba ri Nitori eyi, ara eni lo ni àṣà yorubá eyti o gbe lori iwa rere.",0,yoruba kan mòní nípa ìgbà àkerekere lo je gbogbo ise ibile tèmi.,0,yoruba "Ifilọlẹ BBC Yoruba yoo waye lọjọ kọkandinlogun oṣu keji ọdun ""A ṣe awa naa lee ni BBC tiwa. Eyi ga o. BBC Hausa, Swahili ati bẹẹ lọ la maa n gbọ po wa fun ọpọlọpọ ọdun. ""Asiko si ti to bayi tileesẹ agbohunsafẹfẹ BBC yoo da oju opo Yoruba silẹ. Fun iru ede to rẹwa, to si yaayi lati sọ, bii ede wa yi, ohun to rọrun lati foju sọna fun ni eyi."" Eyi ni awọn ọrọ Senator Rashidi Ladọja, tii se gomina tẹlẹ nipinlẹ Oyo, eyi to jẹ ipinlẹ kan lẹkun iwọ oorun guusu Nigeria, tọpọ eeyan ti n sọ ede Yoruba. Ero Sẹnatọ Ladọja yi lo se afihan bi ireti awọn ọmọ ilẹ Kaarọ oo jiire se jinlẹ si nipa agbekalẹ oju opo BBC Yoruba, se tiwa n tiwa, akisa ni ti aatan. Nkan ti awọn eeyan nsọ lori BBC Yoruba Owe yoruba kan lo ni: ""Gele ko dun, bii ka mọọ we, ka mọọ we, ko dabi pe ko yẹni, ko tun wa yẹ ni ,ko dabi pe ko jẹ tẹni."" Itumọ eyi ni pe, agbekalẹ oju opo BBC Yoruba ko rẹwa to bii ki awọn eeyan tẹwọ gbaa. Eyi si jẹ anfaani nla lati kan si ọpọ eeyan ni ede abinibi wọn. Igbesẹ yi yoo tun fun awọn Yoruba lanfaani lati lẹnu ninu ileesẹ agbohunsafẹfẹ BBC. Oju opo ikanni BBC Yoruba yi yoo tun se agbekalẹ itumọ to yanranti fun igbe aye, asa, ise,ajọdun ibilẹ, owe ati bẹẹ bẹẹ lọ, laarin awọn iran Yoruba. Igbe aye awọn eeyan yoo si tubọ pegede sii , tileesẹ iroyin kan ba n pese iroyin fun wọn ni ede abinibi wọn. Orisun isẹ iroyin tuntun Ẹni-ọwọ Henry Townsend se agbekalẹ ileesẹ itẹwe akọkọ lorilẹede Nigeria lọdun 1854, eyi to papa lo, lẹyin ọdun marun to se ifilọlẹ rẹ, lati fi tẹ iwe iroyin akọkọ lorilẹede Nigeria sita ni ede abinibi Yoruba,eyi to pe ni ""Iwe Irohin Fun Awọn Ara Ẹgba Ati Yoruba"". Ọjọ kẹtalelogun, osu kọkanla ọdun 1859 si ni iwe iroyin akọkọ naa jade . Lẹyin ifilọlẹ naa ni wọn wa pe orukọ rẹ ni ""Iwe Irohin"". BBC Yoruba bẹrẹ iṣẹ ni pẹrẹwu Amọ, wọn ni Ọba mẹwa, igba mẹwa, bi aye ba nyi, o yẹ ka maa ba aye yi ni. Pepele iroyin lorilẹede Nigeria ti yipada pupọ bayi kuro ni ti aye atijọ, ọpọn iroyin ti sun siwaju, amọ sibẹsibẹ awọn eeyan Yoruba si fẹ maa mọ ohun to n lọ. Wọn n garun, ti wọn si n kopa ribiribi, ti wọn ko si kawọ gbera rara lati mọ ohun to n sẹlẹ lawujọ wọn, paapa ni ede abinibi wọn.. Niwọn igba to si jẹ pe isu atẹnumọran kan kii jona, eyi lo sokunfa bibi oju opo BBC Yoruba bii ọmọ tuntun jojolo. Se ohun to ba si ti ya kan, kii tun pẹ mọ, Aaya ti wa bẹ silẹ, o ti bẹ sare bayi, ijiroro ati iroyin nipa asa ati oselu ti wa gba ọna ọtun yọ bayi, ọpọn ti sun. Erongba fifun awọn eeyan ni iroyin ti wọn lee lo (ni ede abinibi wọn), lo n mu ki iroyin naa sun mọ wọn pẹkipẹki, to si tun n jẹ ki wọn jẹ olotitọ si oju opo to n fun wọn ni iroyin naa kọja ero ẹnikẹni. Isẹ Iroyin to ni Igbẹkẹle kikun Niwọn igba to jẹ pe akọmọna ileesẹ agbohunsafẹfẹ BBC ni otitọ, orukọ rere ati aisegbe sibikan, eyiti oju opo BBC Yoruba yoo jogun, se ọmọ kii ba ipele iya rẹ, ko si asọ da, ko si aniani pe eyi yoo fun awọn Yoruba to jẹ ololufẹ oju opo yii lanfaani lati tẹwọgba ilana isẹ iroyin to se ara ọtọ, to si da lori igbẹkẹle awọn araalu. Iko BBC Yoruba tuntun Bi o tilẹ jẹ pe o se ni laanu pe, akoko amulo oju opo ayelujara taa wa yi, n faaye silẹ fun itankalẹ iroyin eke ti ko fẹsẹ mulẹ, eyi to ti mu ki alafo nla wa laarin awọn iroyin to jẹ otitọ ati awọn araalu. Sugbọn, bi ẹkun pẹ lọ titi, ayọ n bọ lowurọ, pẹlu ifilọlẹ oju opo BBC Yoruba bayi, alafo naa ko ni pẹ dohun igbagbe. Bẹẹni awọn osisẹ ti setan lati maa da bi ẹdun, rọ bii owe lori oju opo BBC Yoruba bayi. Igbesẹ wa akọkọ Wọn ni itọwo laa mọ adun ọbẹ, eto ifinimọle awa osisẹ gan ni itọwo akọkọ, eyi to fun wa loye lati mọ ohun ti ileesẹ agbohunsafẹfẹ BBC da le lori. Sise alabapade awọn oludanilẹkọ wa, fifi eti silẹ si idanilẹkọ wọn, ati fifi ara kinra pẹlu awọn akọroyin tuntun miran ti yoo maa sisẹ papọ loju opo BBC Yoruba lẹyinọrẹyin, wu ni lori pupọ. Lati ọjọ kinni ti gbogbo wa si ti foju kan ara wa, lati di ""bi igbin ba fa, ikarahun a tẹle"", taa si fọwọ sowọpọ lati sisẹ papọ. Eyi to wa jẹ oyin ninu rẹ ni igba ti wọn pin kaadi idamọ fun wa gẹgẹ bii osisẹ ileesẹ BBC, eyi lo wa fi idi rẹ mulẹ nitootọ pe osisẹ BBC ni wa. Se wọn ni, iborun ti ko ba sunwọn, abẹ abiya lo n gbe, eyi to ba sunwọn, ejika ni yoo wa, bi kaadi idamọ wa yi se sunwọn, lo mu kawa naa maa gbee kọrun kiri bii ami ẹyẹ goolu . Ero wa gẹgẹbi osisẹ ileesẹ BBC Lasiko taa bẹrẹ si ni ko eroja jọ fun ifilọlẹ oju opo BBC, ohun kan to se pataki taa se akiyesi rẹ ni pe ara awọn araalu n ya gaga lati ba wa sọrọ nitoripe ileesẹ agbohunsafẹfẹ BBC la ti wa. Kini Yoruba n pe ni ""pen""? Wọn nigbagbọ pe a yoo sọ ohun ti wọn wi lai bomi laa. Koda, nigba ti iroyin awọn ọmọ Nigeria to ha sorilẹede Libya gbode, ileesẹ ti wọn gbe isẹ kiko awọn ọmọ Nigeria wale lati orilẹede Libya le lọwọ, mọọmọ kan si wa lati fun wa ni ẹkunrẹrẹ iroyin nipa iriri awọn ọmọ Nigeria, bẹrẹ lati akoko ti wọn n gbera lati orilẹede yi lọ si Libya, titi de igba ti wọn pada de. Loni ni ọjọ ọla bẹrẹ. Niwọn igba to jẹ pe ika to ba tọ simu, laa fi nre imu, ileesẹ BBC gba awọn osisẹ ti musemuse wọn da musemuse sẹnu isẹ. Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Awọn ọdọ tileesẹ BBC ko jọ lati maa se bẹbẹ loju opo BBC Yoruba yi yaayi pupọ nitori wọn ni ọgbọn atinuda lati da ara. Ohun ti yoo si ti idi rẹ yọ ni agbekalẹ awọn iroyin meriiri nipa awọn eeyan, latọwọ awọn eeyan ati fun awọn eeyan e - ẹ ma binu, o ka mi lara ni, o sa yẹ ki ohun ti mo n wi ye yin. Ero awọn ikọ osisẹ BBC Yoruba Adedayo Owolabi: ""Mo ri ileesẹ agbounsafẹfẹ BBC gẹgẹ bii ibudo atọnisọna taa ba n sọrọ nipa eto igbohunsafẹfẹ lode oni. ""Ileesẹ BBC ni orisun iroyin to jẹ ajaabalẹ, bii ẹmu ogidi, iroyin otitọ, ti ko ni ẹja n bakan ninu, ojulowo iroyin ti kii se ẹbu atawọn iroyin ti wọn ko bu omi la, ti ko si ni ẹlẹgbẹ. Koda, idanilẹkọ wọn gan ko ni orogun. Ojurere Ọlọrun ni lati jẹ osisẹ BBC."" BBC n wo awọn iroyin ni fini-fini Olubayọde Alebiosu: ""Isẹ akoroyin jẹ ara igbe aye mi. Atipe, lọwọlọwọ bayi, Ileesẹ BBC Yoruba ni aye mi."" Adedayo Okedare: ""Ala to wa si imusẹ ni bi mo se darapọ mọ ileesẹ agbohunsafẹfẹ BBC, koda gan, o tete wa si imusẹ ju bi mo se seto rẹ lọ. Bi BBC si se pe mi fun ifọrọwanilẹnuwo jẹ iwuri fun mi. Mo jẹ alabukun fun lati jẹ ara mọlẹbi BBC to gbooro."" Joshua Ajayi: ""Nigba ti mo gbọ pe ileesẹ agbohunsafẹfẹ BBC fẹ da oju opo Yoruba silẹ, ọkan mi lọ sọdọ awọn babanla mi, ti wọn ko mọọkọ-mọọka lede oyinbo ati ilakaka wọn lati gbọ ojulowo iroyin to wulo. Mo ni itara fun ipenija tuntun yi. Koda, nko lee mu ara ro mọ."" Busayọ Akọgun: ""Ibẹrẹ ọtun fun isẹ akọroyin ti mo yan laayo ni bi mo se darapọ mọ ileesẹ agbohunsafẹfẹ BBC jẹ. Nse lo dabi ala titi taa fi bẹrẹ isẹ. Koda, inu mi si n dun dẹyin."" Funmi Jokotade: ""Ala to wa si imusẹ ni bi mo se darapọ mọ ileesẹ BBC yi. Nko mọ pe o lee gba ọna yi yọ. Inu mi dun gidigidi."" Yetunde Olugbenga: '""Nigba ti mo gbọ nipa agbekalẹ ikanni kan ti wọn pe ni BBC Yoruba, Mo ni whao, awọn tia ni eleyi. Se eyi wa lee jẹ ootọ bi lati ọdọ ileesẹ agba ọjẹ agbohunsafẹfẹ bii ti BBC? Sugbọn Ọlọrun nikan lo mu mi darapọ mọ wọn , ati pe emi ni mo n soju 'awọn ti a'.""",0,yoruba À_kọ́lé ojú-ìwé,0,yoruba "Nígbà tí Ọba fè mú, A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..",0,yoruba "se joko. Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Wábiwọ́sí ìyà ni Ajax fi ṣe Tottenham lálejo ni Amsterdam Ajax kọkọ gbo ewuro soju Tottenham nile wọn pẹlu ami ayo kan sodo ninu ipele akọkọ ifẹsẹwọnsẹ to kangun si aṣekagba idije Champions League. Bakan naa ẹwẹ, Ajax lo tun kọkọ gbayo meji wọle Tottenham ninu ipele keji ere bọọlu ọhun, ko to di pe ẹlẹsẹ ayo Lucas Moura dayo meji naa pada ni kete ti abala keji bẹrẹ. Lucas Moura, wo sunsun, lo ba tun f'ọba le pẹlu gbigba goolu kẹẹta sawọn Ajax , eyi to mu ki Tottenham pegede fun aṣekagba idije Champions League ti saa yii. Kcee fí ọwọ́ Jóná lóri Liverpool Vs Barcelona Sàǹgbá fọ́! Liverpool fí ogun ẹ̀yìn ja Barcelona Ilé ẹjọ́ kòtẹmilọ́rùn yóò dajọ́ ìdìbò gómìnà Oṣun ọdún 2018 Ajax ló kọ́kọ́ gbá góòlù méjì sáwọ̀n Ni bayii, Tottenham ni yoo koju Liverpool ninu aṣekagba idije Champions League ti yoo waye ni papa iṣere Real Madrid ni ọjọ kinni oṣu kẹfa ọdun yii",0,yoruba "A bí Yisa Sofoluwe ni ọjọ́ kejìlélógún, oṣù kejílá, ọdún 1967 to si gbá bọ́ọ̀lù fún orílẹ̀-èdè Nàìjíríà gẹ́gẹ́ bi a dile ẹyin mú. Ẹyìn ni apá òsì ni ìròyìn sọ pé ó máa ń gbá láàrin ọdún 1983 si ọdun 1988, bákan náà ló gbá Nation's Cup ọdún 1984 àti ti 1988 Sofoluwe jẹ góòlù kan fún orílẹ̀-èdè Nàìjíríà lásìkò náà. Ó farahàn nínú idíje bọ́ọ̀lù Nàìjíríà fún ìgbà ogójì lásìkò tó n gbá bọ́ọ̀lù Bákan náà ni Sofoluwe ti fi igba kan jẹ́ agbábọ́ọ̀lù Abiola Babes nílùú Abeokuta, IICC ti Ibadan àti Gatew+ay Abeokuta. Ṣááju ni ìròyìn kàn pé, àgbà ọ̀jẹ̀ agbábọ́ọ̀lù náà ṣe àìsàn to sì gba ìtọ́jú nílé ìwòsàn LUTH. Ọ̀kan ninu àwọn ọrẹ́ rẹ̀ Waidi Akanni sàlàyé pé, àwọn ń gbìyànJÚ láti wá owó tí yóò fi ṣe iṣẹ́ abẹ̀ tó nílò, ṣùgbọ́n ẹpa kò bóró mọ́. Ìròyin sọ pé mínísítà fún eré ìdárayá àti ọ̀rọ̀ ọ̀dọ́ lọ́sàn ọjọ́ Iṣẹgun gbé ìgbésẹ̀ láti ran Sofoluwe lọ́wọ́ láti bá gómìnà ìpínlẹ̀ rẹ̀ sọ̀rọ̀ kí wọ́n lé ràn an lọ́wọ́ lórí ọ̀rọ̀ iṣẹ́ abẹ náà. Mínísítà fí owó ránṣẹ́ pẹ̀lú láti fi ran ìtọ́jú rẹ̀ lọ́wọ́ sùgbọ́n kò dúró ṣe iṣẹ́ abẹ náà tó fi gbekuru jẹ lọ́wọ́ ẹbọra. Agbábọ́ọ̀lù ikọ̀ Super Eagles tẹ́lẹ̀rí Yisa Sofoluwe jáde láyé Agbabọọlu ikọ Super Eagles tẹlẹri, Yisa Sofoluwe ti jade laye ni ẹni ọdun mẹrinlelaadọta, lẹyin to ṣe aisan. Opin ọsẹ yii ni iroyin jade nipa aisan rẹ lẹyin ti wọn lo ni aisan ninu agbari, cerebral atrophy to niiṣe pẹlu ọpọlọ. Aisan yii ma n jẹ ki gbogbo sẹẹli ọpọlọ ni ifasẹyin, ti ọpọlọ ko si ni lee ṣiṣẹ mọ bi o ṣeyẹ. Sofoluwe ni agbabọọlu ẹyin to n dile mu nigba aye rẹ, ti gbogbo aye si mọ ọ si ""Dean of Defence"". Ọjọ Kejidinlọgbọn, Oṣu Kejila, ọdun 1967 ni wọn bi akọni naa to si gba bọọlu si awọn lẹẹkan fun orilẹede Naijiria. O gba bọọlu pẹlu ikọ to de aṣekagba idije AFCON ni ọdun 1984 ati ọdun 1988. Awọn akẹgbẹ rẹ ati awọn ololufẹ rẹ ni wọn ti n ṣe idaro rẹ lẹyin to papoda pe ki Edua de ilẹ fun ẹni ire to lọ.",0,yoruba àtẹ́lẹwọ́ la bálà a ò mẹni tó kọ ọ́ irọ́ ni wọ́n pa èdè yorùbá ò le è parun,0,yoruba "Awọn ara adugbo ni ṣadede ni ile na wo mọ awọn to n ṣiṣẹ nibe lori Iṣẹlẹ yi waye ni ọjọ meji lẹyin ti ile kan dawo lEko l'Ọjọru nibi ti ogun eeyan ti padanu ẹmi wọn. Ọga ajọ naa ni iwo oorun Guusu to n mojuto awọn ilẹ kaarọ ojiire eleyi ti Ibadan wa labẹ wọn Slakku Luggard lo sọrọ yi fun BBC. Content is not available End of Facebook post, 1 O ni eeyan meje lawọn doola labẹ ile na ṣugbọn ko si ẹnikẹni to padanu ẹmi nibẹ. Saaju, Ikọ BBC Yoruba kan si agbegbe ibi ti ile alaja mẹta naa ti da wo nilu Ibadan. Gẹgẹ bi ohun ti akọroyin wa jabọ ati ohun ti awọn ara adugbo sọ, eeyan mẹrindinlogun lo n ṣiṣẹ nibẹ nigba ti ile naa dawo. Ọga ọlọpaa nipinlẹ Ibadan Shina Olukọla na fi to awọn oniroyin leti pe awọn doola ẹmi eeyan mẹta nibẹ. Ile miran tun wo ni Ibadan Ni agbegbe Ṣogoye lẹgbẹ Molete ni iṣẹlẹ naa ti ṣẹlẹ. Kete ti o ṣelẹ lawọn kan ti ọrọ naa soju wọn ti fi ọrọ sita loju opo Twitter O sọ ninu ọrọ rẹ pe o ṣeeṣe ki awọn si wa labẹ awoku ile naa. Ẹgbọ́n olóògbé Suga: Wọ́n yìnbọn fún Suga lójú mi, n kò sì lè dá wọn dúró @TopsyAshaolu ti iṣẹlẹ ọhun ṣoju rẹ ni awọn oṣiṣẹ ajọ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri ko tete debi ti ile naa ti da wo lulẹ. Ẹnikan to n gbe agbegbe ti ile naa ti wo ṣalaye pe wọn si n kọ ile naa lọwọ ni",0,yoruba RT @user: Oro - Word Oro - Speech Oro - wail Oro - deity Oro - to think Oro - to mix Oro - to fall (rain) Oro - to be soft Oro - to…,0,yoruba gbé lọ yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà.,0,yoruba Ehín erin = ivory (ọ̀gbẹ́ni Philips àti ikọ̀ rẹ̀ jí ehín erin Ìbíní ➡️ Mr Phillips and his team stole Benin's ivory) #InYoruba #learnyoruba,0,yoruba Ìbàdandun ni ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn. (Item 138),0,yoruba Yọọ́kúrò láti inú àkọlé yìí,0,yoruba Ìfẹ̀hònúhàn ìtako ìṣèjọba Condé fún ìgbà kẹta ọjọ́ kan ṣoṣo tí mú ẹ̀mí àwọn ènìyàn lọ .,0,yoruba "Asofin Melaye ti figba kan korin 'Ajekun Iya' si awọn alatako rẹ ri ni ọdun 2017. Oludari ipolongo ati ẹkọ oludibo ni ajọ Inec, Ọgbẹni Oluwole Osaze-Uzzi, lo sọ eleyi di mimọ nigba to n ba amohunmọworan Channels sọrọ. Ọgbẹni Osaze-Uzzi sọ wi pe: ""Ni bayii wọn ti gbe gbogbo igi-idina ofin kuro lọna, ajo naa yo si tẹsiwaju bi ẹni wi pe ọrọ ile ẹjọ ko ṣẹlẹ ri."" Awọn oludibo iwo-oorun Kogi ti kọkọ f'ọwọ si wi pe ki wọn o pe sẹnẹtọ naa pada. Inec si bẹrẹ ipepada naa, sugbọn Melaye lọ si ile ẹjọ lati da ipepada na duro, amọsa o kuna nile ẹjọ naa. Lẹyin igba naa lo sọ wi pe ẹjọ ti ile ẹjọ naa da ko tẹ oun lọrun. Sugbọn ile ẹjọ to gbẹjọ naa lọ sọ wi pe ki ajọ Inec ma ba iṣẹ rẹ lọ. Ninu ẹjọ ti wọn da lọjọ Ẹti, awọn adajọ ile-ẹjọ naa l'aAbuja sọ wi pe ẹjọ ti Mẹlaye gbe wa ko l'ẹsẹ nlẹ. Akoroyin BBC gbiyanju lati gbọ tẹnu Dino Melaye, sugbọn asofin na ko gbe ipe to fi s'ọwọ si ẹrọ-ibani-sọrọ rẹ.",0,yoruba "Ní ìlú kan, Ìyá ni olùkó. ìrìn ìròyìn. A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..",0,yoruba "ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Nitori eyi, ara eni lo ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "Ọmọba Harry fi ọrọ yi lede nibi apejẹ kan to kopa nibẹ lọjọ Aiku Nibi apejẹ kan ti oun ati iyawo rẹ Meghan kopa nibẹ nirọlẹ ọjọ Aiku ni o ti sọ pe o wu awọn lati maa ṣiṣẹ sin yeye Ọba lai gba owo ṣugbọn ''ko le ṣeeṣe'' Eyi ni igba akọkọ ti yoo sọrọ nita gbangba lori ọrọ yii lati igba ti oun ati iyawo rẹ Meghan ti kede pe awọn fẹ yẹra kuro nile ọba. Ọmọọba naa ni oun ri ayọ ati idunnu ti oun ti n wa pẹlu Meghan ṣugbọn oun fẹ ki o ye awọn eeyan pe awọn ko lọ lai wẹyin wo. ''Ile ni ilẹ Gẹẹsi jẹ fun mi, ko si oun ti yoo si yi i pada'' Harry, iyawo rẹ ati ọmọ rẹ Archie ni Victoria lasiko ọdun Keresimesi to kọja Harry sọ pe ohun to n ṣẹlẹ n ṣafihan iru bi nkan ko ṣe rọrun fun oun eleyi to mu ki oun fi mọlẹbi oun pamọ lati le gbe igbe aye alaafia. Nibẹrẹ oṣu yii ni ọmọọba Harry ati Meghan sọ pe awọn fẹ yẹra kuro nipo gẹgẹ bi aṣaaju mọlẹbi ọlọba ilẹ Gẹẹsi tawọn si fẹ́ da duro funra awọn. Lọjọ Abamẹta ni ikede wa lati aafin Buckingham Palace pe wọn o ni maa lo oye ọlọmọọba wọn mọ ti wọn ko si ni kopa ninu awọn iṣẹ to jọ mọ jíjẹ́ ọmọ ọba. Wòó nínú àwòrán: ìgbé ayé Harry àti Meghan ṣáájú ìyapa kúrò nílé Ọba Ọmọọba Harry ati aya rẹ ti a mọ si Duke ati Duchess Sussex lẹyin igbeyawo wọn ni wọn ko ni lo orukọ oye ile ọla to jẹ ile Ọba UK mọ. Koda, wọn ko ni fọwọ kan owo ilu mọ ni ile Ọba ni Buckingham. Bakan naa ni wọn pinnu lati da miliọnu meji ati irinwo pọun ile UK ti ile Ọba fi ba wọn tun ile Cottage ti wọn n gbe lẹyin igbeyawo wọn ṣe pada Harry àti Meghan kò ní lo orúkọ oyè wọn mọ́, wọn kò sì lẹ́tọ̀ọ́ sí owó ilú mọ́ ní UK. Owó ara wọn ni wọn yoo maa na pẹlu ileri lati ma doju ti Ọbabinrin ninu iwa ati iṣe wọn nibikibi ti wọn ba wa. Lódun 2016 ni aafin Kessingtin fi atẹjade sita lati fidiẹ mulẹ pe lootọ ni Ọmọọba Harry ati oṣere binrin Meghan Markle ti n fẹ ara wọn lati oṣu diẹ sẹyin. Toronto ni wọn ti kọkọ fi aworan wọn ti wọn jọ ya papo sita. Ni kete ti wọn ṣe ikede ipinnu wọn lati fẹ ara wọn titi lae ni Meghan sọ fun BBC pe ọna ara to yanilẹnu, to mu ife dani, to tun dùn leti to wa tuni lara ni Harry gba dẹnu ifẹ kọ oun. Losu keji ọdun 2018, ni awọn tọkọtaya naa kopa ninu eto itagbangba pẹlu ẹgbọn rẹ Duke ati Duchess Cambridge. Nibẹ ni Meghan ti darapọ mọ ẹbi alayọ yii lati kopa ninu eto Royal Foundation Charity. Nibi eto yii ni Harry ti ṣe yẹyẹ pe Awọn mẹrẹẹrin a jọ wa pọ laelae ni. Lọjọ kọkandinlogun, oṣu karun un, ọdun 2018 ni wọn so awọn mejeeji pọ ni Windsor Castle. ero to le ni igba le ni ẹgbẹrun kan ni wọn fiwe pe sibi igbeyawo naa ti wọn si ṣafihan rẹ kaakiri awọn amohunmaworan ni UK. Ori ẹṣin ni tọkọtaya yii gun fi ki awọn ara ilu pe wọn ku aduroti lẹyin igbeyawo naa. O le ni ẹgbẹlẹgbẹ ero to to si oju opopona lati wa ki awọn t\ọkọtaya tuntun ti yoo maa ṣakoso Susex ni UK. 'A kẹ̀yìn sí Ivory Coast, owó yín ò lè máa jẹ́ ""eco"" táa ti mú fún àjọná owó ECOWAS' Ẹgbẹ́ kan fún Tinubu ní wákàtí mẹ́rìnlélógún láti sọ èrò rẹ lórí Amọtẹkun Lalekan Ayọkunnu Are jáde láyé Kínla! Ṣé olùkọ́ fásitì OAU míràn tún ti kó sí gbaga ìbálòpọ̀-fún-máàkì ni? Ile ijọsin St George Chapel ni tọkọtaya Harry ati Meghan ti jẹ ẹjẹ ootọ inu sira wọn titi iku yoo fi ya wọn niwaju Obabinrin ati ero to pọ pẹlu ayọ Wo àwọn ìbejì tó lẹ́ pọ̀ lẹ́yìn àṣeyọrí ìṣẹ́ abẹ dókìtà 70 Obabinrin Elizabeth, Duke ti Edinburgh ati awọn eekan mi ninu ile Ọba ni gbogbo wọn fi ayọ han nibi eto igbeyawo Harry ati Meghan pe o ṣoju wọn.Inu Ọbabinrin ati ọkọ rẹ dun pupọ lati ri ọmọmọ wọn ko gbe iyawo to wuu wọnu ile ọla loju aye wọn. Loṣu kẹfa, ọdun 2018 ni Obabinrin Elizabeth ati Olori Meghan kọkọ jọ fojuhan papọ nita. Awọn mejeeji jọ ṣi Gateway Bridge and Chester's Storyhouse Theatre nilu Ọba. Opọ ni ile Ọba ti t\wọ gab Meghan wọle lẹyin eto yii. Títí d'òní, Bàbá mi dara pọ̀ mọ́ iṣẹ́ ológun kò sí padà wálé - Grandma Biafra Lasiko ọyẹ ni ilé Ọba ni Kessington fi sita pe Meghan ti fẹraku ati pe wọn ko ni pẹ bi \omọọmọọmọ miran fun Ọbabinrin Elizabeth. Kete leyin ikede yii ni Harry ati Meghan bẹrẹ irinajo akọkọ wọn lọ silẹ okeere. Wọn lọ si Australia, New Zealand, Fiji ati Tonga papọ. Eyi ni ọkan lara awọran ti wọn ya ni Bondi Beach ni Sydney ni \Australia pẹlu awọn ololufẹ wọn. Ìtàn ìgbé ayé Bode Thomas rèé, ó kọ́ wa láti máa kó ẹnu wa ní ìjánu Ààfá mẹ́ta réwọ̀n hé nípa ṣíṣe ìrànlọ́wọ́ òjijì fún obìnrin kan pẹ́lù 36 mílíọ̀nù náìrà Harry àti Meghan kò ní lo orúkọ oyè wọn mọ́, wọn kò sì lẹ́tọ̀ọ́ sí owó ilú mọ́ ní UK Wo àwọn krìstíẹ́nì tó n wẹ̀ nínú odò tó ní yìnyín láti ṣàjọyọ̀ ìrìbọmi Jesu Lọjọ kẹfa, oṣu karun un, ọdun 2019, ọdun kan lẹyin igbeyawo wọn ni Meghan bi ọmọkunrin lantilanti sinu ile Ọba. Archie Harrison Mountbatten Windsor ni wọn sọ orukọ ọmọ tuntun o. Oun ni ẹni keje si itẹ Ọba ilẹ Gẹẹsi lẹyin Obabinrin elizabeth. Harry fi idunnu rẹ fawọn akọroyin pe iriri naa ti dara ju lati di baba ikoko. Loṣu kẹfa ọdun 2019 ni tọkọtaya yii ni awọn ko ṣe iṣẹ iranlọwọ papọ mọ pẹlu Duke ati Duschess Cambridge to jẹ égbọn Harry ati aya rẹ. Wọn ni awọn fẹ bẹr ti ara awọn lọtọ Super touch: Roller Blader ni mí láti ọdún mẹ́jọ sẹ́yìn Lọdun to kọja ni Archie omọ tuntun ti abi kọkọ rinrin ajo lọ silẹ Adulawọ. Wọn gbe e lọ ki Archbishop Desmond Tutu ni orilẹ-ede South Africa lasiko abẹwo wọn akọkọ gẹgẹ bii ẹbi kan. Omọọba Harry ati ọmọ rẹ Archie ni Canada ti wọn kede lati maa gbe lasiko yii Wo àwọn ìbejì tó lẹ́ pọ̀ lẹ́yìn àṣeyọrí ìṣẹ́ abẹ dókìtà 70 Aworan yii ni tọkọtaya Harry ati Meghan ya nile wọn ni Canada ṣaaju bibeere fun iyọkuro ninu iṣẹ ile Ọba ni eyit i Ọbabinrin Elizabeth ti tu wọn silẹ bayii pe o dabọ. Ile Ọba ni Haary ati Meghan ko ni maa lo orukọ oye wọn ati pe wọn ko ni maa na ninu owo ile Ọba mọ Gbogbo aworan yii lo ni awọn to ni wọn bi a ṣe darukọ wọn.",0,yoruba Tìí ní móòdù ojú kọ̀ǹpútà kíkún,0,yoruba "pataki. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọba lo ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba Ọlọ́pá YouTube naa ní ègé olóótọ fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ìyá lo tun se joko.,0,yoruba "Gomina Ayade to kede pe oun ti kuro ninu ẹgbẹ alatako PDP lọ si APC to wa lori alefa ni, ki ipinlẹ oun le jẹ anfaani mudunmudun ijọba apapọ loun fi ṣe bẹẹ. Ayade to ke gbajare ipenija orisirisi ti ipinlẹ rẹ n koju nipa ọrọ owo, ohun amayederun ati airiṣẹse awọn ọdọ tun sọ pe, isipo pada oun yoo mu ki awọn jẹ anfaani lọdọ ijọba apapọ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: O wa gba awọn Gomina akẹgbẹ rẹ miran niyanju, lati pawọpọ pẹlu aarẹ Buhari lati mu idagbasoke ba Naijiria. ""A nilo ki gbogbo awọn Gomina mọ wi pe eyi kii ṣe ọrọ ẹgbẹ oṣelu, jijẹ ọmọluabi ni, jijẹ ẹni apọnle si ni. Ifarajin si afojusun Naijiria naa si laa n sọ'' Aworan Gomina Ayade to kuro ninu ẹgbẹ PDP lọ si APC O ni ti gbogbo awọn ba pawọpọ pẹlu aarẹ ẹni ti yoo gba ijọba lyin rẹ lọdun 2023 ko ni ṣe wahala pupọ. Lọjọbọ yi ni Gomina Ayade kede pe ohun ko ṣẹgbẹ PDP mọ lẹyin ipade bonkẹlẹ kan to ṣe pẹlu awọn Gomina APC mẹfa. Ninu awọn to wa nibi ipade naa la gbọ pe awọn aṣofin ile asofin agba mii naa wa. Lara awọn Gomina to ṣabẹwo si nile ijọba la ti ri Gomina ipinlẹ Kebbi, Imo, Yobe, Plateau, Jigawa, ati Ekiti.",0,yoruba Gba agbára lọ́wọ́ Ìjáde Ipá,0,yoruba ilera ṣẹlẹ ni Eko ti gbogbo eniyan sọ o ṣe pataki. (2002),0,yoruba "Àwòrán láti ọwọ́ọ Jason Persse , CC BY - SA 2 . 0 .",0,yoruba nípa àìkú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé.,0,yoruba "Ọkùnrin onínúure kan , Sunday Adéníyì , ṣe agbátẹrù ìtẹ̀jáde 1 , 000 ẹ̀da ìwé ìgbẹ̀kọ́ “ Alífábẹ́ẹ̀tì Aèébáèjìogbè Odùduwà """""""" fún àwọn ọmọ iléèwé alákọ̀ọ̀bẹ̀rẹ̀ .",0,yoruba "Alaafia la wa o otutu die kan n mu ni nitori ojo ale ana""""""""""""""""@user: Ẹ kú ojúmọ́ o ẹ̀yin ẹ̀dá rere. Ṣ'álàáfíà ni? Ṣẹ́ dáadáa""""""""""""""""",0,yoruba "Ọmọ orileede Chile naa darapọ mọ Inter Milan fun saa ọdun kan lẹyin to lo oṣu mọkandilogun ni Old Trafford. Nigba to wa ni Man United, oun ni agbabọọlu to n gba owo ju lọ tii ṣe £400,000 lọsẹ. Ṣugbọn goolu marun un pere lo jẹ ninu ifẹsẹwọnsẹ marundinlaadọta to kopa ninu rẹ lati igba to de sọdọ wọn lati Arsenal loṣu Kini ọdun 2018. ''Inu mi dun pe mo lọ si Manchester United.Mi o ṣẹṣẹ ma s pe oun ni ẹgbẹ to ti gba ami ẹyẹ julọ ni ilẹ Gẹẹsi'' O salaye pe nigba ti oun lọ si Arsenal,o dun mọ oun ṣugbọn United n gboro si lasiko naa ti wọn si n ra awọn agbabọọlu tori pe wọn fẹ pegede. ''Mo fẹ darapọ mọ wọn lati gbogbo ife.Mi o kabamọ pe mọ lọ si ọdọ wọn'' Goolu ọgọrin(80) ni Sanchez jẹ ninu ifẹsẹwọnsẹ mẹ́rìndínláàdọ́sàn án (166) ni Arsenal lẹyin to buwọlu iwe adehun miliọnu ọgbọn poun lati Barcelona lọdun 2014. O gba ami ẹyẹ agbabọọlu to pegede julọ ldun 2017 ni Premiership. Amọ lati igba tokuro ni Arsenal lọ si Man United ni nnkan to ti rọgbọ mọ. Goolu meji pere lo jẹ ninu ifẹsẹwọnsẹ mẹtadinlọgbọn ni saa to kọja botile j wi pe o ṣe daada forileede Chile ninu idije Copa Amerika to ti jẹ goolu meji.",0,yoruba "Bi o tilẹ jẹ pe iṣẹ ilu ni Amaechi ba lọ si orilẹede Spain, Rotimi Amachi ni ọpọlọpẹ awọn ọlọpaa lo gba ohun silẹ lọwọ awọn ọmọ orilẹede Naijiria naa bi bẹẹ kọ, boya ẹkọ o ba ṣoju mimu fun oun. Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ Minisita fun eto irinna ilẹẹwa naa ni oun dupẹ lọwọ ori pe iwọn ni ikọlu naa mọ, oun ko si farapa, bẹẹ lo fi kun un pe awọn ọmọ orilẹede yii ti ọrs ko ye daadaa lo kọlu oun. Bi ẹ ko ba gbagbe, laipẹ yii ninu ọdun 2019 yii naa ni awọn ọmọ orilẹede Naijiria kan din dundu iya fun igbakeji aarẹ ile aṣofin orilẹede Naijiria tẹlẹ, Sẹnetọ Ike Ekweremadu lorilẹede Germany.",0,yoruba kè é ṣẹ̀hìn tí krìstẹ́nì dé la bẹ̀rẹ̀ sí í pe ọjọ́ lọ́jọ́ ọ̀sẹ̀ àyálò èdè ni ọjọ́ọ̀sẹ̀ ọjọ́ àkọ́kọ́ ọ̀sẹ̀ fún,0,yoruba Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó ṣe pàtàkì. (Item 83),0,yoruba "RT @user: @user @user @user @user @user ..iru petineesi wo wa leleyi? Ati Ogbeni ati Alagba,…",0,yoruba "Nígbà tí Ọba fè fi, Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..",0,yoruba #Alafia #AlafiaAtiIsokanFunGbogboEniyan #Yoruba #Langbasa #Lagos #Nigerian #African 👏🏼🙌👏🏼🙌👏🏼 Alafia ati isokan fun gbogbo eniyan https://t.co/4KdbaCGVtC,0,yoruba "Ìlú yorubá lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Nitori eyi, ara eni ni nfàn ojú kakaaki.",0,yoruba ènìyàn ni ó pa Bàbá lo ni àṣà yorubá eyti o gbe lori ọ̀run dídì.,0,yoruba nkan ti mo so fun awon ore mi niyen pe ki ilu to le yipada hun ise nla tori iwa ibaj,0,yoruba "Ní nígbà àkerekere, Ìyá ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé. ti Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Ohun ìdánimọ̀ pánẹ́ẹ̀lì tí a somọ́ dúrọ́wà yìí. Bọ́tìnì yìí kàn wúlò tí bọ́tìnì irúfẹ́_nǹkan bá jẹ́ ""nǹkan-dúrọ́wà"".",0,yoruba Coronavirus in Africa: WHO ní ìwádìí ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ yóò ṣèrànwọ́ láti pinwọ́ àrùn náà,0,yoruba "@user @user @user @user Nígbà tí nǹkan ò ṣe wọ́n, they will refund this one",0,yoruba "ìrìn ìròyìn. Nitori eyi, ara eni lo ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..",0,yoruba oníṣẹ́ ìṣẹ́ ni ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba Menstrual cycle and Covid vaccine: Ṣé ǹkan oṣù yín ń dà hìì hìì lẹ́yìn tẹ́ẹ gba aabẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19?,0,yoruba "lo fi. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "Orin ará abúlé kan; ♪ """"""""""""""""k'á jẹun k'á só fà á, oko lakúkú wà"""""""""""""""" ♪ #IseAgbeNiseIleeWa",0,yoruba "Ní ìlú kan, Ìyá ni olokìkì. ìrìn ìròyìn. Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba ẹkọ́ ṣẹlẹ ni Eko ti gbogbo eniyan sọ o ṣe pataki. (2007),0,yoruba "lọ. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "Nígbà tó kún jú, àwọn ènìyàn ni ó pa Ìyá lo tun se se.",0,yoruba kakaaki. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba "OIC n ṣepade Ọrilẹede mẹtalelaadọta ninu awọn orilẹede to jẹ ọmọ ẹgbẹ OIC lo jẹ awọn orilẹede ti awọn ẹlẹsin musulumi ti pọ ju. Ẹgbẹ OIC ni aṣoju ni ajọ iṣọkan agbaye ati ajọ ilẹ alawọfunfun ti wọn n pe ni European Union. Nigeria Population: Báwọn ọmọ Nàíjíríà ṣe ń pọ̀ si jẹ́ ìpèníjà fún Buhari Kinni erongba OIC? Gẹgẹ bi adehun ti wọn ṣe, ẹgbẹ OIC pinnu lati maa gbe ohun to jẹ mọ ẹsin musulumi larugẹ lawọn orilẹede to jẹ ọmọ ẹgbẹ naa. Ẹgbẹ OIC tun pinnu pe awọn yoo ṣe imugbooro aṣa ati imọ sayẹnsi lawọn orilẹede to jẹ ọmọ ọhun. OIC tun pinnu lati mu eto aabo lọkun-kundun ati lati lepa alaafia kaakiri gbogbo orilẹede ti ẹgbẹ naa wa. OIC tun pinnu lati maa ṣe igbelarugẹ eto ẹkọ imọ-ijinlẹ ni gbogbo orilẹede to jẹ ọmọ ẹgbẹ naa. Akitiyan OIC lori awọn to ṣatipo Ẹgbẹ OIC ti gbalejo awọn atipo bi miliọnu mejidinlogun lati igba ti ẹgbẹ ọhun ti wa titi di ọdun 2010 Awọn orilẹede to jọ ọmọ ẹgbẹ OIC ti n gbalejo awọn atipo lati awọn orilẹede ti rukerudo ti n ṣẹlẹ lati ọdun 2010 Kinni o mọ nipa OIC? Lọdun 2011 ni ẹgbẹ OIC yi orukọ rẹ pada Organisation of Islamic Conferencde ssi Organisation of Islamic Cooperation. Buhari mórí lé Saudi lẹ́yìn ìbúrawọlé fún sáà kejì Lẹyin iburawọle fun saa keji l'Ọjọru, Aarẹ Muhammadu Buhari mo ri le orilẹ-ede Saudi Arabia lonii Ọjọbọ. Aarẹ Muhammadu Buhari n lọ fun ipade OIC Aarẹ n lọ fun apero ẹgbẹ Organisation of Islamic Cooperation ti ọpọ mọ si OIC ti yoo waye lọjọ Ẹti niluu Makkah. Ọjọ keji, oṣu kẹfa ni Aarẹ Buhari yoo pada si orilẹ-ede Naijiria. Nigeria Population: Báwọn ọmọ Nàíjíríà ṣe ń pọ̀ si jẹ́ ìpèníjà fún Buhari Ninu atẹjade ti oludamọran agba fun aarẹ lori ọrọ iroyin, Garba Shehu sita, Aarẹ Buhari yoo sọrọ nibi apero ọhun. Atẹjade naa sọ pe aarẹ yoo sọrọ lori iṣepataki ki awọn orilẹ-ede to jẹ ọmọ ẹgbẹ OIC wa ni iṣọkan lati le jọ koju ipenija bi awọn agbesumọmi ti wọn n da rogbodiyan kalẹ kaakiri. Aarẹ Buhari yoo tun sọrọ lori anfaani to wa nibi idokowo awọn orilẹ-ede ilẹ okere ni Naijiria. Àgbà ni Obasanjo, oun tó ń sọ yé e, ìjọba ni kó tají - Wale oke Buhari ni aarẹ orilẹ-ede Naijiria kẹta ti yoo lọ fun apero ẹgbẹ OIC lẹyin oloogbe aarẹ tẹlẹ ri, Umaru Yar'Adua ati aarẹ ana, Goodluck Jonathan ti kọkọ lọ fun irun apero bẹẹ. Gomina ipinlẹ Jigawa, Mohammed Badaru Abubakar, Gomina Oṣun, Gboyega Oyetola ati Gomina ipinlẹ Niger, Abubakar Sani Bello wa lara awọn ti yoo kọwọ rin pẹlu aarẹ lọ ilẹ Saudi. Ẹni bá láyà kó wá wọ̀ọ́! Ta ni Ìgè Àdùbí nílẹ̀ Oodua?",0,yoruba "Eye Bank in Lagos: Ibùdó ìtọ́jú ojú ní kẹ fi ẹyinjú yín sílẹ̀ tẹ bá kú, àwọn kìí fojú ṣe ètùtù tàbí rúbọ",0,yoruba iyalẹnu wey ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba "àtọ́wọ́dá, àwọn oníṣẹ́ ìṣẹ́ ni a ní nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó wáyé..",0,yoruba ó pa Ọmọ lo ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba ibile. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọba lo lọ.,0,yoruba "@user: @user E ma seun o! Odun uo a da fun wa o!"""""""""""""""" Àmín ẹ̀ pọ̀",0,yoruba oòrùn ń tàn gbà láti ibi tí ẹnìkan kò mọ̀ .,0,yoruba Dunsin Oyekan sọ̀rọ̀ lẹ́yìn tó móríbọ́ nínú ìjàmbá ọkọ̀,0,yoruba "Òmíràn nínú àwọn ìròyìn - in wa ṣàlàyé bí àwọn ọmọ orílẹ̀ èdèe China tí ó wà lórí ayélujára ṣe máa ń fi ìpalẹ́numọ́ ṣeré àti wá ọ̀nà àrà tí wọ́n máa ń gbà sọ nípa ìṣẹ̀lẹ̀ náà láì dárúkọ rẹ̀ , bí wọ́n bá sì fi ọwọ́ọ ṣìgún òfin mú wọn , ìjìyà ojú ẹsẹ̀ tí ó kọjáa kékeré ni onítọ̀hún yóò jẹ ní agodo ọba .",0,yoruba "Yoruba ni ajeje ọwọ kan ko gbe ẹru dori, nitori naa lo fi se pataki lati maa ran ara wa lọwọ. Olukọ wa lọsẹ yii, Arabinrin Funke aya Falade-Young si ti wa nikalẹ lati kọ wa nipa orisirisi asa iran ara ẹni lọwọ to wa ati anfaani wọn. Olukọ wa salaye lori ilana sise Ajọ, Aaro ati Ọwẹ lati fi ran ara wa lọwọ ati iyatọ to wa laarin wọn. Bakan naa la tun mọ nipa awọn ọna ta le gba lati san eto yii pada laarin awọn eeyan to ba n kopa ninu rẹ. Arabinrin Funke Falade-Young salaye ni kikun fun gbogbo wa bi asa iranraenilowo se se pataki nile Yoruba Ẹ fi ara balẹ, kẹ maa ba olukọ wa bọ, lati kẹkọ nipa asa ilẹ Yoruba to da lori eto riran ara ẹni lọwọ.",0,yoruba ìlú.. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọba lo ni iwa rere lojiji.,0,yoruba òní lọjọ́ ajé tó àkọ́kọ́ ńnú oṣù ọ̀wẹwẹ̀ torí ìdí èyí ṣẹ̀ṣẹ̀ ni kájé yọ̀ mọ́ mi ewé ọ̀yọ́yọ́ ló ní kí o máa yọ́nú sí mi ewé ojúṣàájú ló ní kí aráyé máa fi oore gbogbo ṣe ìṣáájúù mi ewé àánú ló ní kí aláàánú ó máa ṣàánúù mi àṣẹ àṣẹ àṣẹ,0,yoruba Gẹ́ẹ̀sì(_US-ASCII),0,yoruba Ogún mélòó ló wà nínú ọgọ́rùn-ún méjì? #Ibeere #Yoruba,0,yoruba "Ọba fè lọ, Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba "àìlẹ̀, Ìyá ri Nitori eyi, ara eni lo ni ẹ̀ká àwẹ eyti o gbe lori ọ̀run dídì.",0,yoruba Ìdáhún sí ìbéèrè àló òsè tó kojá rè o👉 Ęní/ìbùsùn 👏👏 #ÀàlóYorùbá #Yorùbádùn #wevaluemoral #Yorùbáculture #Besttribeever. #weappreciateourculture #yoruba #yorubademons #alo #àló… https://t.co/c4f1DaYu1T,0,yoruba ìwé orisirisi. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò.,0,yoruba "Ó yẹ kí a rí i bíi “ ẹ̀san """""""" láti apá ọ̀dọ̀ àwọn ẹ̀yà Hausa , Fulani .",0,yoruba sí ìbàdandun láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba agba a yi lo ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Alàji lo joko.,0,yoruba "yìí ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìṣẹ́ ọ̀pọ́lọ̀.",0,yoruba ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba gúdù mọọnì sà adúpẹ́ mo gbéyìnbó o gúdù mọọnì mà adúpẹ́ mo gbéyìnbó o ẹ káàárọ̀ o ẹ̀yin ọ̀rẹ́ a kú atura o,0,yoruba "ìgbà mi owó àkokò, Bàbá lo ni iwa rere lojiji.",0,yoruba "‘Lóòtọ́ làwọn kọmíṣọ́nà kó ọkọ̀ ìjọba lọ ṣùgbọn gómìnà àná, Oyetọla fọwọ́ síi’",0,yoruba àwọn ẹ̀gbá ka ìtakété sókè ìkòròdú sí ohun àbùkù sí ẹ̀gbá ní ìbẹ̀rẹ̀ ọdún ẹ̀gbá rán ọmọ ogun ẹgbẹ̀fà sí ìkòròdú láti pa ìlú náà run àwọn ọmọ ogun ẹ̀gbá rọ̀gbà yí ìkòròdú ká nígbà tí ọ̀rọ̀ yìí dé etí ìgbọ́ ìjọba britain wéré ni wọ́n,0,yoruba "agbègbè tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba National Sports Festival: Ìjọba àpapọ̀ ní kò sí ohun tó jọ pé ìdíje náà yóò párí l'Ọ́jọ́bọ̀,0,yoruba "àìmọ́. Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.",0,yoruba asin. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.,0,yoruba Àwòrán láti ọwọ́ọ Muhammadtaha Ibrahim Ma'aji tí ó jẹ́ àṣẹ ìlò CC BY 2 . 0 .,0,yoruba Èkó yii nípa èkó aṣà lo je ti ibile.,0,yoruba "Ọgba ẹwọn to wa ni ilu Lahore ni igbẹjọ naa ti waye labẹ eto aabo to l'agbara Abid Malhi ati Shafqat Ali Bagga fi ipa ba obinrin kan to jẹ ọmọ orilẹ-ede Pakistan ati France lopọ. Iroyin sọ pe wọn pade obinrin naa lasiko ti epo bẹtiro tan ninu ọkọ arabinrin naa ni opopona kan nilu Lahore. Dipo ki wọn ran lọwọ, niṣe ni wọn fi ipa wọ inu ọkọ rẹ, wọn ja a lole, wọn si tun fi ipa balopọ loju awọn ọmọ rẹ mejeeji. Ọrọ ti ọlọpaa kan sọ lẹyin iṣẹlẹ naa, pe kini obinrin naa n wa nita lasiko naa lai si ọkunrin kankan pẹlu rẹ ti fa iwọde nla ni Pakistan. Iru iwọde to tẹle iṣẹlẹ naa ko waye ri ninu itan orilẹ-ede Pakistan Amọ ni ọjọ Satide, ile ẹjọ kan nilu Lahore sọ pe Abid Malhi ati Shafqat Ali jẹbi ẹsun ifipabanilopọ, ijinigbe, idigunjale ati igbesunmọmi. Adajọ si dajọ iku fun wọn. Agbẹjọro wọn sọ pe wọn yoo pe ẹjọ kotẹmilọrun lori idajọ naa. Bawo ni iṣẹlẹ naa ṣe waye? Ọjọ kẹsan-an, oṣu Kẹsan-an, ọdun 2020 ni obinrin naa kagbako awọn afipabanilopọ yii. Ẹnu irinajo lo wa, ti epo ọkọ rẹ fi tan. O pe ẹbi rẹ kan to gba a nimọran lati pe nọmba ajọ pajawiri to wa ni opopona naa, oun funra rẹ si ti n bọ lati wa ran an lọwọ. Gẹgẹ bi ẹsun ti mọlẹbi rẹ kan kọ ni agọ ọlọpaa, niṣe ni ọkunrin meji fi tipatipa wọn inu ọkọ ti oun ati awọn ọmọ rẹ duro si, ti wọn si ji owo ati ẹṣọ ara rẹ. Wọn tun fi ipa ba a lopọ ni ori papa kan to wa nitosi loju awọb ọmọ rẹ, ki wọn o to salọ. Botilẹ jẹ pe ibanujẹ ọkan mu obinrin yii, o gbiyanju lati ṣapejuwe awọn to kọlu. Iwọde nlanla loriṣiriṣi to waye lẹyin ti ọga ọlọpaa ilu Lahore, Umer Sheikh fi ọgbọn sọ pe ẹbi obinrin naa ni nkan to ṣẹlẹ si, ko ṣẹlẹ ri ni orilẹ-ede Pakistan. Lẹyin iwọde yii ni wọn ṣe ofin tuntun lori ifipabanilopọ, eyi to faaye gba igbẹjọ ni kiakia, ati idajọ alailaanu.",0,yoruba "àkerekere, Ọba ri Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba "Gbajumọ oṣere sinima Yoruba, Eyiwunmi Muka Aramide ti ọpọ mọ si Muka Ray ti darapọ mọ oṣelu bayii pẹlu bi gomina ipinlẹ Kwara, Abdulrazaq Abdulrahaman ṣe yan an gẹgẹ bii amugbalẹgbẹ agba lori ọrọ aṣa ati irinajo afẹ. Gbajumọ onitiata to lokiki ni Muka Ray, ọmọ agbegbe idibo wọọdu Ipetu/ Rore/ Aran-Orin ni ijọba ibilẹ Irẹpọdun si ni. Ijọba ipinlẹ Kwara kede orukọ Eyiwumi Muka Aramide ati ipo tuntun ti wọn yan an si l’Ọjọbọ. Ṣaaju iyansipo rẹ, gomina Abdulrazaq kan naa ti yan eekan elere sinima miran, Fẹmi Adebayọ si ipo amugbalẹgbẹ pataki lori ọrọ aṣa, iṣe ati irinajo afẹ lọdun 2016. Ikede iyansipo Muka Ray tun tọka si ara igbesẹ akọtun eyi to n fihan bi awọn eekan elere sinima lorilẹede Naijiria pẹlu ṣe ti n lẹnu ninu ọrọ oṣelu lorilẹede Naijiria. O n tọ ipasẹ awọn oṣere bii Bukky Wright to dije fun ipo ile aṣofin apapọ lọdun 2014. Bukky Wright dije labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu SDP nigba naa. Desmond Elliot to wa nile aṣofin ipinlẹ Eko bayii.  Desmond Ellio lo n ṣoju ẹkun idibo Surulere nile aṣofin ipinlẹ Eko bayii labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu APC. Olubankọle Wellinghton ti ọpọ mọ si Banky W to n dije fun ipo aṣojuṣofin lẹgbẹ oṣelu PDP fun eto idibo apapọ ọdun 2023 pẹlu Funkẹ Akindele ti ọpọ mọ si Jennifer to n dije gẹgẹ bi igbakeji gomina nipinlẹ Eko labẹ ẹgbẹ oṣelu PDP.",0,yoruba ọmọ ò lè ṣe kí ó má fọ èdè ẹ ni ará yóò sọ àwa ni a ò fẹ́ sọ yoòbá a má ń form gan an ̀báronu,0,yoruba "Lára ìṣekúṣe lati mú oníṣekúṣe, ẹlẹ́yà ni a ti rí ẹlẹ́lẹ́yà. Ọ̀rọ̀ wo la yọ láti ara ìrégbè, adúgbò, ojúkòkòrò? #Ibeere #Yoruba",0,yoruba "Baàlè mú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba Omoluabi wa ni ìgbà àkerekere lo je ti ibile. Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.. A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba iṣẹ́: ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó wáyé..,0,yoruba da ti o nuni ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọba lo tun se mú.,0,yoruba àmọ́ nígbà tí mo wòye títí mo wá mọ ìdí abájọ tí ó fi rí bẹ́ẹ̀ ó wá yé mi wàyí pé ọ̀dọ̀ ẹni là á kọ ebè sí àti pé bù fún mi kí n bù fún ọ làkèré ń ké lódò wọ́n ń dami síwájú kí wọ́n ba tẹlẹ̀ tútù,0,yoruba eni tii o see oju koo dabii eni tii o see eyin ede dun,0,yoruba "Ilumọọka agbẹjọro, Jiti Ogunye to ba BBC sọrọ lo fidi ọrọ yii mu lẹ. Ogunye ni ""melo ni eeyan bi Bobrisky lorilẹede Naijiria ti ijọba yoo fi kọ ile igbọnsẹ ọtọ fun wọn."" Agbẹjọro Ogunye ni, ọrọ runrun lọrọ naa nitori iṣoro to n koju orilẹede Naijiria pọ ju pe, ki ẹnikan maa sọ pe o yẹ kawọn ko ṣakọ, ko ṣabo ni ile igbọnsẹ ti wọn lọtọ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Amofin Ogunye ṣalaye pe, ofin ilẹ Naijiria gan an ko faye gba awọn ko ṣakọ ko ṣabo, nitorinaa, iru eleyi ko le fẹsẹ mu lẹ. Ijọba apapọ lo kọkọ fi ikilọ lede nipa ewu to wa ninu kawọn eeyan bii Bobrisky maa ba awọn obinrin lo ibudo igbọnsẹ papọ. Ikede yii waye lẹyin ti rogbodiyan ṣẹlẹ ni papakọ ofurufu Nnamdi Azikwe ni ilu Abuja, nigba ti wọn ri Bobrisky to n lo yara igbọnse awọn obinrin. Ijọba wa rọ ẹka ilera lorilẹede Naijiria lati la awọn eniyan lọyẹ nipa ewu to wa ninu lilo yara igbọnse kan naa pẹlu Bobrisky, ti awọn eeyan kan si daba pe, ki wọn pese ile igbọnsẹ ọtọ fun awọn eeyan to jẹ ‘Kosakọ-Kosabo’ bii Bobrisky ati Miss Sahhara lawọn ibudo ajọlo. Ṣugbọn amofin Ogunye ni awọn iṣẹlẹ bi awọn ọlọpaa ti wọn n ko awọn ara ilu satimọle lainidi, ọna ti ko dara, iṣekupa awọn ọmọ Naijiria lorilẹede India lo yẹ ki ijọba wa nnkan ṣe si bayii. Agbẹjọro Ogunye ṣalaye siwaju si pe, ofin Naijiria si n ri Bobrisky gẹgẹ bi ọkunrin ayafi to ba lọ ṣe ibura nile ẹjọ pe oun fẹ yipada lati ọkunrin si obinrin. O fikun ọrọ rẹ pe awọn agbofinro lẹtọ lati fọwọ ofin mu un to ba lọ si ile igbọnsẹ awọn obinrin ni Naijiria.",0,yoruba "- kí a kọ GB àti P - ìlà kékeré sí ìsàlẹ̀ fáwẹ̀lì ẹ, ọ, àti kónsónàntì ṣ - ọ̀rọ̀ tí ó gbọdọ̀ parí pẹ̀lú 'ọn' àti 'un' - àmì orí ọ̀rọ̀; òkè tàbí ìsàlẹ̀ àti àmì ọ̀rọ̀ tí a fà gùn, fún àpẹẹrẹ: ilêwé, õrẹ̀ abbl - n gbọdọ̀ wà pẹ̀lú nwọn, ẹnyin",0,yoruba "Ṣugbọn ta ni ọkunrin yii to n pe ara rẹ ni Jesu gan an, ati pe kinni o n ṣe kaakiri ilẹ adulawọ? Ọpọ eeyan lo ti n pin aworan ati fọnran ọkunrin yii lori ayelujara, koda aṣofin kan lorilẹede South Africa, Julius Malema sọ pe, alufa ijọ kan lorilẹede ọhun gbalejo Jesu yii, lati wa ṣe iwaasu ninu ijọ rẹ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Amọ, awọn aworan to lu ayelujara pa ọhun wa lati ibi ayẹyẹ kan niluu Kiserian, lagbegbe Nairobi lorilẹede Kenya. Orukọ ọkunrin eke Jesu yii ni Michael Job, o jẹ ọmọ orilẹede Amẹrika. Oniwaasu ni, bakan naa lọ jẹ oṣere tiata. Ilu Orlando nipinlẹ Florida ni ọkunrin ọhun n gbe, nibi to ti n ṣe bii Jesu. Isọ ti wọn ti n ta aga ijoko ati nnkan ọgbin lo wa ninu fidio to fi sita lori oju opo Facebook rẹ. Ọpọ eeyan lori ayelujara lo ti n fi awọn aworan ọkunrin yii ṣe ẹfẹ ati bi awọn alufa ijọ kan nilẹ Afirika, ṣe maa n ṣe iṣẹ iyanu. Ọkan lara awọn aworan yii ṣafihan bi alufa kan lorilẹede Kenyan sẹ sọ wi pe, oun ri Jesu to rin loju popo ni Kenya. Michael Job ṣeleri wi pe, oun n ṣiṣẹ iyanu ati imularada ninu awọn fọnran iwaasu rẹ lorilẹede Kenya, bo tilẹ jẹ pe ọpọ lo koro oju si ọrọ yii. Kii ṣe igba akọkọ ree ti Ọgbẹni Job wa si ilẹ Afirika, o ti wa si orilẹede Togo nibẹrẹ ọdun yii ṣugbọn ko wọ iru aṣọ bayii nigba naa, kootu lo wọ.",0,yoruba ekaaro gbogbo omo kootu ojiire eni ni jimoo oloyin oyin ati adun ko ni wonle gbogbo wa o,0,yoruba "Genevieve Nnaji gba awọn obinrin ni imọran ohun loju opo ikansiraẹni Facebook rẹ. Genevieve woye pe ""ẹni to ni Ibalopọ pẹlu rẹ le ma nifẹ rẹ, bakan naa ẹni to ni ifẹ rẹ denu le ma ni Ibalopọ pẹlu rẹ."" ""Ẹyin obinrin ẹ ronu o, ọkunrin to korira rẹ le ba ọ sun,"" Genevieve kilọ. O ni ofuutu fẹẹtẹ lasan ni erongba awọn obinrin kan to gbagbọ pe awọn le fi nini ibalopọ pẹlu ọkunrin mu un mọlẹ lati fẹ wọn gẹgẹ bi aya. Genevieve ni ""itanra ẹni jẹ ní kí obinrin maa ro pe oun le mu ki ọkunrin nifẹ oun nipa fífi ara rẹ silẹ fun Ibalopọ."" O ni ""ifẹ aiṣẹtan kii fi tipa mu obinrin lati ni Ibalopọ pẹlu rẹ."" Genevieve sọ pe ""ọkunrin to ba ni ki o fi ìfẹ hàn s'oun nipa Ibalopọ n lo ẹ ni, yóò ja ẹ ju silẹ to ba ti ri ẹlomiran to gbadun Ibalopọ pẹlu rẹ ju ẹ lọ."" ""Iwa omugọ ni ki obinrin sọ ara rẹ di ẹru ọkunrin fun Ibalopọ,"" Genevieve lo sọ bẹẹ. O rọ àwọn obìnrin tí wọn ba ti n gbero lati fi Ibalopọ de ọkunrin mọlẹ pe ki wọn tun ero wọn pa, ki wọn si ṣe ipilẹ tuntun fun Irinajo ifẹ wọn. Genevieve fikun ọrọ rẹ pe ""ewu n bẹ loko longẹ fun igbeyawo ti ọkunrin ba fẹ obinrin nitori Ibalopọ."" ""Gba lati fẹ ọkunrin to ba nifẹ rẹ denu, jẹ ki ọkunrin naa bu iyì fun ẹ, ki o si ṣetan lati lo gbogbo igbesi aye rẹ pẹlu rẹ,"" ọrọ ree lati ẹnu Genevieve.",0,yoruba "Amin o ati eyin naa se daadaa ni""""""""""""""""@user: E k'aaro n beye o! Owo wa ma r'oke l'ose yii :)""""""""""""""""",0,yoruba ojú onà. ti Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "🎶🎵 Olùtùnú mi l'ójẹ́, nínú gbogbo wàhálà Óní kí n kó àníyàn mi l'ón lórí Òun ni ìtànná ipadò, ìràwọ̀ òwúrò Òn nìkan larewà ti ọkàn mi fẹ̀. 🎺🎸🎷 #MySongForTheRestOfTheYear #HappySundayFamilyAndFriends #yoruba #ÈdèYorùbárẹwà #ỌMỌLÚWÀBÍÈKÌTÌ https://t.co/QuRSsQs6Cd",0,yoruba @user Òwe yìí báwa wí gidi-gidi ní àkókò tí a wà yí o. Ẹ ṣeun gan-an ni!,0,yoruba Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó ṣe pàtàkì. (Item 98),0,yoruba Omoluabi wa ni èkó aṣà lo je ti ibile.,0,yoruba "Ripẹtọ peters yinbọn pa Angela Igwetu ni ọjọru ọsẹ yii, lalẹ o ku ọla ti yoo pari agunbanirọ rẹ Bakan naa ni ileeṣẹ ọlọpaa ni Ripẹtọ Bẹnjamin Peters yoo tun fi oju ba ile ẹjọ. Kọmiṣọna ọlọpaa nilu Abuja, Sadiq Bello lo ṣalaye ọrọ yii nilu Abuja. Kọmiṣọna ọlọpaa Sadiq Bello ni 'atimọle ni o wa bayii ni ireti ibẹrẹ igbẹjọ rẹ'. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: O ni ko si idi fun Ripẹtọ naa lati yinbọn ati pe awawi ti ọlọpaa naa n ṣe pe agunbanirọ ọhun n pariwo fun iranlọwọ kii ṣe idi fun ibọn yinyin. O ni awọn ọkunrin meji to wa ninu ọkọ naa sọ pe ile igbafẹ ni awọn ti n bọ pẹlu agunbanirọ to di oloogbe naa ki o to yọ ori sita lati inu ọkọ ati pe ko si ewu kankan to wu ki ọlọpaa naa to yinbọn. Linda Igwetu ti ọlọpàá yinbọn pa ni Abuja ""Ileeṣẹ ọlọpaa ti gbe igbesẹ gbogbo to yẹ, ọlọpaa ti yinbọn ti wa lahamọ, igbesẹ gbogbo fun ibaniwi ni a si ti pari. Iṣẹ ti bọ lọwọ rẹ, o si ti farahan niwaju ile ẹjọ. O ti wa latimọle ni ireti igbẹjọ rẹ."" Kọmiṣọna ọlọpaa nilu Abuja ni ileeṣẹ ọlọpaa ko jẹ fi ọwọ pa oṣiṣẹ rẹ to ba tapa si ofin lori nitori gbogbo igba ni wọn n tẹẹ mọ wọn leti pe iwa ọmọluabi ṣe pataki lẹnu iṣẹ. LASTMA: Ẹ̀rí la nílò láti fi òsìsẹ́ tó ń gba rìbá jófin Ìjà ọlọ́pàá àti alápatà ni Bodija gbẹ̀mí Sulia aláìṣẹ̀ ni UCH",0,yoruba "èrò àti àsà tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Ẹ̀yin ti Yanki, kò tíì tán ooo. Ilẹ̀ ò wulẹ̀ tíì ṣú níhà ibẹ̀un. Ẹ̀yin ti Kúbà àti Brasil bákannan. Ó tún kù ni ìbọn ń ró. #TweetYoruba",0,yoruba Alaye she mo le ri fuel die n be 😀😀 #Yoruba #Lasisi @user,0,yoruba @user wípé ọmọbìnrin ọgọ́ta; 60 tún ti di àwátì ní #Kummabza #Damboa #Borno o :(,0,yoruba "Nígbà tó kún jú, àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún gbogbo.",0,yoruba "se lọ. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọba lo ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "RT @user: Ẹ gbọ́ o. Eré ni àwàdà ni, àwọn ẹ̀fọn wọ̀nyí gan-an, ó dàbí pé ògùn ò rànwọ́n mọ́ o. A fí wọn, wọn ò kú. Nkan mà wá d ...",0,yoruba ọkunrin ri pe ṣe iyalẹnu wey ti o wulo.,0,yoruba "Wọn mọ ẹbi Joshua daadaa ni ilu Sagamu, ti wọn si mọ itan awọn baba nla rẹ daadaa. Baba-baba-baba rẹ ni Daniel Adebambo Joshua, ọlọrọ onilẹ ati oniṣowo ti wọn gbagbọ pe o yan orukọ kẹta rẹ nigba to di ọmọlẹyin Kristi. Daniel ran ọmọ rẹ kan nileewe nilẹ Britain, nibẹ lo ti fẹ obinrin Irish kan to ba a wale pada si Naijiria nibi ti wọn ti tọ ọmọ meje. Ọkan lara awọn meje ọhun ni Robert to fẹ Yeta Odusanya lati ilu Sagamu kan naa, ohun si ni baba Anthony ati aburo rẹ, Janet. Orukọ mii ti Anthony n jẹ ni Olaseni. Awọn aṣeyọri rẹ ninu jija ẹṣẹ fihan pe idile rẹ gbajumọ tayọ ilu wọn nikan de gbogbo orilẹede Naijiria. Pẹlu iyi lo fi maa n pọn orilẹede rẹ le nibikibi to ba wa, asia Naijiria ko le ma fẹ lẹlẹ nibi to ba ti n ja, koda aworan Afirika wa gbagada lapa rẹ. O maa n fihan pe oun fẹran awọn ounjẹ ibilẹ Naijiria gan Bi o ṣe fẹran Naijiria to, o ko ounjẹ ranṣẹ sile fun awọn idile ti Coronavirus ṣakoba fun. O jẹ ẹni to lẹkọ ile pẹlu ọrọ pẹlẹ lẹnu ati ẹrin musẹ to maa n di ẹrin keekee. O nira ki Anthony ma bori to ba ja ẹṣẹ tori naa irawọ to tan jade wa lati Naijiria ni ọpọ ka a si, eyii si mu ki ọpọlọpọ ololufẹ rẹ lati Naijiria fẹran rẹ gan. Ero maa n wọ ni nibi iworan ti wọn ti maa n wo ija Anthony Joshua ni Sagamu, koda Joshua tun ni ẹgbẹ awọn alatilẹyi n tirẹ ni Sagamu. O to ẹgbẹrun mẹwa ololufẹ rẹ to wo ija kan, koda awọn kan rinrinajo lọ wo o. Bi Joshua ko tilẹ ṣe raye ri ipade ṣe pẹlu awọn ololufẹ rẹ nigba to wale ninu oṣu keji, ko sẹni to binu si i, ṣugbọn o ri ọba ati awọn ijoye ko to pada. ""Ko si iyọnu, ọmọ wa naa ṣi ni, aṣoju wa si ni,"" ọkan lara wọn, Okunore lo sọ bẹẹ. ""Mo mọ pe o tan mọ Watford amọ ọmọ ilu wa ni baba ati baba baba rẹ ati babaa babaa babaa rẹ"". Iwuri ni Joshua Ọpọ ọdọ ni ẹkun Guusu-Ila Oorun lo ti n fi Joshua ṣe awokọṣe pẹlu bi wọn ṣe n wo o ti wọn si n farabalẹ kọ bo ṣe n goke. Ẹni ọdun mọkanlelogun kan, 'Lekan the Engine' Muibi to jẹ mọkaliiki ni Ooṣa ni Joshua jẹ si oun. ""Mike Tyson gangan lo mu mi fẹran jija ẹṣẹ amọ Joshua lo n ti mi soke pe mo lee moke tori ọmọ Naijiria bii emi loun"".",0,yoruba "Irọ́ baba irọ́! Olé, baba olé! Èké baba èké! #Britain #Europe",0,yoruba ènìyàn a yi yi ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò.,0,yoruba Kókó ìròyìn àkọ́kọ́ 1 .,0,yoruba "@user ní #WEFAfrica. Ó ní àgbẹ̀ náà lè wọ ago #Rolex, pé kí àwọn ọ̀dọ́ #nigeria ó ṣe àgbẹ̀ #Abuja",0,yoruba "gbé joko yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba yi yi ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ àti ìbi tí wọn wà.,0,yoruba agba ri pe jẹ́ pàtàkì wey ti o nuni ti o lẹ.,0,yoruba ".@user ti wa di alagbafo fun @user lori oro ibo egbe @user ni ipinle eko. Ogbeni @user ati Gomino @user yio fi igba gbaga ni ojo keta, osu kewa, odun 2018 https://t.co/93q0MqLQZV",0,yoruba "Èkó yii nípa ìwé ẹ̀kó ni nfàn ojú kakaaki. Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "RT @user: Abi o. K'Olorun so wa, ki aa ri odun titun l'ayo ati alaafia o RT""""""""""""""""@user: Ọdún ń yí lọ biribiri.""""""""""""""""",0,yoruba "àìlẹ̀, Olùwo ri Nitori eyi, ara eni lo ni ẹ̀ká àwẹ eyti o gbe lori ọ̀run dídì.",0,yoruba "RT @user: """"""""""""""""M.K.O ọmọ Yorùbá rere, sun re o!!! Ẹ kú iṣẹ́ o @user, @user ṣàduà pé kí ọjọ́ yín ó dalẹ́. Àṣẹ http://t.co/GVWFLTI…",0,yoruba RT @user: @user @user @user @user @user @user Oniro ni yin e ko si Mon tin en se pelu eyin…,0,yoruba "Oludije fun ipo gomina labẹ asia ẹgbẹ́ oṣelu African Action Congress (AAC) ninu idibo ipinlẹ Ekiti ti yoo waye lọ́jọ́ kejidinlogun, oṣu Kẹfa, ọdun 2022, ni Ajagunigbala Moses Olajide. Wọn bi ni ọjọ kẹẹdogun, oṣu Kẹjọ, ọdun 1964, n'ilu Aramoko, nipinlẹ Ekiti. Gẹ́gẹ́ bi akọsilẹ nipa rẹ to wa lori ayelujara Facebook, o ni iwe ẹri ile ẹ̀kọ́ girama ati ti GCE. Bakan naa lo gba iwe ẹri ninu imọ Bíbélì ni Fasiti ilu Calabar. Alufaa ni Ajagunigbala ninu ijọ African Apostolic Church, n'ilu Igede-Ekiti. Lọdun 2018, wọn yan an gẹgẹ bi akọwe ikede fun ẹgbẹ́ oṣelu Mega Party of Nigeria (MPN), lasiko idibo gomina ipinlẹ Ekiti lọdun 2018. Oludije ẹgbẹ́ AAC ọhun sọ pe oun yoo mu atunṣe ba ẹka eto ilera nipinlẹ Ekiti. Bákan naa lo ni oun yoo ṣe atunto igbokegbodo ọkọ, to fi mọ eto aabo, nipinlẹ naa.",0,yoruba Ìlú tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìṣẹ̀: ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo.,0,yoruba _________ ni baba Ifá? (A) Ọ̀sẹ́ méjì (B) Ọ̀yẹ̀kú méjì (D) Èjì Ogbè #Ibeere #Yoruba,0,yoruba "Ileeṣẹ ayelujara nla naa yóò bẹ̀rẹ̀ ìnáwó orí ayélujára to jẹ ti ara rẹ Eto naa wa lati mu eto sisan owo lori ikanni igbalode ṣeeṣe lawọn orilẹ-ede mejila kan nigba ti a o ba fi ri oṣu mẹta akọkọ lọdun 2020. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ileeṣẹ ayelujara naa fẹ bẹrẹ si nii gbe owo ori ayelujara tirẹ, eyi to pe orukọ rẹ ni Global Coin yẹwo ni opin ọdun yii. Facebook ti n ba gomina banki ilẹ Gẹẹsi, Mark Carney fikunlukun lori rẹ. Wo ọna ti o le gba lati fi daabo bo ara rẹ lori Facebook. Oludasilẹ Facebook, Mark Zuckerberg ṣe ipade pẹlu Ọgbẹni Carney loṣu to kọja lati jiroro lori awọn anfani to wa ninu eto naa ati awọn wahala to lee ti inu rẹ jẹyọ. Abdulfatah Ahmed: Àwọn Kwara fẹ́ dán ilé ọkọ kejì wo ni lásìkò yí Facebook tun ti gba imọran lori awọn ohun to nii ṣe pẹlu ofin ati ilana eto iṣuna ori ayelujara naa lọdọ awọn adari eto iṣuna ilẹ Amẹrika. Bakan naa lo tun n ba awọn ileeṣẹ agboworin ori ayelujara kan bii Wester Union sọrọ nitori awọn ọna olowo pọọku ati ayarabi aṣa ti o n wa fun awọn eeyan ti ko ni apo ifowopamọsi lati fi owo ranṣẹ tabi gba owo. Facebook fẹ da owo ori ẹrọ kọmputa silẹ eyi ti ko ni ga ju ara lọ ti yoo tun pese abo to peye fun awọn ina isanwo lori ayelujara lai naani boya ẹni bẹẹ ni aṣuwọn ifowopamọsi ni banki tabi ko ni. Eto ọhun ti wọn da pe ni Project Libra eleyi ti facebook n gbero rẹ yii yoo wa bọ si gbangba ni oṣu kejila ọdun. Lábẹ́ odò! Ìgbéyawó yìí lárinrin Szu Ping Chan",0,yoruba àwọn alákọra àtọ̀hùnrìnwá onímúṣoṣoro yìí ti kó ọ̀pọ̀ ọmọ yorùbá lẹ́rú fúlàní ló ta àjàyí ìyá àti àbúròo rẹ̀ méjèèjì sóko ẹrú ní bí nǹkan,0,yoruba ẹ kú ojúmọ́ ire o lónìí ọjọ́ ẹtì a ò ní tí o,0,yoruba Àkójú ọ̀rọ̀ yi kún fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde sí ara ilẹ̀. (Item 139),0,yoruba ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Bàbá lo fi.,0,yoruba "fè joko, Nitori eyi, ara eni lo ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Àwòrán - ẹ̀fẹ̀ láti ọwọ́ọ Samuel Mwamkinga ( Joune ) , a lòó pẹ̀lú àṣẹ .",0,yoruba "Nígbà tí ó ṣe , ìgbésẹ̀ náà yírapadà di igi àràbà tí ẹnìkan kò leè ṣí nídìí tí ó fi ara da igbàgede ètò ìlú Nàìjíríà t'ó rorò .",0,yoruba Àtójọ ID nǹkan pánẹ́ẹ̀lì,0,yoruba fi. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé.,0,yoruba wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ẹkọ́: ti o nuni ti o jare.,0,yoruba àṣà ìlú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó wáyé.,0,yoruba "Mínísíta tó ń rí sí ètò ìrìnà àti iṣẹ́ òde ni Nàìjíríà tí fèsì sí ọ̀rọ̀ tó gbòde pé ààrẹ Muhammadu Buhari àti Asíwájú Bola Ahmed Tinubu ní àdéhùn tí wọ́n ṣe fún ipò ààrẹ ọdún 2023. Ọ̀rọ̀ náà ló tí ń tàn ká láti ọdún 2015, kí ìdìbò ààrẹ to wáyé. Àwọn kan sọ pé ẹgbẹ́ All Progressives Congress (APC) yọ Tinubu gẹ́gẹ́ bí oludije fun ìgbàkejì ààrẹ fún Buhari nítorí awuyewuye pé musulumi ati musumi kò lè di ààrẹ. Wọn ni èyí sì lo mú kí Buhari fi ọkàn Tinubu balẹ̀ pe oun ni yoo gba ijọba lọdun 2023. Èyí ló mú kí àwọn gómìnà ìhà Gúúsù àti àwọn olóyè ẹgbẹ́ òṣèlú People Democratic Party (PDP) bẹ̀rẹ̀ sí ní fi ẹ̀sùn kan APC pé wọ́n yí Nàìjíríà sí orílẹ̀-èdè Musulumi. Àwọn alẹ́nulọ́rọ̀ péjọ láti rọ Tinubu, tí wọ́n sì ni kí o mú ẹni tí yóò jẹ ìgbàkejì fún Buhari wa. Lẹ́yìn èyí, ni wọ́n yan kọmísọ́nà ètò ìdájọ́ nípìnlẹ̀ Eko nígbà kan rí, Yemi Osinbajo si ipo igbakeji aarẹ, tí wọ́n sì já Gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti, Kayode Fayemi sílẹ̀. Ṣùgbọ́n ṣáájú ìdìbò ọdún 2019, ìròyìn sọ pé ààrẹ túbọ̀ fi dá Jagaban lójú pé òun ni yóò gba ipò lọ́dún 2023. Lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ díẹ̀, wọn ni Tinubu ransẹ́ pé Gómìnà ìpínlẹ̀ Osun tẹ́lẹ̀rí, Bisi Akande láti wá sìn òun lọ sí ilé iṣẹ́ ààrẹ fún àbẹ̀wò. Làsìkò yìí gẹ́gẹ́ bí ìròyìn ṣe sọy, ní Tinubu tún ní kí ààrẹ Buhari tún ìlérí rẹ̀ ṣe, tí ààrẹ sì tún fọwọ́ sọ̀yà pé kódà bójú bá yẹjú, ohùn kò ní yẹ̀. Ìgbàgbọ́ ni pé ìpàdé èyí wáyé nínú oṣù kíní ọdún 2018. Nigba to n sọrọ lori isẹlẹ yii pẹlu iwe iroyin Daily Trust, Rotimi Amaechi ṣàlàyé pé òun kò ní ànfàní láti mọ kókó tó wà nínú àdéhùn wọn. Gómìnà ìpínlẹ̀ Rivers nígbà kan rí ọhun ni, kò si ìdánilójú pé Buhari àti Tinubu ṣe irú ìpàdé ìdákọ́nkọ́ tó jọ bẹ́ẹ̀. Ó fi kun pé òun gẹ́gẹ́ bí adarí gbogboogbò fún ìpolongo ẹgbẹ́ APC, kò sí àsìkò kankan tí òun péjú síbi irú ìpàdé bẹ́ẹ̀. ""Ṣùgbọ́n tí ó bá wá jẹ́ pé ìpàdé ìdákọ́nkọ́ wáyé láàárín ààrẹ Buhari àti Asiwaju Ahmed Tinubu, òun kò mọ̀."" "" Tí ó bá jẹ́ pé ìpàdé ìtagbangba tí ẹgbẹ́ APC pè, tí mi ò sì sí níbẹ̀ ajẹ́ wípé nǹkan mìíràn wà níbẹ̀ nìyẹn. Amaechi fi kún pé òun kò gbọ́ ìgbà kankan tí wọ́n sọ pé kí wọ́n gbé ìjọba fún Tinubu lọ́dún 2023. Ọmọ ilé igbimọ̀ asòfin ni ìpínlẹ̀ Eko ni a síwájú ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress (APC) Bola Ahmed Tinubu mú ọ̀rọ̀ Nàìjíríà ni òkúnkúndùn Agbenusọ ilé ìgbìmọ̀ asòfin Eko ìpínlẹ̀ Eko Mudashiru Obasa lo sọ èyí lẹ́yìn tí òhun àti àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ̀ tó kù rin ìrìnàjò lọ sí ilẹ̀ òkèèrè láti lọ sàbẹ̀wò sí Asiwaju Ahmed Tinubu Ó ní kokoko ni ara Asiwaju le, ti ko si si amin pe o n se ojojo kankan Díẹ̀ lára àwọn tó sàbẹ̀wò sí Bola Ahmed Tinubu ni alága ìgbìmọ̀ tẹ̀ẹ́kótó lórí ìgbòkègbodò ọkọ̀ Temitope Adewale, alága ìgbìmọ̀ tẹ̀ẹ́kótó lórí ètò ìlú àti àyíká Nureni Akindanya àti alága tẹ̀ẹ́kótó lórí ètò ọ̀rọ̀ ajé ilẹ̀ òkèrè Sylvester Ogunkelu. Obasa ni bí Tinubu ṣe máa ń dẹ́rìn pa àwọn ènìyàn náà lọ sì ń ṣe àti pé ìfọ̀rọ̀wérọ̀ láàrin àwọn tó jọ kọ́wọ̀ọ́rin wáyé lórí àwọn nǹkan tó ṣe pàtàkì fún ìdàgbàsókè Nàìjíríà. Ó ní abẹ̀wo náà ṣe pàtàkì nítorí ipò Tinubu gẹ́gẹ́ bí aṣáájú lórílẹ̀ - èdè yìí, ó jẹ́ atọ̀nà fún ọ̀pọ̀ àti aláànú ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ Nàìjíríà. Agbẹnusọ ilé sọ pé :"" Ọ̀rọ̀ Nàìjíríà jẹ a síwájú gidi gan. Kokoko ni ara rẹ̀ lè a sì ni ìfọ̀rọ̀wérọ̀ tó pọ̀ gidi gan pàápàá jùlọ lórí ìdàgbàsókè orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Inu rẹ̀ dùn gidi, ó ṣe àwàdà bí ó ṣe máa ń ṣe bákan náà sì ni ó ní ìgbàgbọ́ nípa ìlọsíwájú Nàìjíríà """,0,yoruba "Eniola Afeez: Ẹ̀rọ ayàwòrán CCTV ti tú àṣírí ẹni tó ja mi lólè, ẹ bá mi wá a",0,yoruba "RT @user: """"""""""""""""@user: Kábíyèsí o! Ọba alárọ tó ṣe ilé ayé róbótó bíi igbá ńlá, Bàbá ńlá ńlá tí ìjì kan ò lè mìn ... #BringBackOurGi…",0,yoruba "joko, Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó ga.",0,yoruba "Iye kaadi idibo ti awọn eeyan ko tii gba n kan ọpọ lominu O salaye yi ninu ifọrọwanilẹnuwo to ṣe pẹlu BBC Yoruba Agboke ni ọtọ ni ohun ti oun sọ ati wi pe ''o ya mi lẹnu pe awọn akoroyin kan gbe iroyin ohun ti mi o sọ sita'' ''Nkan ti mo sọ ko ni iwe iroyin yẹn gbe jade.Awọn eeyan lo tami lolobo nigboro wi pe wọn ni mo sọ wi pe awọn oloselu n fi owo damu mi.'' O fikun wi pe ''oun ti mo sọ ni wipe kaka ki ọpọlọpọ oloselu pawọ pọ pẹlu wa lati ri wi pe awọn oludibo gba kaadi to pọ nilẹ, kaadi ti ko si ni tita ni wọn wa kaakiri. Nipa kaadi ti o wa nilẹ, o tẹnumọ bo ṣe ṣe pataki ki awọn ara ilu wa gba kaadi wọn saaju idibo. ''Kaadi ti awọn eeyan ti gba lọdọ wa ti to 240,000 ti a si ni akọsilẹ pe eyi ti wọn ko ti gba ju 900,000 lọ.'' ''Idi ti a fi ni ki awọn oloselu ke si awọn eeyan lati wa gba kaadi re.Eni ti ko ba ni kaadi ko le ni anfaani lati dibo nitori Inec ti fagile lilo foomu 'incidence' ti a ma n lo tẹlẹ ti kaadi ko ba si tabi ti ko ṣisẹ'' Wòlíì Kasali sọrọ nípa awuyewuye pé o lè ìyàwó rẹ̀ jáde nílé INEC yoo sun miliọnu meje kaadi idibo O ko le dibo pẹlu kaadi ti kii ṣe ti ẹ BBC Yoruba bere lọwọ ogbẹni Mutiu pe kini yoo ṣẹlẹ si awọn kaadi ti ara ilu ko ba wa gba. Alaye to ṣe ni wi pe awọn yoo da irufẹ kaadi bẹ pada lọ si ẹka ijọba ipinlẹ Inec lati ijọba ibilẹ ni kete ti idibo ba ku bi ọsẹ kan. ''Bi eeyan ba ti lẹ ri kaadi onikaadi gba ko le sanfani fun nitori ko ni le fi dibo. Ohun to pe Inec ni ki awọn eeyan wa gba kaadi wọn ki eto idibo baa le lọ deede.''",0,yoruba "#AFCONU23Q Goolu mẹta ọtọtọ ni ẹlẹsẹ ayo Victor Osimhen nikan gba sawọn Libya ti Naijiria si fagba han akẹgbẹ wọn pẹlu àmì ayò mẹ́rin sodo(4-0). David Okereke lo fọba lee, lẹyin to gba goolu ẹlẹẹkẹrin wọle Libya, bẹẹ lawọn ọmọ Naijiria fijo bẹẹ nilu Asaba ti ere bọọlu ọhun ti waye. Èré Ọṣun: Àtáója ní wọn kò jí ère Ọṣun, ó sì wà níbi tó wà Libya lo jawe olubori pẹlu ami ayo meji sodo ninu ifẹsẹwọnsẹ akọkọ ti wọn gba lorilẹede Libya lọsẹ to kọja. Ṣugbọn ẹgbẹ agbabọọlu Naijiria fakọyọ ni papa iṣere Stephen Keshi lọjọ Aje lẹyin ti wọn gbayo mẹrin sawọn ti Libya kosi le da ẹyọkan pada. Nibayii orilẹede Sudan tabi Kenya ni ẹgbẹ agbabọọlu Naijiria yoo koju bayii ninu ipele to kan. Orilẹede Egypt ni yoo gbalejo idije ọhun to jẹ ẹlẹkẹẹta iru rẹ, ninu oṣu kọkanla ọdun yii.",0,yoruba àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jẹ́ dára jù...,0,yoruba @user Mo kí yín o fún àwọn ìròhìn oríṣìíríṣìí tí ẹ máa ń fi tó wa létí. Ẹkú iṣẹ́ o.,0,yoruba Ajíhìnrere Oníwàásù nínúu wàhálà ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀,0,yoruba ìlú.. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jẹ́ dára jù...,0,yoruba ìbàdandun láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba "Yoruba ni igba ko lọ bi orere, ako o tọ lọ bi ọpa ibọn, nitori saa laa ni, ẹnikan ko lo ile aye gbo. Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu gbajugbaja oṣere tiata, Olusola Isola Ogunsola, ti ọpọ eeyan mọ si Isho Pepper ati awọn aya rẹ, ti wọn dìjọ mi agbo tiata Yoruba logbo-logbo laarin ọdun 1965 si 1992. Ọjọ Aje, ọjọ Kejidinlọgbọn osu Kejila ọdun 1992, eyi to pe ọgbọn ọdun bayii ni iku pa oju akọni osere naa de, amọ bi onirese rẹ ko ba fin igba mọ, sibẹ awọn eyi to ti fin ko le parun. Bi o tilẹ jẹ pe Isho Pepper ati meji ninu awọn iyawo marun-un to n ba a ṣe ere tiata ti jade laye, sibẹ o yẹ ki awọn ọdọ iwoyi mọ nípa igbe aye ati iku akọni oṣere tiata naa, to fi mọ ipa to ko si idagbasoke iṣẹ tiata nigba aye rẹ. Ta ni Isho Pepper? Apetan orukọ gbajumọ oṣere tiata naa ni Olusola Isola Ogunsola, tii ṣe ọmọ bibi ilu Abeokuta, to jẹ olu ilu ipinlẹ Ogun bayii ni guusu iwo oorun Naijiria.. Ọjọ Kẹrinla, oṣu Kọkanla, ọdun 1942 ni Samuel ati Abigail Ajike Ogunsola bi akọni oṣere tiata naa sile aye, to si jẹ ọmọ agboole Baala Dasaolu lẹyin mọsalasi Ita Igbẹyin ladugbo Oke Itoku. Olusola ni abigbẹyin ninu ọmọ mẹrin ti awọn obi rẹ bi, abule Olokuta, ni ẹba Alahọ to wa nijọba ibilẹ Oluyole nilu Ibadan si lo ti lo igba kekere rẹ, ibẹ si lo ti lọ sile ẹkọ alakọbẹrẹ Christ School, Olokuta. Lẹyin to pari iwe mẹfa rẹ lo pada si Abeokuta fun eto ẹkọ girama, to si lọ si Abeokuta Grammar School nibi to ti bẹrẹ afihan ifẹ rẹ si ere tiata lasiko ti ọpọ eeyan korira isẹ naa, ti wọn si n rii awọn osere tiata bii alagbe. Nitori idi eyi, ọpọ ipenija ni Olusola koju nidi iṣẹ to yan laayo ọhun, tawọn ẹbi ati ọrẹ si kọ ẹyin sii. Amọ, niwọn igba to jẹ pe yeye ọmọ nii gba ọmọ, iya rẹ, Abigail Ajike ṣe atilẹyin alailẹgbẹ fun un nidi iṣẹ naa, ti Olusola si dara pọ mọ ẹgbẹ oṣere tiata Akin Ogungbe to wa nilu Abeokuta lọdun 1959, lẹyin to pari ẹkọ girama. Lara awọn ti wọn dijọ kọ iṣẹ tiata lọdọ Akin Ogungbe lasiko naa ni Jimoh Aliu, Charles Olumo (Agbako), oloogbe Afolabi Afolayan (Jagua), ati Femi Adeyemo (Baba n gba life). Olusola kuro lọdọ ọga rẹ lọdun 1965 lati da ẹgbẹ tiata tara rẹ silẹ, to si n kọrin, lu ilu, jo ati sere. O fẹ ọpọ iyawo lati maa ba sere, ti wọn si n tẹle yika gbogbo ilu to ba n lọ. Isho Pepper jẹ ọkan lara awọn oṣere tiata to kọkọ ṣe ere itage lori amohunmaworan pẹlu awọn gbajumọ oṣere tiata miran bii Hubert Ogunde, Baba Sala, Baba Mero, Kola Ogunmola, Oyin Adejobi, ati Adeyemi Afolayan. Bakan naa lo ṣe ọpọ ere ninu iwe Atọka, oun naa si tun ni oṣere tiata kẹrin to ya ere sinima lẹyin Hubert Ogunde, eyi to gbe e lọ si orilẹ-ede United Kingdom (UK). Ọpọ eeyan ni Isho Pepper kọ ni iṣẹ tiata, lara wọn ni Samson Eluwole (Jinadu Ewele), oloogbe Adeniyi Orofo (Ewejoko) ati oloogbe Gbolagade Adedeji (Aro onifila gogoro). Olusola jẹ ọkan lara awọn agba ọjẹ oṣere tiata to da ẹgbẹ awọn oṣere taa mọ si ANTP silẹ lọdun 1976, to si jẹ akọwe owo akọkọ fun ẹgbẹ naa laarin ọdun 1976 si 1989, bẹẹ lo tun gbe ọpọ ere jade ni ede Yoruba. Lara awọn ere naa ni Fere bi Ekun, Alaafin Aganju, Agbalowomeri, Efunsetan Aniwura, Ibu Olokun, Koseegbe, Ajaloleru, Iyawo Alalubosa ati bẹẹ bẹẹ lọ, ko si fẹ ẹ si ilu kan ni Naijiria ti Isho Pepper ko gbe ere tiata de. Lasiko ti Olusola n dabira lati gbe aṣa, ede ati ìṣe Yoruba larugẹ sii, ni iku ja ẹmi rẹ gba lairo tẹlẹ lasiko aisan ranpẹ lẹni aadọta ọdun, ni ọjọ kejidinlọgbọn, oṣu Kejila, ọdun 1992. Mojisola Ogunsola: Oloogbe Mojisola Ogunsola ti awọn eeyan mọ si Iya Alakara nigba aye rẹ, ni iyale patapata ninu awọn iyawo Isho Pepper, to si maa n tẹle ọkọ rẹ lọ ṣe ere tiata kaakiri. Ẹni ọgọta ọdun ni oloogbe naa nigba to jade laye lẹyin iku ọkọ rẹ, to si ko ipa manigbagbe ninu iṣẹ tiata pẹlu ọkọ rẹ. Iyabode Ogunsola Iyabode Ogunsola ni ọpọ eeyan mọ si Efunsetan Aniwura, to si jẹ gbajumọ oṣere lobinrin lasiko ti ọkọ rẹ wa laye. Efunsetan si ni gbogbo aye mọ julọ ninu awọn aya oloogbe Isola Ogunsola sugbọn lọwọ lọwọ bayii, o ti dagbere fun iṣẹ tiata, to si di oniwaasu ọrọ Ọlọrun. Ọpọ ere sinima, fiimu agbelewo ati ere itage ni Efunsetan ti kopa ninu rẹ, ko si si ẹni to ri obinrin naa lori pẹpẹ iwaasu, ti ko ni maa ranti awọn ara manigbagbe to ti da ninu isẹ tiata. Laipẹ yii si lo ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ loke eepẹ. Funmilayo Ogunsola: Ijewuru ni adape orukọ Funmilayo Ogunsola ninu iṣẹ tiata, to si ti silẹ bora lọdun 2019 lati ipasẹ aisan ẹjẹ ruru to ba fínra. Isẹ kekere kọ ni Funmilayo ko nidi isẹ tiata loju aye ati lẹyin iku ọkọ rẹ, ki iku to yọ ọwọ rẹ lawo lasiko aisan ranpẹ. Orukọ Ijẹwuru to fi silẹ si lo di manigbagbe titi di oni yii, tawọn eeyan fi n ranti rẹ. Funmilayo ni iyawo kẹta Isho Pepper, toun naa si ko ipa ti ko kere si idagbasoke iṣẹ tiata. Yetunde Ogunsola Arẹwa obìnrin, apọnbeporẹ, ni Yetunde Ogunsola nigba to wa lewe, ti Isola Ogunsola fẹ bii aya. O sa ipa rẹ lati mu agbega ba iṣẹ ọkọ rẹ, tii ṣe ere tiata, ti ọpọ eeyan si mọ gẹgẹ bii Iyawo Alalubosa tabi Ayoni, nitori ipa to ko ninu ere naa Iyawo Alalubosa. Titi di akoko yii, Yetunde Ogunsola sì n kopa ninu ere tiata lorisirisi, oun naa si ti di Ajihinrere. Bolatito Ogunsola Bolatito ni iyawo kekere to gbẹyin ninu awọn iyawo Isho Pepper, Aina Orosun si ni ọpọ eeyan mọ si. Bolatito ko ipa manigbagbe ninu iṣẹ tiata lasiko ti ọkọ rẹ, Ishola Ogunsola wa loke eepẹ, sugbọn lẹyin ti ọkọ rẹ ku tan, oju obinrin naa ko han mọ ninu ere tiata. Nibayi to pe ọdun mejidinlọgbọn ti Olusola Isola Ogunsola jade laye, to si fi ọpọ ọmọ silẹ saye lọ, a si n gbadura pe ki ọba oke tẹ si afẹfẹ rere, ko si di idile to fi silẹ saye lọ mu sinsin.",0,yoruba Wọ́n ti yọ Portable bíi jìgá kúrò nínú àwọn tí yóò gba àmì ẹ̀yẹ ‘Headies’ nítorí wòtòwótò,0,yoruba orúkọ wo ni ìran káàárọ̀oòjíire ń pe ẹranko inú àwòrán yìí,0,yoruba lọ́nà kejì ẹ̀wẹ̀ ìwà lẹ̀ṣọ́ èèyàn la ṣe tún pa òwe pé ìwà rere lẹ̀ṣọ́ ènìyàn ìwà ni ẹ̀ṣọ́ tí a kó lọ òde,0,yoruba "rere. Bàbá lo ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba "Bakan naa ni ileẹjọ naa paṣẹ fun gomina ati kọmisọnna fun ijọba ibilẹ lati gba sabuke rẹ pada. Ileẹjọ ni sabuke naa tapa si aṣẹ ileẹjọ ti wọn da ni Ọjọ Kọkanla, Osu Kẹta, ọdun 2021. Adajọ Sherifat Adeyemi to yọ ọba naa ni ilana ti wọn fi gbe ọba naa wọle ko ba ofin mu. Wọn ni iwadii fihan pe ọba gbe igbeṣẹ naa pẹlu gomina tako aṣẹ ileẹjọ, nitori adajọ ko i ti dajọ lori ẹni ti ipo ọba naa tọsi. Lori iro: Ká ni àwọn Òbí mi gbà fún mí, èmi àti Sunny Ade á jọ máa 'Compete- Baba Lórí ir Nibayii, ọba naa ti pasẹ fun Oyetunde lati sọra fun pipe ara rẹ ni ọba naa ni agbegbe ọhun titi ti idajọ yoo fi pari lori ọrọ ẹni ti ọba naa tọsi. Adajọ fikun wi pe ko si aridaju pe awọn to pe ẹjọ ti ṣetan lati gba alaafia laaye lai lọ si ileẹjọ mọ. Bakan naa ni adajọ ọhun wa sun igbejọ naa di ọjọ Kẹrindinlogbọn, Oṣu Kẹrin, ọdun 2021. Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Bolanle Adekanmi kọ́ wa nípa oríṣíi Àròkọ Yorùbá tó wà Lara awọn ti wọn pe ẹjọ mọ ni Gomina ipinlẹ Oyo, Olotu eto idajọ nipinlẹ naa, kọmisọna fun ọrọ ijọba ibilẹ ati oye, Ọmọọba Thompson Oyetunji, Oloye Adewale Erinle, Oloye Ademola Ishola, Oloye Adegbite Adeleke, Oloye Oyegoke Oyegbami, Oloye Oladele Akinbola ati ọmọọba Gideon Oyekunle. Ẹ̀yin olórin ẹ̀mí tó ń bóra, lo èékáná gígùn, oò yàtọ̀ sí aṣẹ́wó hòtẹ́ẹ̀lì tí wọ́n ń gbé bíi súùtì Pepper Menti - Bola Are",0,yoruba Èyí ni òun tí a kọ eḳọ nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò.,0,yoruba "Lọjọ Iṣẹgun ni Gomina ipinlẹ Kaduna, Mallam Nasir El-Rufai yan an gẹgẹ bi ọkan lara awọn ajọ to n ri si ọrọ karakata ni ipinlẹ Kaduna,(KADIPA). Lonii Ọjọru. ọjọ kọkanla oṣu kẹta ni Gomina El-Rufai tun fun Sanusi ni ipo mii. Oludamọran Gomina lori ọrọ iroyin, Ọgbẹni Muyiwa Adekeye ṣalaye pe Sanusi ti di alakoso igbimọ alaṣẹ fasiti ipinlẹ Kaduna. Sanusi rọpo Oba Alaye, Malam Tagwai Sambo to ti wa nipo naa lati ọdun 2005. Adekeye ṣalaye pe Gomina El-Rufai fun Sanusi ni ipo ọhun nitori ipa to ti ko lori eto ẹkọ lorilẹede Naijiria. Gomina El-Rufai dupẹ lọwọ Malam Sambo fun bi o ti gba pe ki Sanusi di alakoso igbimọ alaṣẹ fasiti ipinlẹ Kaduna tuntun ọhun. Gómìnà ìpínlẹ̀ Kaduna fún Sanusi ní ipò tuntun Gomina ipinlẹ Kaduna ti yan Mahammadu Sanusi keji gẹgẹ bi ọkan lara awọn ajọ to n risi ọrọ karakata ni ipinlẹ Kaduna,(KADIPA). Ninu atẹjade ti wọn fi lede ni wọn ti fi lede wi pe wọn fẹ fi eyi ṣe atunto ẹka to n risi idagbasoke ọrọ aje ni ipinlẹ naa. Wọn fikun wi pe awọn gbe igbeṣẹ naa nitori wọn mọ pe ipinlẹ Kaduna yoo fi ohun ribiribi kọ lara ọgbọn ti Sanusi ni ati oye rẹ nipa eto ọrọ aje.",0,yoruba "Lónìí ni Arugbá, Àdìgún Ọlọ́ṣun àt'àwọn ìyá, bàbá Ọlọ́ṣun ń'nú aṣọ àlà pẹ̀lú gbogbo alájọ̀dún yóò wọ́ lọ sí odò Ọ̀ṣun. #OsunOsogbo",0,yoruba "àkokò, Olùwo ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba Ènìyan ti nilo oṣiṣu fun ẹkọ́ tabi ibini.,0,yoruba "Kò wúlò kí a máa sọ̀rọ̀ tako ìjìyà abẹ́lé kí a sì tún máa gbèlẹ́yìn àṣàrò ìnáwó tí kò ní ṣe ààbò ètò àwùjọ , ìṣúná àìtó tí gbogbo wa mọ̀ pé ipa òdì ni ó ń kó nínú ayé àwọn obìnrin .",0,yoruba ẹ rí kiní gíga tó dà bíi òkè yìí à bẹ́ ò ríi ọ̀pọ̀ ló gbabẹ̀ bá ọba lọ ìrìnàjò àrìnmabọ̀,0,yoruba "Komisana fun eto iroyin nipinlẹ Osun, Arabinrin Funke Egbemode sọ fun BBC Yoruba pe ""gomina ti fi aṣẹ fun igbimọ lọba-lọba lati yanju ọrọ naa nilana aṣa."" Egbemode sọ pe ""nkan ti ko ṣe e gbọ l'eti ni pe ọba meji woju ara wọn nibiti awọn eniayn miran wa."" ""Gomina ti da si, a si ti ba awọn to yẹ sọrọ, to fi mọ awọn to fi ẹhonu wa si ọọfisi gomina. A ko si ni i jẹ ki iru iṣẹlẹ naa o waye mọ."" Lori ẹsun ti Oluwo fi kan awọn ọba mẹjọ ti ọrọ tun kan pe wọn n ta ilẹ ilu wọn lọna ti ko tọ ọ, Egbemode sọ pe gbogbo ẹhonu Oluwo, ati tawọn ọba yooku ni ijọba yoo gbọ. Kò sí ǹkan tó ń jẹ́ ọ̀rọ̀ ìgbàgbọ́ tàbí ìmọ̀le nínú àgbékalẹ̀ Amotekun - Alake ti Egba Ṣugbọn ṣa, lori bi awọn kan ṣe n fẹ ki ijọba o sọ pe ki Ọba Abdulrasheed Akanbi o kuro lori oye fun igba diẹ, Arabinrin Egbemode sọ pe ijọba ko ni i sọ nkan ti yoo ṣe, ki wahala miran ma ba a tun bẹrẹ. Awọn Oloye ati diẹ lara awọn olugbe ilu Ọgbaagba ṣe iwọde lati fi ẹhonu wọn han lori bi Oluwo ti Iwo, Ọba Abduraheed Akanbi ṣe gba ọba ilu wọn, Agbowu tilu Ọgbaagbaa, Ọba Dikrullai Olaleke Akinropo, Ọlabiran Kẹta l'eti nita gbangba. Owurọ ọjọ Aje ni awọn ara ilu ati ijoye lati ijoba ibile Iwo, Ayedire, Ola oluwa se iwọde lọ si ọdọ gomina ati agbẹnusọ ile igbimọ aṣofin. '500 level'' ni mo wà nígbà tí mo di adélé Ọba' Awọn olufẹhonuhan naa gbe oriṣiriṣi akọle dani, ninu iwọde naa to waye nilu Oṣogbo ti wọn si n ke si ijọba lati sọ pe ki Oluwo lọ rọọkun nile na. Opin ọsẹ to kọja ni a gbe iroyin jade pe ija waye laarin Oluwo ati Ọba ilu Ọgbaagba lasiko ti wọn n ṣe ipade alaafia pẹlu igbakeji ọga agba ọlọpaa nilu Osogbo lori ọrọ to ni ṣe pẹlu ilẹ. Oluwo fi ẹsun kan awọn ọba mẹjọ kan to wa labẹ rẹ pe wọn n ta ilẹ ilu wọn lọna aitọ. Lasiko to n ṣalaye ohun to bi ija agba meji to waye lọjọ Ẹti laarin rẹ ati Agbowu tilu Ọgbaagbaa, Ọba Dikrullai Olaleke Akinropo, Ọlabiran Kẹta, Oluwo sọ pe lootọ ni ọga ọlọpa pe awọn si ipade alaafia, amọ se ni Agbowu n da ọrọ mọ oun lẹnu, to si n pe oun ni orukọ buruku, ti ko se gbọ seti. Oluwo salaye loju opo Instagram rẹ pe se ni Agbowu na ọpa asẹ rẹ si oun, to si fẹ kii bọ oun loju, ti oun si fi tipa kọ igbesẹ naa, eyi ti ara Agbowu ko gba rara.",0,yoruba Ẹ ṣé ìyá mi ❤️ 🖤 https://t.co/dVoQspNuR1,0,yoruba o jare. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa aráyé: ti o nuni ti o nuni ti o pataki.,0,yoruba ilera ṣẹlẹ ni Ibadan ti gbogbo eniyan sọ o dara. (1997),0,yoruba "Bẹẹ lọrọ ri fun awọn ole meji kan nipinlẹ Eko, nigba ti ọwọ palaba wọn segi, ti akara wọn si tu sepo. Awọn firi nidi ọkẹ naa, ti wọn gbajugbaja fun isẹ alọnilọwọgba lagbegbe Lekki, ni wọn pe oruk wọn ni Adebayọ Ayọmide ati Isaac David. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Aago mẹsan alẹ ni ikọ ọtẹlẹmuyẹ, ti ọga ọlọpa kan lati agọ ọlọpa Marọkọ, Isah Abdulmajid ko sodi, lọ paraaro afara kan to so adugbo Lekki pọ mọ Ikoyi, asiko yii si ni wọn ri awọn omidan meji kan, ti wọn n gbọn jinni-jinni. Nigba ti wọn beere lọwọ awọn ọmge naa pe, ki lo se wọn, ni wn ba salaye pe awọn alọkolohunkigbe meji lo fi ibọn gba ohun ini awọn, ti wọn si tọka ọna tawọn ole ọhun morile fun awọn ọlọpa. Aṣọ òkè: Alákọ̀wé ní ọ̀nà láti wá oúnjẹ fáwọn tó ń ṣe aṣọ òkè ló ṣún òun débẹ̀ Ọwọ sinkun awn ọlọpa yii ba awọn ole naa, ti wọn si ba ibọn ilewọ kan, ada ati ọpọ ẹrọ ibaraẹnisọrọ alagbeka lọwọ wọn. Nigba ti wọn n ka ni agọ ọlọpaa, awọn ole naa ni ara ọmọ ẹgbẹ ikọ adigunjale kan ti wọn n da agbegbe Lekki laamu ni awọn. Nigba to n gbosuba fun ikọ ọlọpa to se bẹbẹ yii, Kọmisana ọlọpa nipinlẹ Eko, Zubairu Muazu wa pasẹ pe ki wọn gbe ẹsun awọn ole meji ọhun sabẹ ikọ to n gbogun ti iwa idigunjale nipinlẹ Eko fun iwadi kikun. Muazu wa fọkan awọn olugbe ipinlẹ Eko balẹ pe ileesẹ ọlọpa mu aabo ẹmi ati dukia wọn lọkunkundun, to si tun fewe ọmọ mọ awọn ọdaran leti lati tun ero wọn pa, bibẹẹkọ ikoko ko ni gba omi, ko gba ẹyin, ko tun gba ṣọṣọ.",0,yoruba "Omoluabi wa ni èkó aṣà lo je ti ibile. Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.. Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba "Ggbajugbaja oṣere Nollywood, Adebimpe Oyebade, ti kegbare sita pe ẹlẹtan ni awọn ọkunrin. Nibu ọrọ kan to kọ soju opo ayelujara Instagram rẹ lo ti n beere lọwọ awọn ololufẹ rẹ pe, ki lo maa n mu ki awọn ọkunrin yi iwa wọn pada si obinrin ti wọn n fẹ, lẹyin ti ibalopọ ba ti waye laarin awọn mejeeji. O ṣalaye pe kii ṣe obinrin nikan lo ma n ṣe oju meji tabi jẹ ọdalẹ ninu irinajo ifẹ, o ni ati ọkunrin ati obinrin lo ni iwa yii lọwọ. O tọka si bi oriṣiriṣi ọkunrin ṣe ma n yi iwa pada si obinrin, ti obinrin naa ko si ni ri oju wọn nilẹ mọ, lẹyin ti ọwọ ọkunrin bẹẹ ba ti tẹ nkan to n wa ninu irinajo ifẹ naa. Ọrọ naa waye lori fidio kan to fi sita, ninu eyi ti oun ati akẹẹgbẹ rẹ, Adedimeji Lateef, ti ṣe ere kekere kan, ninu eyi ti awọn mejeeji ti jẹ ololufẹ. Ninu fidio naa, to jẹ apa kẹrin eto kan ti Adebimpe ma n ṣe, lo pe akori rẹ ni 'DiaryOfAnAfricanWoman EP 4 - MEN ARE SCUM'. Ninu fidio naa, awọn mejeeji fẹran ara wọn pupọ, ṣugbọn lẹyin asiko diẹ, Lateef ko gbe ipe Adebimpe mọ lori foonu. Ibalopọ to ti waye laarin wọn di oyun, amọ niṣe ni Lateef kọ lati gba oyun, to si sọ fun Adebimpe pe, awọn obi oun ko faramọ ki awọn fẹra gẹgẹ bi ọkọ ati iyawo. Adebimpe beere pe ,ki lo de ti awọn ọkunrin kan ma n tan obinrin, nigba ti wọn mọ pe awọn ko ni erongba lati fẹ ẹ sile? O ni ti ọkunrin ba ṣẹṣẹ n fẹ obinrin, o ma n fi aaye silẹ lati wa pẹlu rẹ, ṣugbọn to ba ti kọja lara rẹ tan, aye lati rira ko ni i si mọ. O wa sọ fun awọn ọkunrin pe, ki wọn yi iwa pada, ki wọn o ṣe obinrin bi wọn ba ṣe fẹ ki ọkunrin mii ṣe si ọmọ wọn obinrin.",0,yoruba "RT @user: Olúwadámilọ́lá, happy birthday darling. Igba ọdún, ọdún kan ni. Kòní bàjẹ́ baby 😘😘😘",0,yoruba "From #ibadantotheworld we say happy birthday to the living legend mamarainbowofficial igba odun ojo kan ni🤩😍 #ibadanpride #nollywood #lagelufm967 #africanmagicyoruba #yorubawedding #yoruba #bbcyoruba @user Ibadan,… https://t.co/qp49i6RR21",0,yoruba "Ní ìlú kan, Bàbá ni olokìkì. ìrìn ìròyìn. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..",0,yoruba lòdì Ìjẹ̀. A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba "gbé fi yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba olùparapọ̀ ri pe jẹ́ pàtàkì wey ti o ṣe pataki.,0,yoruba Tinubu 2023: Ọ̀nà tí Bola Tinubu fẹ́ gbà ṣẹ́gun ìgbésùnmọ̀mí rèé tó fi ń ṣèlérí,0,yoruba "Ẹ̀mí ọmọdé kan nù nínú ìjọ tó wó lulẹ̀ Nígbà tí BBC bá Kọ́mísánà Ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ náà, Muhammed Mustapha sọ̀rọ̀ ló fi àrídájú hàn pé ọmọdékùnrin kan pàdánù ẹ̀mí rẹ̀ nínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà. Bákan náà, Kọ́mísánà jẹ́ kó di mímọ̀ pé ilé ìjọsìn náà ti lé lọ́gọ́rùn ún ọ̀dún ó sì ti rí bíi ilé àlàpà. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí: 'Irọ́ ni pé Boko Haram pa ọmọ ogun ọgbọ̀n ní Borno' Ẹ fójú lóùnjẹ láti ibi ètò àmì ẹ̀yẹ̀ AMVCA Kíni Akpabio, Buhari fẹ́ lọ se ní China? Ọ̀gọ̀ọ̀rọ̀ olùjọ́sìn ìjọ Kátólìkì Pọ́ọ̀lù míma ti ìlú Ugolo, Adagbrasa ní ìjọba ìbílẹ̀ Okpe ní ìpínlẹ̀ Delta ló wà nínú ilé ìjọsìn náà nígbà tó wó lé wn lórí. Ní àkókò tí a kó ìròyìn yìí jọ, kò tíi sí àrídájú iye ènìyàn tó fara pa sùgbọ́n ohun tí àwọn olùgbé ìlú náà sọ fún àwn oníròyìn ni pé ìṣẹ̀lẹ̀ náà wáyé lákòkò ìsìn. 'Agogo méje ń lọ lù láàrọ̀ la gbọ́ ariwo ńlá kan'",0,yoruba Ire á kárí gbogbo wa. A kò ní r'ógun #BokoHaram lónìí o.,0,yoruba "Ẹ wí fún ilé ìgbìmọ̀ @user kí wọ́n dí isà ejò kí wọ́n mú ti eku ẹmọ́ dẹ, kí wọ́n fi ẹ̀rọ alátagbà 'ílẹ̀! @user #Nigeria",0,yoruba "Ẹsun ibalopọ lori BB Naija Ọmọbinrin ọhun ni wọn fẹsun kan pe, o tapa sofin ile iṣẹ ọlọpaa Metropolitan Police nitori fọnran to lu ayelujara pa ṣafihan rẹ pe, o n ni ibalopọ pẹlu akẹgbẹ rẹ lori eto ọhun. Ile iṣẹ ọlọpaa ilẹ Gẹẹsi to ṣalaye ninu atẹjade kan ti wọn fi ṣọwọ si BBC salaye pe, ọlọpaa naa beere fun aaye iyọnda lati lọ kopa ninu eto naa ṣugbọn ileeṣẹ ọlọpaa ko fun un laaye naa. Ileeṣẹ ọlọpaa Met ni Kareem kọkọ kọwe beere fun aye lati lọ fun isinmi alaigbowo-oṣu ṣugbọn ko sọ ohun to fẹ lọ ṣe, wọn si fun laaye. Ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe, awọn mọ pe Kareem n kopa ninu eto agbelewo naa lọwọlọwọ lai gba iyọnda lọwọ awọn alaṣẹ ileeṣẹ ọlọpaa. Eto BB Naija Ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn ko lọwọ si bi Kareem ti wa lori eto naa ati pe, kii ṣe ileeṣẹ ọlọpaa ilẹ Gẹẹsi loun n ṣoju fun niwọn igba to wa lori eto naa. Ẹsun ibalopọ lori BB Naija Atẹjade ti alukoro Ileeṣẹ ọlọpaa Met, Rebecca Byng fi ṣọwọ si BBC ṣalaye pe, iwadii ti bẹrẹ lori ọrọ Kareem. Atẹjade naa sọ siwaju si pe, o ti wa ninu ofin ati ilana ileeṣẹ ọlọpaa Met pe, wọn gbọdọ huwa bi ọmọluabi nibi kibi ti wọn ba wa. Eto BB Naija Agbẹnusọ fun Khafi sọ pe Khafi yoo sọrọ si ẹsun yii nigba to ba to asiko. Ẹsun ifabanilopọ lori BB Naija Khafi jẹ aṣoju ileeṣẹ ọlọpaa Met gẹgẹ bi ọlọpaa alawọdudu nilẹ Gẹeṣi . Ofin awọn ọlọpaa Met tun sọ pe, awọn ọlọpaa ko gbọdọ se nnkan ti yoo tabuku tabi mu ẹgbin ba orukọ ileeṣẹ ọlọpaa ilẹ Gẹẹsi. ''Ọlọpaa kọlọpaa to ba tapa si awọn ilana ati ofin wọn, yoo foju wina ofin.''",0,yoruba egúngún = eégún òròrùn = oòrùn = òògùn,0,yoruba 2. #Parioweyii À rí ìgbọdọ̀ wí... #Ibeere #Yoruba #Owe,0,yoruba Òǹlo Weibo mìíràn fi èròńgbàa rẹ̀ hàn pẹ̀lú ohun tí ó fẹ́ fún Kérésìmesì :,0,yoruba Ẹko ti o nuni ti o nuni ti o pataki.,0,yoruba "Gomina Ajimobi ti yóò fi ipò rẹ̀ sílẹ̀ lẹ́nu ọjọ́ diẹ sí ìsìnyín ló sẹ̀sẹ̀ yan olórí òsìsẹ́ tuntun ní ìpínlẹ̀ Ọyo. Akeem Olatunji to jẹ agbẹnusọ fun ẹgbẹ oselu PDP ni gomina Ajimobi lo si wa lori oye, bẹẹ lo si ni anfaani lati se ohun to wu u. Olatunji ni awọn ko le e sọ pe awọn fọwọ si igbesẹ naa tabi awọn ko fọwọ si i, ṣugbọn awọn yoo wo igbesẹ naa finifini ti awọn ba de ipo, lati wo boya ọna to gba de ipo ba ofin mu gẹgẹ bi akowe agba tabi bẹẹ kọ. Contortionist: Mo lè gbé ìfun mi pamọ́ ki n tún se èémí! O fikun un pe ohun to wu gomina naa lo n se nipinlẹ naa, amọ ko da eto ẹgbẹ oṣelu PDP to jawe olubori ninu idibo to kọja ru nitori ẹka osisẹ yato si eto oselu lorilẹ-ede Naijiria. Ijó Bàtá ti Yorùbá gb'oríyìn ní Calabar Festival 2018 Ti a ko ba gbagbe, ni Ọjọru, ọsẹ yii ni gomina Abiola Ajimobi yan abileko Ololade Agboola gẹgẹ bi adari awọn osisẹ tuntun, lẹyin ti abileko Hannah Ogunnesan ko iwe fi ipo silẹ. Colorado ni Amẹrika àti odò Awaye ní Naijiria nikeji àdágún órí àpáta ní gbogbo àgbáyé!",0,yoruba @user hahaha. Ó jù bẹ́ẹ̀ lọ díẹ̀. :),0,yoruba "Góòlù àwò dàmi ẹnu yíí kún ara góòlù Ronaldo gbá wọlé nínú mẹ́ta tí Real Madrid fi ṣe àgbà Juventus Góòlù àwò dàmi ẹnu yíí kún ara góòlù méjì tí Ronaldo gbá wọlé nínú mẹ́ta tí Real Madrid fi ṣe àgbà Juventus. ìṣẹ́jú kẹta ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà ni Ronaldo ti kọ́kọ́ mi àwọ̀n kí ó tó di wí pé ó tún fò sókè fi ẹ̀yìn gbá bọ́ọ̀lu wọ inú àwọn Juventus. Ronaldo tàn bí oòrùn níwájú Juventus Ńṣe làwọn olólùfẹ́ Juventus dìde sókè rọ òjò àtẹ́wọ́ lu Ronaldo lẹ́yìn tó gbá góòlù náà wọlé. Gbogbo bí Juventus ṣe gbìyànjú láti yíí ojú ọ̀rọ̀ padà ló já sí pàbó tí aláàkóso ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà sì tún lé atamátàsé ikọ náà, Paulo Dybala jáde. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ní ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ míràn tó wáyé, Bayern Munich lu Sevilla mọ́lé pẹ̀lú àmì ayò méjì sí ẹyọ kan. Ńṣe làwọn olólùfẹ́ Juventus dìde sókè rọ òjò àtẹ́wọ́ lu Ronaldo Agbábọ́ọ̀lù Sevilla, Jesus Navas ló kọ́kọ́ gbáá bọ́ọ̀lù wọ ilé ara rẹ̀ kí Thiago Alcantara tó fi orí gbé òmíràn wọlé. Ṣáájú méjí yíí ni Pablo Sarabia, ti gbé Sevilla síwájú kí omi tó tẹ̀yìn wọ ìgbín wọn lẹ́nu.",0,yoruba àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba ìsẹ̀yín ni adarí ìjọìsìn ìjọọba ìjọẹgbẹ́ ń fi ọ̀bẹ ẹ̀yìn bu iṣu gbogbo ọmọ ìjọ arálùú ẹgbẹ́ jẹ,0,yoruba "E ( Olóòtú ètò “ Ojúmọ́ Ire """""""" ) : Báyìí ni a ṣe gbèrò láti ṣe é ; akọ̀ròyìn - in wa á máa wa ọkọ̀ bí yóò ṣe máa fi ọ̀rọ̀ wá ọ̀rọ̀ lẹ́nu alámọ̀dájúu yín .",0,yoruba tí ìyà ńlá bá gbéni ṣánlẹ̀ kéékèèké á máa gun orí ẹni when tripped by a major setback one easily becomes vulnerable or falls prey to minor ones a major setback can be unsettling and quite often makes us vulnerable to minor ones,0,yoruba se se. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gblọ yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba "RT @user: @user. Beeni ore mi, meebi fun anfaani ara wa ati ojo iwaju ni.... O di dan dan ki a jo kopa ninu atunse yii",0,yoruba "“ Ìpínlẹ̀ Kano kò tíì ní ìrírí nípa ààrùn COVID - 19 tẹ́lẹ̀rí , ìyàlẹ́nu ló sì ń jẹ́ fún wa bí ààrùn COVID - 19 se wá ń tàn kálẹ̀ báyìí .",0,yoruba Àkójú ọ̀rọ̀ yi kún fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde sí ara ilẹ̀. (Item 182),0,yoruba ni ọrọ̀ àìmọ́ lo je gbogbo ise ibile tèmi.,0,yoruba _Ìjáde Ipá,0,yoruba ìlú.. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìṣẹ̀: ti o nuni ti o wulo.,0,yoruba "Ẹyẹ òwìwí kì í ṣe ẹyẹ rere ní Tanzania , àti pé , bẹ́ẹ̀ ni Tanzania kì í ní ìgbàgbọ́ - asán .",0,yoruba "Ẹsin abalaye ti kọja bẹẹ pẹlu awọn agbelarugẹ to ti baa ati ọpọn imọ to wa ninu rẹ. Lasiko ti BBC Yoruba lọ jọsin pẹlu awọn onisẹse ti ijọ Imọlẹ Olodumare, a ri pe diẹ ni iyatọ to wa laarin bi wọn se n jọsin nibẹ ati nile ijọsin tawọn ọmọlẹyin Kristi. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Se ti orin aladun lati ẹnu awọn ẹgbẹ akọrin wọn ni abi ọna tawọn ẹlẹyinju ẹgẹ obinrin ati alakọwe n gba jere ọkan si iwa rere lawujọ wa. Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC Yoruba, Ọmọwe Ifayemi Ifatunde ni awọn onisẹse n fẹ ki ijọba pin ere iselu alagbada de ọdọ gbogbo ẹsin pata pata. Bakan naa lo tun n fẹ ki ijọba pese gbogbo anfaani to n fun awọn Kristiẹni ati Musulumi de ọdọ awọn onisẹse.",0,yoruba "yorubá tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.",0,yoruba "Ọba fè lọ, Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde sí ara ilẹ̀.",0,yoruba lákòótán ẹni tí ò jẹ́ nǹkan kan tó ń ṣe bí ẹní jẹ́ mẹ́wàá ni a máa ń fi ẹṣin ọ̀rọ̀ bá wí pé o ò tíì tó ò ń mí fìnìn,0,yoruba yankolu yankolu ko wa tan bi gbe ogbeni aye dee sanle ni se ni aye dee yoke ogbontarigi olofofo linda ti pada sori afefe o,0,yoruba "RT @user: Eyin temi eku ojumo, emi eyan yin ogbeni Taofeek Omo Gawat Omo bibu ilu eko Ni Massey, Eko mi eko Ilé 🏡, eko Oni baje #Tweet…",0,yoruba "Awọn Gomina ti n pe fun akoso ọlọpaa ipinlẹ fun igba diẹ Yari to jẹ Gomina ipinlẹ Zamfara sọ eyi lẹyin ipade apero ọlọjọ meji ti ile igbimọ asofin agba gbe kalẹ lori eto aabo ni orilẹede Naijiria. Ninu ọrọ rẹ, oni ''awọn se agbatẹru ọrọ ti igbakeji aarẹ, sọ wipe o pọn dandan ki ipinlẹ kọọkan o maa se isakoso awọn ọlọpaa wọn''. Igbakeji aarẹ, Yemi Osinbajo sọrọ lori anfaani ọlọpaa ipinlẹ kọọkan Gomina naa sọ siwaju wipe ''iye ọlọpaa ti o wa lorilẹede Naijiria kere si iye awọn eniyan ti o wa lorilẹede yii, eyi to s'afihan ailera awọn ọlọpaa lorilẹede yii"". Nigba ti Yari n sọrọ lori iye owo ti yoo naa awọn ipinlẹ lorilẹede Naijiria lati gbe ọlọpaa ka'lẹ ni ipinlẹ wọn, o wipe ""ko pọn dandan fun gbogbo ipinlẹ lati se igbekalẹ yii, sugbọn ki awọn to ba lagbara rẹ o se e"". Ile-isẹ iroyin fun ijọba apaapọ, NAN ranti wipe igbakeji aarẹ, Yemi Osinbajo, nigba se'pade naa lọsẹ ti o kọja, sọrọ lori anfaani to wa ninu ki ipinlẹ kọọkan o sakoso ọlọpaa ti wọn. Bi ọlọpaa ipinlẹ ṣe n ṣiṣẹ l'America L'orilẹẹde Amẹrica, ileesẹ ọlọpa ipinlẹ maa n mojuto awọn ohun to niise pẹlu iwadi iwa ọdaran. Isọwọ sisẹ wọn yatọ si ti ọlọpa gbogboogbo ; awọn ni wọn n mojuto igboke-gbodo ọkọ lawọn oju popona to jẹ ti ijọba ipinlẹ, aabo awọn araalu,ipese aabo fun gomina ipinlẹ, to fi mọ eto ẹkọṣẹ awọn to ṣẹṣẹ fẹ ẹ darapọ mọ ileesẹ ọlọpa abẹle, ati ọgbọn atinuda lori imọ ẹrọ ati sayẹnsi. Yatọ si eyi, wọn tun di alafo nla to wa laarin ọna ti ileesẹ ọlọpa agbegbe ati ti gbogboogbo n gba ṣiṣẹ. Bakanna ni wọn maa n ṣe iwadi ti wọn naa lori awọn iṣẹlẹ iwa ọdaran. Lara awọn ohun ti wọn maa n ṣe iwadi rẹ ni, awọn ẹgbẹ olokoowo egboogi oloro, awọn onifayawọ ibọn ati awọn ogbontagi ọdaran mi i. Ki iṣẹ wọn le ba so eso rere, awọn ileesẹ ọlọpa ipinlẹ ni i awọn irinṣẹ to ba igba mu to fi mọ awọn akanṣe ibudo ikọṣẹ l'orilẹede naa. O ti to aadọta ọdun ti wọn ti da ileeṣẹ ọlọpa ipinlẹ. Awọn ohun to niiṣe pẹlu bi awọn araalu ṣe n pọ si, to fi mọ idagbasoke to n de ba awọn ileesẹ lasiko igba naa lo fa a lo ṣe atọkun fun idasilẹ rẹ. Interview with Col. Hassan Stan Labo (Reitired Colonel) POINTS: No better time to start than now. reasons: Serious security challenges in nigeria demand establishment of state police police is better under state management fg can regulate no justification for abuse of police by state governors, laws should be passed to watch and guide top 3 things to do: 1. recruitment process must be thorough and pick the best hands 2. world class training on arms and civility 3. funding for logistics and wages",0,yoruba ikú ré kete lóríi wa torípé ònìí ni ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ àìkú,0,yoruba wá lẹ̀ẹ̀ní nípa aráyé: ti o nuni ti o ṣe pataki.,0,yoruba "ni Nitori eyi, ara eni lo ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba "Àtẹ́wọ́ (àtẹ́lẹ́-ọwọ́) labálà (ni a bá ilà), a ò mọ ẹni tó kọ ọ́ #Atelewo #Owe #Yoruba",0,yoruba "ní nípa ire àti ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìṣẹ́ ọ̀pọ́lọ̀.",0,yoruba Igisekele: Àwọn àgbà ọ̀jẹ̀ akọrin Fuji ń ṣèdárò Amoo Igisekele tó jáde láyé,0,yoruba "Ní nígbà àkerekere, Ọba ri Nitori eyi, ara eni lo je ti ibile.",0,yoruba àṣà kì í ṣe nílẹ̀ yìí nìkan mo lérò wípé o mọ̀ bẹ́ẹ̀,0,yoruba ìwà: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò.,0,yoruba "Ikọ iroyin BBC News Yoruba wọ igboro Abẹokuta tii ṣe ilu Oloye Ọbasanjọ lọ lati mọ ohun ti awọn eeyan ibẹ nii sọ nipa agba oṣelu naa. Abọ wa ni wi pe, bi awọn kan ṣe rii gẹgẹ bi eeyan to buru, awọn kan rii gẹgẹ bii ọmọ Naijiria rere ti ko yan ẹya, ede, tabi igun kan ni pọsin. Apapọ ọrọ wọn ni pe irin ṣi pọ lẹsẹ alajọ Ẹbọra Owu lati ninu ilakaka rẹ fun igbe aye idẹrun fun mutumuwa lorilẹede Naijiria. Abọ ree...",0,yoruba "Ní ní àìlẹ̀, Ìyá ri Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba "Ivory Coast vs Algeria: Ivory Coast já ìràwọ̀ Algeria lulẹ̀ nínú ìdije AFCON, ni wọ́n bá dèrò ilé",0,yoruba "Trafficking in Abuja: Ọkùnrin 15 ni mo ń ba sùn lọ́ọ̀jọ áti san owó ọ̀gá mi Èyí jẹ́ ǹkan ti Ngozi (eyí kìí ṣe orúkọ rẹ̀ gangan) ń là kọjá lójoojúmọ fún ọ̀pọ̀lọ̀pọ̀ oṣù nínú ilé ìtúra kan ní agbègbè Lugbe l'Abuja to jẹ olu ilu Naijiria. Ngozi dí èrò ilé Aṣẹ́wó lẹ́yìn ti àládúgbọ rẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Anambra fí lọ̀ọ́ pé oun yóò ràn án lọ́wọ́ láti baa rí iṣẹ́ láti le san owó ilé-iwé rẹ̀ ti o ba lé wá si ilú Abuja. ""Ọ̀gá mi a sọ pé ki ń wọ síkẹ̀tì pélébé àti búláòsì kékeré lati lọ le ara mi si ojú pópó. Ọkùnrin mẹ́ẹ̀dógun ni mò ń ba sùn ti wọ́n a sì san ẹgbẹ̀rùn kan náìrà fún ọgá mí"" èyí ni ọ̀rọ̀ Ngozi. Àwọn ọkùnrin tó wà nínú ayé wa gbúdọ̀ bọ̀wọ̀ fún wa - Adarí FIN Ajọ NAPTIP ni ìdá àádọ́rin ninu ọgọ́rùn un obinrin bii ti Ngozi ni wọ́n ti fí n ṣe aṣẹ́wo láti ìpínlẹ kan sí òmíràn ni orílẹ̀-èdè Naijiria. Ní ti Mercy (èyí kìí ṣe orúkọ rẹ̀ gangan) náà jẹ́ ọkàn lárá wọ́n. O sọ fún BBC pé wọ́n tan oun wá si ilé aṣẹ́wo náà ni agbègbè Lugbe ni Abuja. O ní lẹ́yin ti òun siṣẹ́ tan fún ọ̀pọ́ oṣù fun ọgá òun, ni oun wá gbìyànjú lọ́jọ́ kan lati sálọ sùgbọ́n ọ̀gá oun pada gbá òun mú, o si fi abẹ gé gbogbo ara oun yálayàla. Trafficking in Abuja: Ọkùnrin 15 ni mo ń ba sùn lọ́ọ̀jọ áti san owó ọ̀gá mi Ilé Aṣẹ́wó pọ̀ bàbì ní agbègbè Lugbe ni Abuja Àdúgbọ ti ilé Aṣẹwo yìí wa jẹ́ ibi kan ti àwọn òtòsì pọ sí jùlọ, bó tilẹ̀ jẹ́ pé àdúgbò náà kò ni ojú pópó kan gidi, síbẹ̀ àwọn ilé aṣéwo ti wọ́n fi páko kọ ló pọ̀ jùlọ. BBC ṣe àbẹwo si ilé aṣéwo yìí níbi ti ọ̀pọ́ àwọn ọdọmọbinrin pẹ̀lu aṣọ pénpé pọ si jùlọ ti àwọn ọmọ ọkùnrin àdúgbo náà si n tú iná igbó mímú ni ita otẹ̀lí náà. Helgies Bandeira: Ọ̀pọ̀ oúnjẹ Yorùbá ni à ń jẹ ni Brazil Akoroyin BBC náà ṣe bi ẹni pé oun ni àwọn ọmọbinrin kéèkèké ti oun fẹ́ mú wá si ibẹ̀. Ẹni to ba pàde sàlàye fún akọroyin BBC pé ko kan lọ mu yàrá kan ko si lo mú ọmọ náà wá fún iṣẹ́ síṣe O sọ́ fun akoroyin wa pé yóò maa san ẹgbẹ̀rún méèdógun náira lọ́sọọsẹ̀ fún owó yàrá. O fi kun un pé ti ọmọ ti o n mú bọ ko ba ti dagbà to lọ́jọ́ ori, o ní láti maa pe ọjọ ori rẹ̀ ni ogun ọdun ati jù bẹ́ẹ lọ. Iyara kan ninu ile aṣẹwo ni Lugbe Abuja Wọ́n sàlàye fún akọròyìn wá pé, ọmọ to ba mu wá yoo maa san ẹgbẹ̀run mẹwàá sí ẹgbẹ̀run mẹ́ẹ̀dogun lójoojúmọ pàápàá jùlọ bi o ba ṣe le ṣiṣẹ́ si. Ọ̀gá àgbà fun àjọ NAPTIP, Julie Okah-Donli sàlàyé fun BBC pé àwọn ọmọ kekeeke ti wọ́n ń lo fun àwọn iṣẹ́ ibi yìí ti pọ̀ gan ni orilẹ̀-èdè Naijiria. ""Níwọ̀n ìgbà ti àwọn tó ń lọ ilé aṣẹ́wo ba ti wà, àwọn ọmọ keekeeke náà ni wọ́n a maa lò."" Julie ni ajọ náà ti lọ kaakiri lati ka awọn ilé aṣẹ́wo ti wọ́n ti n lo àwọn ọmọ wẹ́wẹ́ náà mọ ti àwọn si ti ti omiran pa ti àwọn si gbe ẹni to nii lọ si ile ẹjọ. Donli ni Síbẹ̀ lẹ́yìn ti àwọn ti gbé wọ́n lọ si ilé ẹjọ, àwọn o sinmi láti maa ran àwọn ọmo ti wọn ko kúro nibẹ̀ lọ́wọ́, Ngozi àti Mercy pẹ̀lú àwọn ọmọ míràn ti ajọ náà gbà sílẹ̀ ni àwọn ti kó lọ si ibi ààbò kan ni ìlú Abuja nibi ti wọn ti n kọ́ iṣẹ́ ọwọ́.",0,yoruba wúlò. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò.,0,yoruba ẹ̀ká ojú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìwà: ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde wá.,0,yoruba "RT @user: KOKO INU IWE IROYIN: OJO KERINDINLOGUN: OSU KESAN, EGBAA ODUN-LE MEEDOGUN: 2015: http://t.co/ewPJtbYJ8V via @user",0,yoruba Yan àmì-àṣírí.,0,yoruba "Fún àpẹẹrẹ , atọ́kùn ètò lórí ẹ̀rọ amóhùnmáwòrán tó jẹ́ adàṣà - àtijọ́ - mú - ṣinṣin — ajìjàǹgbara ẹni tó ti fi ìgbà kan rí ṣe ìpolongo ìtako ìbupá — fúnnu lórí Twitter wí pé òun ti kópa nínú àwọn ìlànà - ìsìn ajẹmẹ́sìn tó léwu :",0,yoruba "tí Ọmọ fè lọ, Nitori eyi, ara eni lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó ga.",0,yoruba Mozilla (HTML),0,yoruba "ìbàdandun ìlú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba nípa ìròyìn tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìṣẹ̀: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba wúlò. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ìyá lo ni ẹ̀ká àwẹ eyti o gbe lori iwa rere.,0,yoruba "RT @user: @user e je ki a gbadura fun orile ede wa,ki asi fi owo ara wa tun iwa ara wa se,Nigeria si ma da....Ajumose ni o",0,yoruba àrọ́mọdọ́mọ kìnìhún nígbó ọmọ akọ ni ̀bá,0,yoruba "tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Nitori eyi, ara eni lo ni Nitori eyi, ara eni lo je ti ibile.",0,yoruba otù ifẹ́ orísun ìran yoòbá ò ní í tú ilẹ̀ yorùbá ò ní í tú ara kì yóò tu àwọn ìráṣẹ́ ikú gbogbo tó pètepèrò ibi ilẹ̀ẹ wa,0,yoruba "Ọ̀nà ti jìn gan an, àmọ́ kò jìn tó iye ọjọ́ tí àwọn baba wa fi ṣe ayé lọ́nà ìbílẹ̀.",0,yoruba ṣe kò yẹ kí àwọn òǹgbùfọ̀elédè ̀bá àti èdè ilẹ̀e ó wà lọ́fíìcì,0,yoruba Ìtalólobó tí a ṣàfihàn fún dúrọ́wà tàbí àtòjọ-ẹ̀yàn,0,yoruba ronú lọ́rọ̀. ti Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba àṣà ìlú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ẹkọ́: ti o nuni ti o nuni ti o tẹ.,0,yoruba rere. Ọba lo ni àṣà yorubá eyti o gbe lori ọ̀run dídì.,0,yoruba "bí ọ̀kan nínú wọn, kí òhun fi lè mú wọn lọ sí Ọ̀yọ́. Ní wọ́n bá gbà si lẹ́nu. Nígbà tí wọ́n dé Ọ̀yọ́, inú Aláàfin dùn láti rí àwọn Ẹkùn-Òsì àti àwọn èèyàn wọn. Aláàfin bá bi Adébẹṣin wípé,"""""""""""""""" níbo lo gbé kó yìí?"""""""""""""""" Ní àti ìgbà náà, ibi tí adébẹṣin ti pàdé àwọn",0,yoruba "Lowurọ Ọjọru nileẹjọ giga ti wọn ti n gbẹjọ lAbuja la ti gbọ pe agbẹjọro Maina ti fariga pe oun ko ṣoju Maina mọ. Adeola Adedipe lo n ṣoju ọkan lara awọn ti wn pe lẹjọ iyẹn ileeṣẹ Maina Common Input Property and Investment Ltd lori ẹsun ikowojẹ ti wọn fi kan Maina. Agbẹjọro naa ni idi ti oun fi fiwe ranṣẹ ni pe Maina ko san owo fun oun nitorinaa oun ko ni le ṣoju rẹ nile ẹjọ mọ. Bẹẹ naa lo tọrọ aforijin lọwọ adajọ Okon Abang lori pe oun ko yọju sile ẹjọ lati ọjọ yi ti wọn ti n sun ẹjọ siwaju leralera. Ninu ọrọ rẹ, adajọ Abang ni Adedipe mọmọ lati ma ṣe yọju sile ẹjọ lọjọ iṣẹgunni. O ni ko si iwe kankan ti adajọ ri gba lati ọdọ rẹ pe ki wọn yọnda oun ninu ẹjọ naa. Ni igbẹjọ to waye lọjọ Iṣẹgun, Adajọ ti ṣaaju ni ki wọn mu ọmọ Maina Faisal ti o kọ lati yọju sile ẹjọ. Bi nkan ti ṣe ri bayi, ko si ẹni to le sọ ibi ti Maina ati ọmọ rẹ salọ lati igba ti igbẹjọ wọn ti bẹrẹ. Adájọ́ ti pàṣẹ pé kí wọ́n mú ọmọ Rasheed Maina, Faisal, tó sá mọ́ ilé ẹjọ́ lọ́wọ́: Ọrọ ti Senetọ Ndume la kọkọ gbọ nipa alaga igbimọ ti ijọba Naijiria gbe kalẹ lati ṣatunto eto owo ifẹyinti, Abdulrasheed Maina to sa mọ ile ẹjọ lọwọ. Ni bayi, adajọ ile ẹjọ giga to gbe idajọ kalẹ pe ki wọn fi Senetọ Ndume si gbaga ni Kuje ti ni ki wọn wọgi le beeli ti wọn fun ọmọ Maina, Faisal ki wọn si mu u tori pe o sa mọ ile ẹjọ lọwọ. Adajọ Okong Abang tun ni ki wọn bẹrẹ igbẹjọ lori ẹsun ikowo ijọba pamọ ti wọn fi kan pẹlu titi ti awọn agbofinro yoo fi mu pada wa sile ẹjọ. Bakan naa ni adajọ sọ pe ki ẹni to se oniduro rẹ, asofin ile aṣojuṣofin apapọ to n soju Kaura-Namoda, Sani Umar Galadima yọju sile ẹjọ. Adajọ ni o gbọdọ wa lati ṣalaye idi ti awọn ko fi ni gba owo ọgọta miliọnu Naira to fi ṣ'oniduro fun Faisal. Aṣẹ ti Adajọ yi gbe kalẹ n waye lẹyin nkan bi ọjọ mẹta ti ile ẹjọ yi kan naa gbe aṣẹ iru rẹ kalẹ ki wọn mu Abdulrasheed Maina ti o sa mọ ile ẹjọ lọwọ. Maina to jẹ alaga igbimọ atunto ọrọ owo ifẹyinti ni Naijiria ni wọn fi ẹsun pe o lu biliọnu meji owo ijọba ni ponpo. Lọjọ Aje yi ni adajọ ni ki wọn fi Sẹnẹtọ Ali Ndume to ṣe oniduro Maina naa si ọgba ẹwọn to wa ni Kuje titi ti yoo fi san owo oniduro aadọta miliọnu Naira. Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ̀ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí Ẹwẹ lọjọ Iṣẹgun yi, igbẹjọ tẹsiwaju lori ẹsun ti wọn fi kan Maina tawọn eeyan mẹta si wa jẹri lori ẹsun ti wọn fi kan an yi. Agbẹjọro EFCC Mohammed Abubakar sọ lọjọ Iṣẹgun pe ati baba ati ọmọ ni ko ti yọju sile ẹjọ lati ọjọ kẹrinlelogun oṣu Kẹfa ọdun 2020. Faisal oniduro rẹ ati agbẹjọro rẹ ko yọju sile ẹjọ. Abdulrasheed Maina: Wo àwọn nkan tó yẹ kó mọ̀ kí o tó ṣe onídùró fún ẹnikẹni Ọjọ Aje ni ile ẹjọ giga ijọba apapọ nilu Abuja, paṣẹ ki wọn o fi Sẹnetọ Ali Ndume , lati ipinlẹ Borno si atimọle. Eyi ko ṣẹyin bi ẹni to ṣe oniduro fun nile ẹjọ, Abdulrasheed Maina, ṣe salọ. Maina ni laga igbimọ to wa fun ọrọ owo ifẹhinti ni Naijiria. Sẹnetọ Ndume gba lati ṣe oniduro Maina, lasiko ti ajọ EFCC, gbe lọ sile ẹjọ fun pe o ṣe mago-mago ọgọrun biliọnu Naira owo ajọ naa. Ṣugbọn, Maina si ti kuna lati pada yọju sile ẹjọ lẹyin ti wọn gba oniduro rẹ. Eyi lo mu BBC News Yoruba ba Amofin Sadiku Ibitayọ sọrọ lori awọn nkan to rọ mọ ṣiṣe oniduro fun ẹni to n j'ẹjọ. Oriṣi oniduro meji lo wa: Amofin ṣalaye pe oriṣi oniduro meji lo wa. Akọkọ ni eyi ti ileeṣẹ ọlọpa beere fun ati ti ile ẹjọ. ""Oniduro ti ileeṣẹ ọlọpaa maa n waye lasiko ti awọn ọlọpaa ko ti i pari iwadi wọn lati mu ki ẹni naa duro fun afurasi ọdaran. Wọn yoo kan sọ pe ki ẹni naa buwọlu iwe tabi fi iwe idanimọ rẹ silẹ. Awọn ọlọpaa yoo pada ranṣẹ pe e ti o ba jẹ dandan."" Ni ti ile ẹjọ, awọn ti ẹsun ti wọn fi kan wọn ba fi aaye silẹ pe wọn le maa gba ile wọn wa jẹjọ ni adajọ maa n gba oniduro fun. Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ Kini o gbọdọ mọ ki o to ṣe oniduro ẹnikẹni? Amofin Sadiku sọ pe ẹnikẹni to ba fẹ ẹ ṣe oniduro fun ẹni to n jẹjọ gbọdọ mọ, ki o si ni oye irufẹ ẹsun ti wọn fi kan ẹni to fẹ ṣe oniduro fun. O ni ewu ni ti oniduro ko ba mọ ẹsun ti wọn fi kan ẹni to n jẹjọ. Ti ẹni naa ba sa lọ, ori oniduro ni gbogbo atunbọtan ẹjọ yoo da le lori. O ṣalaye pe ẹni to fẹ ẹ ṣe oniduro gbọdọ mọ ẹni to n jẹjọ daadaa, titi de ile ati ẹbi rẹ. O si gbọdọ ni aridaju pe yoo wa sile ẹjọ lọjọkọjọ ti ile ẹjọ ba sọ pe ko wa, ti ko ni salọ. Yatọ si eyi, amofin ni ẹsun ti wọn ba fi kan ẹni naa ni yoo sọ iru oniduro ti adajọ yoo sọ pe ko mu wa. Bakan naa, iwọ ni wa a san owo ti ile ẹjọ ba beere fun lasiko to fẹ ẹ gba oniduro ẹni to n jẹjọ, ti ẹni naa ba fi salọ. Koda, ile ẹjọ yoo gbẹsẹ le dukia ti o ba fi sẹ oniduro fun ẹni to salọ. Ndume tí d'èrò ẹ̀wọ̀n nítori pé ó gba onídùróó Maina tí wọ́n kò rí mọ́ Ilé ẹjọ́ kan nílùú Abuja ti ni kí wan ti Ali Ndume tó jẹ́ sẹnátọ̀ láti Bornu mọ́lé, nítori bi Abdulrasheed Maina to ṣe oníduró fun ṣe pòórá. Ilé ẹja náà lọ́ja ajé lásìkò ìjòkó rẹ̀ nílé ẹjọ ni ki wọ́n ti Maina mọ́ ọgbà ẹ̀wọ́n níwọ̀n ìgbà ti ko rí mú jáde lásìkò tó yẹ kó wá jẹ́jọ́ ìwà àjẹbánu tó ṣe lásìkò tó wà nípò. Sáájú ni Ndume ti ṣe oníduró fún Maina ti wan fi ẹ̀sun méjìlá kan, tó fi mọ́ kíkó owó Nàìjíríà pamọ́ ní ìlú òkèrè. Ọ̀kan lára àlàalẹ̀ gẹ́gẹ́ bi oníduro ti wọ́n fi àdéhùn sí ni pé, Ndumne yóò máà tẹ̀lé Maina wá si ilé ẹjọ́ ní gbogbo ìgbà ti wọn ba nílò rẹ̀. Ẹ̀wẹ̀, àìmọye ìgbà ni Sẹnatọ Ndume ko ti ri Maina mu wá si ilé ẹjọ́. Nínú ìdájọ́ Adájọ́ Okon Abang lo sàlàyé pé, títí di àsìkò tó yóò fi le ṣe àmúṣẹ òníduro rẹ̀, yóò sán mílíọ̀nù 500 si àpò ìjọba Bákan náà ni ilé ẹjọ́ tún fún ìjọba àpapọ̀ láṣẹ láti ta ilé rẹ̀ tó wà ni Asokoro lati rí mílíọ̀nù ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta náírà kójọ. Adajọ́ náà ni wọ́n yóò tú Ndume sílẹ̀ ni ọgbà ẹ̀wọ̀n Kuje, ní kété tí o bá ti ṣètò gbogbo, tó sì san owó tó yẹ ki ó sàn.",0,yoruba lẹ̀ẹ̀ní nípa òkè: ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.,0,yoruba "Lati ọjọbọ ni ori ayelujara ti n ho ruru, ti ọpọ eniyan si n sọ oko ọrọ̀ si gomina ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde, ati ẹgbẹ oṣelu PDP, lori ipade itangbangba ẹgbẹ naa to waye. Ọpọ lo gbagbọ pe ko yẹ ki Gomian Makinde le pe iru ipade nla bẹ lasiko ti arun coronavirus n rin kaakiri ilu. Ṣugbọn nigba to ba BBC sọrọ, Akọwe ikede fun gomina Makinde, Taiwo Adisa sọ pe gbogbo igbesẹ to yẹ ni awọn gbe nibi ipade naa ni ibamu pẹlu imọran awọn eleto ilera. Ṣé Makinde kò wá rugi oyin báyìí lórí ìpàdé ìtagbangba PDP tó ṣe níbàdàn Láì náání àjàkálẹ̀ àrùn coronavirus? Ẹ wo ohun tí baba Adeboye sọ lórí ọ̀rọ̀ Coronavirus Ìjọ kò ní tilẹ̀kùn ilé ìjọsìn nítorí àrùn Coronavirus - Ondo PFN Ọkùnrin kan kú lẹ́yìn tí wọ́n lù ú 'fún pé ó ní coronavirus' O ṣalaye pe gbogbo awọn to wa sibi ipade itagbangba naa ni awọn fun ni ọṣẹ apakokoro (hand sanitiser) l'ẹnu ọna abawọle sibi ipade. ""A pa di dandan fun gbogbo olukopa lati fọ ọwọ wọn l'ẹnu ọna, ati lati fi ọṣẹ apakokoro pa ọwọ ki wọn o to o wọle, lai yọ ẹnikẹni silẹ. Ti mo ba ni kin sọ iye ọṣẹ ti a ra, yoo to ẹgbẹrun mẹwa. Nitori pe iye ti a ra pọ ju iye eniyan to wa si ipade. O tẹsiwaju lati sọ pe awọn ṣe ayẹwo ilera fun gbogbo awọn to gba papakọ ọkọ ofurufu wọle. Lori ọrọ ti ijọba ipinlẹ Ekiti sọ pe awọn sọ fun ijọba ipinlẹ Ọyọ nipa ọmọ America to ku si ipinlẹ Ekiti, ati awọn ti wọn jọ wa si Ekiti, ti ọkan lara wọn si ti ni coronavirus, Adisa sọ pe ijọba Ekiti ko sọ fun ijọba Ọyọ tẹlẹ. ""Ọjọbọ ti ijọba Ekiti kede faye naa ni wọn sọ fun wa. Ao gbọ si tẹlẹ. Koda, wọn fi atẹjiṣẹ ṣọwọ sori foonu kọmisana eto ilera ipinlẹ Ọyọ."" O sọ pe ijọba ti lọ si ile ti wọn de si, wọn si ti fin oogun apakokoro sibẹ. Ati pe wọn ti n gbe igbesẹ si n lọ lọwọ lati mọ awọn to ba wọn ṣiṣẹ, bi itọju ile, aṣọ fifọ lasiko ti wọn fi wa nilu ibadan l'agbegbe Bodija.",0,yoruba "RT @user: Elédùmarè Ọba Atẹ́nílẹ́gẹ́lẹ́gẹ́-fi-orí-ṣe-agbeji-ẹni, mo ké pè Ọ́ ní òórọ̀ yìí, kí O máà ṣaláyì jẹ́ mi. Gbé orí mi sókè. Mú…",0,yoruba Ǹjẹ́ o mọ̀ pé 1859 la ṣí ilé ìwé CMS Girama; ilé-ẹ̀kọ́ àkọ́kọ́ nílùú Èkó? #Yoruba #Njeomo https://t.co/QYeP2HEWGL,0,yoruba "Ninu ọrọ to bawọn ọmọ Naijiria sọ, eyi to fi soju opo Twitter rẹ l'Ọjọbọ ni Bakare ti bọhun nipa iṣẹlẹ ibanujẹ naa. Bakare ni asia orileede Naijiria ti ni abawọn ẹjẹ awọn ọmọ wa pẹlu ikọlu tàwọn ologun ṣe sáwọn oluwọde ni Lekki. ""Abala keji orin ibilẹ Naijiria lo ni a o fi asia ailabawọn le awọn ọmọ wa lọwọ amọ o ṣe ni laanu pe Asia to ni abawọn ẹjẹ wọn, la fẹ gbe le wọn lọwọ"". Oluṣọ-agutan ìjọ Latter Rain fikun pe iwọde EndSARS to waye jẹ ipari iran kan lorilẹ-ede Naijiria ati ibẹrẹ iran miran. End of Twitter post, 1 O ni iwọde naa jẹ ifarahan ibẹrẹ orile-ede Naijiria tuntun ati ifehonuhan awọn araalu ti wọn n pe ni eeyan lasan. Ọlọ́pàá mẹ́fà, àgọ́ ọlọ́pàá márùn-ún ló bá wàhálà ìwọ́de #ENDSARS lọ nípìnlẹ̀ Oyo - Kọ́mísánnà Ẹ má à gbìyànjú láti bo àṣírí ìpànìyàn tó wáyé ní Lekki, á ní ẹ̀rí tó dájú - Amnesty International Àwòrán nǹkan aláràmbarà oríṣiríṣi táwọn jàǹdùkú jí gbé lẹ̀yìn ìwọ́de EndSARS Àwọn tó mọ̀ nípa ìpànìyàn Lekki yóò fojú winá òfin - Sanwo-Olu sí Becky Anderson Àjẹ́ ké lánàá, ọmọ kú lónìí ni ọ̀rọ̀ Tinubu àti ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Tollgate - Bode George "" Iwọde EndSARS lo fi da mi loju pe iran tuntun ni Naijiria ti dìde, ti wọn fi isọkan sọrọ, ti wọn ko si gba ki wọn pa ina wọn tabi fi ọwọ bo wọn lẹnu tori asiko SọrọSoke la wa yii."" Nigba to n ṣe iranti ikọọkan awọn eeyan to ku lati ọwọ ọlọpaa SARS ati lasiko iwọde, Bakare wa kesi ijọba lati fi imu awọn ologun to kọlu oluwọde ni Lekki danrin. Bakan naa lo tun rọ ijọba lati ṣe amusẹ ibeere awọn ọdọ, ki iku awọn oloogbe ma ba a ja si asan.",0,yoruba "kọ eḳọ nípa ire àti ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìṣẹ́ ọ̀pọ́lọ̀.",0,yoruba """Mo maa n sọ ọ pẹlu idaniloju pe mi o ni ọrẹbinrin gẹgẹ bi olorin amọ mo ri i pe kii ṣe agbara mi"". Ajihinrere J.A Adelakun gangan ni orukọ rẹ ṣugbọn ko sẹni to fẹrẹẹ mọ agba olorin ẹmi yii pẹlu orukọ rẹ bikoṣe ""Amọna tete bọ"" eyi tii ṣe akọle orin to sọ ọ di olokiki laye. Ajihinrere Adelakun ṣalaye iru igbe aye to maa n gbe tẹlẹ ko to ba Ọlọrun pade to si bẹrẹ iṣẹ orin ẹmi ti awọn eeyan lee ka si ara awọn isọri orin ti kii ku lailai(Evergreen). Baba Adelakun ni ni ọdun 1972 lasiko to wa lẹnu iṣẹ ologun ni o ba Jesu pade nigba to sin ọrẹ rẹ kan lọ si ijọ CAC ti ọkan rẹ si yi pada lati maa sin Ọlọrun. À ń ké síi yín o, bẹ́ẹ̀ bá ń lo òògùn amú ǹkan ọkùnrin lè fún ìbálòpọ̀ gbígbóná, àrùn rọpa rọsẹ̀ ń bọ̀ o! - NAFDAC Ẹni tó gé orí olóri fi ṣe ògùn owó náá ṣán kú nínú àtìmọ́lé ọlọ́pàá l'Ondo Babatunde lọ bá adari Hoteeli ṣe àjọyo, ó pade iku ọbẹ gbígbóná Kà nípa ìbẹ̀rẹ̀ ìyàwó Ooni Ife, Olórí Silekunola Moronke Náómì, Wòlíì tó di Ayaba Ile Ife ""Mo mu Claro (nkan kekere ti a maa n mu fi mu ori ya) dani mo si sọ fun Jesu pe iwọ Jesu ti mo ṣẹ n gba yii, too ba le ṣee ki n ma mu gbogbo nkan ti mo n mu yii mọ, maa sin ọ"". Ajinhinrere yii ni idile Musulumi ni oun ti jade wa, amọ lati igba ti oun ti gba Jesu ni oun ti dara pọ ,ọ ẹgbẹ akọrin ti aye rẹ si yipada. Lati ibẹ loun naa ti fẹran orin ti wọn si bẹrẹ ẹgbẹ ori ""Ayewa"" eyi to tun jẹ ọkan lara awọn orin wọn. ""Ologun n bẹ lode, Decree lojoojumọ, Satani Oluwa ba ọ wi o dẹhin lẹyin mi..."". Gbogbo ọrọ orin yii ni Ajihinrere Adelakun ni ko si ninu bi awọn ṣe kọkọ kọ orin amọ ẹmi mimọ kan gbe e jade nigba ti wọn de yara orin ti wọn ti fẹ ka a silẹ. 'Ohun tí ojú èmi Alásè gan rí lásìkò ọdún yìí, bàyìí la ṣe runs ẹ̀ o' DSS ní kí n di ológbò bíi Sunday Igboho, ojú mi rí tó ní àhámọ́ DSS l'Abuja- Ifasooto",0,yoruba ìyẹ̀ alẹ́. Èyí ni òun tí a ní nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Bàbá lo ìgbà ọkọ.,0,yoruba "♫ Láílo láílo! Láílo, ọmọ ìyá mẹ́ta ... ♫",0,yoruba "NAPTIP ni ki awọn eeyan ṣọra fun ẹtan awọn kọlọransi lori idije ife FIFA ni Russia Ajọ NAPTIP ni gbogbo awọn ajọ, ileeṣẹ ati ijọba lẹkajẹka gbogbo ti wọn n ran awọn eeyan lọ si orilẹede Russia ni ijọba apapọ ti ni ki wọn gba aṣẹ 'o wẹ yan kainkain' lọwọ ajọ naa ki wọn to mu irinajo wọn pọn lọ si Russia. NAPTIP ní òun kẹ́fín pé àwọn kan fẹ́ máa lo àǹfàní ìdíje FIFA ní Russia fi kó àwọn ọ̀dọ̀ lọ lọ́nà tí kò bófinmu Oludari ẹka iwadi ati itọpinpin ni ajọ NAPTIP, Josiah Emerole lo yannana ọrọ yii nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ lori awọn afunrasi kan ti ọwọ ba ni papakọ ofurufu Muritala Mohammed to wa nilu Eko ti wọn n gbimọran ati ko awọn ọdọ mẹwa lọ si orilẹede Russia fun owo kotọ. Ni ọjọ abamẹta to kọja lọwọ awọn oṣiṣẹ ọtẹlẹmuyẹ ajọ naa tẹ awọn eeyan marun kan, Esan mathew to jẹ ọlọpa, Stephen Fayẹmiwo to jẹ oṣiṣẹ ayẹwo, Azeez Olowo, Idowu fashakin ati Eni Godwin. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ajọ NAPTIP ni ajọ ere bọọlu lorilẹede Naijiria, NFF nikan lo tii fi orukọ awọn eeyan to n ran lọ si Russia fun idije ife ẹyẹ FIFA ṣọwọ fun ayẹwo ni ajọ NAPTIP. ""Oludari agba ajọ NAPTIP ti sin araalu ni gbẹrẹ ipakọ ṣaaju asiko yii pe awọn kọlọransi ẹda kan yoo maa fi idije ife ẹyẹ FIFA ti yoo bẹrẹ ni Russia boju lati ko awọn eeyan lọ si oke okun fun owoo kotọ. Ara wọn ni a si ti n ri bayii"" Oludari ẹka iwadi ati itọpinpin ni ajọ NAPTIP wa fi da awọn araalu loju pe awo oju lalakan fii ṣọri ni ajọ naa ti da bayii lati rii pe awọn ti ko ni iṣẹ to tọna lati ṣe lorilẹede Russia ko raaye ati lọ kuro lorilẹede yii lọna ti ko tọ.",0,yoruba ipilẹ̀ ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìṣẹ̀: ti o lẹ.,0,yoruba "àkokò, Alàji lo ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.",0,yoruba "Ìyá fè se, Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba "Aarẹ ajọ awọn Amofin ni Naijiria, (NBA) ti paarọ ọwọ. Ẹni ti ko tii gba oye imọ ijinlẹ ninu akọsẹmọsẹ ofin ni oye naa ja mọ lọwọ. Orukọ e ni Ọgbẹni Olumide Akpata Won se ikede yi ni nkan bi ago kan oru Ọjọbọ Lati ọdọ Alaga awọn to n ri si eto idibo awon amofin, Ọgbeni Taiwo Taiwo (SAN). Akpata gbe gba oroke pẹlu iwọn ida aadọta ninu ọgọrun un Ọgbeni Babatunde Ajibade ni ẹni to tun tẹ le Ogbeni Akpata ninu eto idibo naa pẹlu ida mẹtalelogun ninu ọgọrun un Eeyan Ogoji ni ko kopa ninu eto idibo naa, ti isiro gbogbo oludibo si jẹ 16,519 29,636 ni akpapọ gbogbo ọmọ ẹgbẹ ti o ko ipa ninu idibo naa. Awon ipo to ku ti won dije fun ni igba keji aare akọkọ ati ẹkeji, akọwe apapọ ,igba keji akọwe, akapo ati bẹẹ bẹẹ lọ. Awon ti won jọ dije dupo ni Diakoni Dele Adesina (SAN) ati Omọwe Babatunde Ajibade (SAN). Awọn miran ti wọn tun dije dupo mii ni: Ogbẹni John Martin fun ipo igbakeji akọkọ: Ogbẹni Adeyemo Kazeem fun igbakeji ẹkeji: Arabinrin Joyce Oduah, akọwe apapọ ati awọn mii Mọ̀ diẹ sii nipa Olumide Akpata: Akpata jẹ agbẹjọro to n soju awon oloko owo ati onisẹ aje. O tun jẹ ẹni akọkọ ti ko gba oye imọ ijinlẹ ninu ofin ti yoo fi di akosemose (SAN) to dije dupo aarẹ to si wọle lati ọdun 1989 nigba ti oloogbe Alao Aka-Bashorun fi n dari gbogbo eto tẹlẹ. Ajibade sọ ninu ọrọ rẹ pe: ""Mo ti pe Olumide lati kii ku oriire gege bii Aare wa to jẹ́ ọgbọn iru aarẹ bee. ninu eto idibo to waye loojo kokandinlogbon si ogbon ọjọ, osu keje, ọdun 2020",0,yoruba "Aarẹ Faure Gnassingbe to wa lori aleefa lọwọlọwọ n dije fun saa kẹrin lẹyin to di aarẹ ilẹ Togo lọdun 2005 nigba ti baba rẹ, Eyadema Gnassingbe aarẹ orilẹede naa tẹlẹ papoda. Eyadema fipa gbajọba lorilẹede Togo lọdun 1967, o si jẹ aarẹ ilẹ naa to fi di ọdun 2005 to ku. Ọmọ rẹ, Faure to ti ṣe ijọba fun saa mẹta ọtọọtọ, n gbegba ibo aarẹ fun saa kẹrin lati tẹsiwaju ijọba ẹbi Gnassingbe lorilẹede Togo. O ti le ni aadọta ọdun bayii ti ẹbi Gnassingbe ti n ṣe ijọba orilẹede Togo. Lati le dẹkun awọn alatako rẹ, aarẹ Gnassingbe ṣe agbekalẹ ofin kan eyi to sọ pe aarẹ ilẹ Togo ko le lo ju saa meji ọlọdun marun un marun un lọ. Eleyi tumọ si pe Gnassingbe si le jẹ aarẹ orilẹede naa di ọdun 2030 to ba wọle idibo gbogbogbo toni ati to ba tun ṣe saa kan sii. Gnassingbe ṣeleri pe oun ṣetan lati tun ọrọ aje orilẹede Togo ṣe ti oun ba wọle. Iṣẹ ati oṣi n ba awọn eeyan Togo finra, akọsilẹ ajọ IMF tiẹ sọ pe orilẹede naa lo tosi ju sikẹjọ lagbaye. Awọn oludije alatako mẹfa ni yoo figa gbaga pẹlu Faure ninu ibi gbogbogbo ọjọ Abamẹta.",0,yoruba ipinle kogi owo awon agbofinro ti ba enimerin tofi ipa ba omo odun mejidilogun lo dail,0,yoruba Àyẹ̀wò àti ìdánwò egbògi àjẹsára tí yóò ṣiṣẹ́ dé góńgó tí a gbé ṣe lọ́nà tí ó bá ìwà - ọmọlúwàbí mu máa ń gba àsìkò .,0,yoruba RT @user: @user adupe mope oun lawo adupe mope Adore more oun lawo adore more Eni ti o dupe oore ana Koni le gbore toni bo(Obara…,0,yoruba Àwòrán ojú - ewé ìwé ìrìnnà látọwọ́ọ Jon Evans ( CC BY 2 . 0 ) .,0,yoruba o ṣé zaddy jẹ́ ka plan nǹkankan nínú deehem,0,yoruba Àkóbì níjó òní nípa àṣà ìdílé lo je ti ibile.,0,yoruba Ọrọ yii lọpọ eeyan n gba bi ẹni n gba igba ọti lori ayelujara opo Twitter papaajulọ lati igba ti Arsenal ti ri iya he lọwọ Liverpool ninu idije Carabao Cup ni papa iṣere Anfield lalẹ Ọjọru. Iroyin sọ pe Mourinho n wa iṣẹ si ilẹ Gẹeṣi nitori nibẹ lo ti ṣaṣeyọri nibi to gba ife ẹyẹ idije Premier League nigba mẹta ọtọtọtọ. Ilẹ iroyin ESPN tiẹ sọ pe Mourinho ṣetan lati ṣe akọnimọọgba ikọ Arsenal ti wọn ti fọwọ osi juwe ile fun Unai Emery. Eleyi jẹ iyalẹnu fun ọpọlọpọ ololufẹ ere bọọlu papaajulọ idije Premier League nitori Mourinho sọrọ alufansa si Arsenal fun ọpọlọpọ ọdun. Mourinho ti kọ lati gba iṣẹ akọnimọọgba ni ẹgbẹ agbabọọlu Benfica ati ikọ agbabọọlu kan lorilẹede China. Bakan naa laagbọ pe o ṣeeṣe ki Mourinho pada si ikọ Real Madrid eleyi to ti tukọ rẹ ri tẹlẹ.,0,yoruba "Top Democrat Nancy Pelosi says lawmakers were not satisfied by the president's briefing on the Iran air strike Idibo naa ni awọn ile igbimọ asofin di fun pẹlu iye awọn ẹgbẹ oṣelu Democrats si ju ti awọn Republican lọ, pẹlu ibo 224-194. Amọ o ṣeeṣe ko ni idena ni ile Asofin Agba ni bi ti ẹgbẹ oselu Republic ti pọ ju Democrats lọ. Awọn asofin naa n dibo wi pe Aarẹ Trump yoo nilo ki ile igbimọ Aṣofin buwọlu igbeṣẹ aarẹ lori orilẹede Amerika. Amọ orilẹede Iran ati US ko i tii sọ boya ija naa si tẹsiwaju, ti wọn yoo si gbena woju ara wọn. Ni ọsẹ yii ni orilẹede Iran yin ado oloro si ibudo ikọ ọmọogun ilẹ Amerika to wa ni Iraq, amọ ko si ọmọ ilẹ Amerika naa to ṣeṣe ninu ikọlu naa. Eleyii ko ṣẹyin bii ilẹ Amerika ṣẹ pa Ọgagun ati adari ikọ ọmọogun ilẹ Iran,Qasem Soleimani ni papakọ ofurufu Baghdad ni orilẹede Iraq. Nitori naa ni idibo naa ṣe paṣẹ fun Aarẹ Donald Trump lati maṣe lọ ikọ ọmọogun ilẹ Amerika lati koju ija si Iran lai gba aṣẹ ilẹ igbimọ asofin orilẹede naa.",0,yoruba A fi àṣẹ lò ó .,0,yoruba RT @user: Won Ti Pa Oga Oniroyin Ni Ilu Eko: Ogbeni Dimgba Igwe to je igbakeji alase ati olootu agba fun ile ise iwe iro... http://t.co/L…,0,yoruba Àkóbì níjó òní nípa ọlọ́run. A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà.. Eyi ni adetokun ninu ilu.,0,yoruba "Ọkùnrin kan ní Kano ṣ'ayẹyẹ ìsọmọlórúkọ lẹ́yìn tó yí orúkọ padà sí Buhari Ọkunrin kan niluu Kano lo yii orukọ ara rẹ pada si orukọ aarẹ ọrilẹ-ede Naijiria, Muhammadu Buhari. Ọkunrin naa to jẹ ẹni ọdun mejidinlogoji tilẹ ṣe ayẹyẹ ikomọjade ọtun lati dawọọ idunnu yi yi orukọ rẹ si Muhammadu Buhari. Oriṣiiriṣii aworan lati ibi ayẹyẹ isọlmọlorukọ ni ọpọlọpọ eeyan ti gbe soju opo ayelujara. Iroyin to tẹ wa lọwọ fidi rẹ mulẹ pe lopopona to lọ si ọgba iko ẹranko si ni ayẹyẹ naa ti waye ni Zoo road ni olu ilu Kano. Okunrin naa fiwe pe Aarẹ Buhari ati gomina Abdulahi Ganduje sibi ayẹyẹ isọmọlorukọ naa. Ọkùnrin kan ní Kano ṣ'ayẹyẹ ìsọmọlórúkọ lẹ́yìn tó yí orúkọ padà sí Buhari Ọkùnrin kan ní Kano ṣ'ayẹyẹ ìsọmọlórúkọ lẹ́yìn tó yí orúkọ padà sí Buhari Koda ọkunrin naa pa ẹran agbo lati fi dawọọ isọlmọlorukọ ara rẹ gẹgẹ ilana eṣin musulumi. Ọkùnrin kan ní Kano ṣ'ayẹyẹ ìsọmọlórúkọ lẹ́yìn tó yí orúkọ padà sí Buhari Eleyi le jẹ iyalẹnu fun ọpọ eeyan, paapaa lasiko ti awọn eniyan n sọrọ lori aibọwọ fun ofin ile ẹjọ ti wọn ni pe o wọpọ lasiko aarẹ Buhari yii. Bẹẹ, awọn eniyan ilu Kano ni ko ri bẹẹ lọdọ ti wọn nitori pe awọn ara ipinlẹ naa tu yaaya tu yaaya dibo fun Aarẹ Buhari ninu idibo gbogbogbo ọdun 2015 ati 2019. Silas Robotic Engineer: Kò sí ǹkan rere tí ọmọ Nàìjíríà kò lè ṣe",0,yoruba adupẹ o yoruba ọpẹ púpọ lọwọ gbogbo alàtà oniru oniyọ ẹṣe o,0,yoruba happy international womens day to every girl and woman and all persons that identify as female in the world a ku odun iya iya ni wura iyebiyeojo ti iya bakuni dingi eni womi,0,yoruba Ìlú yorubá lo ni ẹ̀ká àwẹ eyti o gbe lori iwa rere. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba "mi owó àkokò, Alàji lo tun se joko.",0,yoruba "Ní orílẹ̀ - èdèe Nàìjíríà , àwùjọ ìbánisọ̀rọ̀ orí ayélujára jẹ́ ibi tí ìròyìn ìtakora - ẹ̀yà tẹ̀gbintẹ̀gbin àti ìsọkiri ti máa ń gbilẹ̀ bíi ṣẹ́lẹ̀rú lásìkò ìdìbò .",0,yoruba se se. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìṣẹ̀: ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba "Àwọn kan lè ní #Ethiopia jí iṣẹ́ ọ̀nà ara adé wọ̀nyí láti #Britain. """"""""""""""""""""""""""""""""@user: #HaileSelassieI, #EmpressMenen http://t.co/R7a90cTgVv""""""""""""""""""""""""""""""""",0,yoruba "Síbẹ̀ , akọbúlọ́ọ̀gù Zone9 ṣe àtúnlò ìfẹ́ - ìlú - ẹni nínú ọ̀rọ̀ àti ìṣe .",0,yoruba "Ẹgbẹlẹgbẹ ọ̀dọ́ Nàìjíríà ló ń wáṣẹ́ ajé lọ sílẹ̀ òkèèrè Ọrọ àìríṣẹ́ ṣe àwọn ọdọ Naijiria ti sọ wọn di oṣiṣẹ àwọn iṣẹ ti kò pọ́n nilé nílẹ̀ okeere bii Libya, Italy, France àti bẹẹ bẹẹ lọ. BBC Yorùbá fọrọ wa diẹ ninu àwọn tijọba ko de lati Libya lẹnuwo. Wọn gbagbọ pe, o sàn lati lọ jiya ni Yuroopu ju ki ebi máa pa awọn nile ni Naijiria lọ. Ọna abayọ ti awọn to ku ti wọn ṣi n jiya ni Libya fi le wa sile ni ki ijọba Naijiria rọgun si àwọn ti wọn ti ko de lapa, ki wọn fun wọn niṣẹ oòjọ́ tabi ki wọn da wọn l'ókowò. Igbesẹ yii yoo jẹ ko wu awọn to ku lọhun lati wale. Nkan ti ojú wa n ri lọhun pọ gan an ni, ọ̀pọ̀ obinrin ni wọn fi ń ṣaṣẹwo nilẹ okeere bayii. Wọn gbà pe, ó sàn lati ta awọn nkan ìní wọn lati ri owó lọ silẹ okeere ju ki wọn duro si Naijiria ti kò ti si ounjẹ ati ètò ààbò to yaranti. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:",0,yoruba "Ko si si idi meji ti adajọ Mohammed la kalẹ ju wi pe, ni igba kan ri sẹyin, Ọmọyẹele Soworẹ to ni ileeṣẹ itẹwe iroyin Sahara Reporters ti fi ẹsun kan oun ri nigba meji ọtọọtọ pe oun gba owo lori awọn nnkankan lati da kẹkẹ ẹjọ nu. Soworẹ tọ ile ẹjọ giga apapọ lọ lati gba aṣẹ pe ki ajọ DSS ye tẹ ẹtọ ọmọniyan oun mọlẹ ati pe ki ile ẹjọ paṣẹ ki DSS san ẹẹdẹgbẹta miliọnu naira gẹgẹ bii owo gba maa binu fun oun. Adajọ naa ni ọpọlọpẹ awọn agbẹjọro agba meji kan lo yọ oun ninu ọfin ẹsun naa. Oluwo Divorce: ko si ẹni ti kò mọ pé ọmọ ilẹ̀ òkèrè ni mó fi ṣe aya Onidajọ Mohammed ni idajọ ẹjọ naa lee fi si ibikibi. O ni ti idajọ oun ko ba gbe Soworẹ, o lee ro wi pe oun fi gba ẹsan iroyin ti iwe iroyin rẹ gbe jade nipa oun ni. Amọṣa agbẹjọro fun Soworẹ, Amofin Fẹmi Falana, SAN ṣalaye pe oun ko mọ si iroyin ti adajọ n sọrọ rẹ naa. O ni nigba to ti ri bayii, ko si oun meji ju pe ki adajọ yọ ọwọ rẹ kuro ninu ẹjọ naa ni. Agbẹjọro fun DSS, Godwin Agbadua si faramọ eyi.",0,yoruba "Àwọn aláṣẹ Greek , tí ó ti ṣán àwọn iléèwé pa , tí ó sì ti f'òfin de àpéjọ lójú ọ̀nà àti dènà àjàkálẹ̀ , rọ Iléèjọsìn náà láti ṣe àtúnwò .",0,yoruba ri pe ṣe iyalẹnu wey ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ àti ìbi tí wọn wà.,0,yoruba "fi, Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba "A kò tilẹ̀ mọ ẹni náà tí ó tọ́ láti tukọ̀ orílẹ̀ - èdè Angola , báwo ni ọ̀dọ́ tí kò níṣẹ́ tí kò lábọ̀ yóò ṣe rí owó gba ìwé ẹ̀rí ?",0,yoruba "joko, Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba "àìlẹ̀, Ìyá ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde nìlẹ̀̀ní sáàrí ti nípa ìtànká àti ire ènìyàn.",0,yoruba RT @user: Pe kini? RT @user: Ǹjẹ́ ẹ ti gbọ́? #GbengaAdeboye #AlhajiPastorOluwo,0,yoruba "yóò rò papa re yóò ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.",0,yoruba Eégún tí ń k'éwì ẹ̀ṣà; ewì eégún ń pe Ẹ̀ṣà Ọ̀gbín egúngún àkọ́kọ́ ni wọ́n ń pè. #AraOrunKinkin,0,yoruba ìlú tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba Coronavirus: Seyi Makinde ní ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá ọṣẹ apakòkòrò 'hand sanitiser' lòun fi dènà coronavirus nípàdé ẹgbẹ PDP ní'bàdàn,0,yoruba "Aparadà ijó ìta - gbangba kan “ fò sókè """""""" sí orin soca ní orí ìtàgé ní Queen's Park Savannah , ní Ijó ìta - gbangba ọjọ́ Ìṣẹ́gun , ọdún - un 2009 .",0,yoruba "Ara eni lo ni ìgbà mi owó àkokò, Ìyá lo tun se lọ.",0,yoruba "kakaaki. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "àkerekere. Nitori eyi, ara eni lo ni ẹ̀ká àwẹ eyti o gbe lori àìmọ́ kọ.",0,yoruba Kódà ìṣàmúlò Twitter Aliyev dà gẹ́gẹ́ bí wèrè aládàásọ̀rọ̀ ju ìgbìyànjú ìbá ará ìlú sọ̀rọ̀ lọ .,0,yoruba Ta ní í sọ bóyá gbólóhùn kan lè fa rògbòdìyàn ?,0,yoruba "Àwọn tí ọ̀rọ̀ náà sojú rẹ̀ ní ìjánnú ọkọ̀ ló da isẹ́ sílẹ̀ tó sí yawọ ọjà tí ọ́pọ̀ ẹ̀mí ba ìsẹ̀lẹ̀ náà. O ni gomina Kayode Fayemi o si nile ni o ṣe ran oun lati wa wo ohun to ṣẹlẹ, o si ṣeleri pe ijọba yoo san owo itọju awọn to wa nile iwosan bẹẹ si ni yoo tun ọja naa ṣe. Ileesẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ekiti ti ni eniyan mejila lo padanu ẹmi wọn ninu ijamba ọkọ to waye ni alẹ Ọjọ Satide ni ipinle Ekiti, ti ọpọlọpọ si farapa. agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpaa naa, Caleb Chukwu lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ ni, ọkunrin mẹfa ati obinrin mẹfa lo ku ninu isẹlẹ naa loju ẹsẹ. Eyi waye nigbati ọkọ naa ya lọ kọlu ọkọ ayọkẹlẹ kan, ọkọ Akọta kekere ati ile to wa ni iwaju agbeegbe ọja Iworoko ni ipinlẹ Ekiti. Amọ awọn miran sọ wi pe awọn ti o ku ninu isẹlẹ naa ju bi o se yẹ lọ, ati wi pe idile wa ninu awọn to padanu ẹmi wọn. Lori ẹsun wi pe oloselu lo ni iresi to wa ninu ọkọ naa, Chukwu ni awọn ko lee sọ pe bi ọrọ naa se ri niyẹn, sugbọn awọn mọ wi pe ẹnikẹni lorilẹede Naijiria lo le e lo ọkọ nla lati fi ko ẹru lati ibi kan si omiran. Amọ, eniyan kan ti ọrọ naa se oju rẹ sọ wi pe ọkọ nla naa n gbe irẹsi to jẹ ti oloselu kan ni ipinlẹ Ekiti ti oun dije du ipo sẹnatọ ti yoo ma ṣoju ipinlẹ naa nile igbimọ aṣofin agba. Iroyin ni ìjánu ọkọ naa kọ iṣẹ́ sílẹ̀ tó sì yà lọ bá àwọn èèyàn nínú ọjà naa. 'Twitter ló gbà mí lọ́wọ́ ikú' Amọ, awọn miiran sọ wi pe awọn ti o ku ninu isẹlẹ naa ju bi o se yẹ lọ, ati wi pe idile wa ninu awọn to padanu ẹmi wọn.",0,yoruba "RT @user: @user @user @user Ė şé o, Komíşómà wa! Kí àwa omo Òduà jákèjádò àgbáyé gbìyànjú làti tùnbò gbè èdè, às…",0,yoruba ni òun tí a ní nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ àti ìbi tí wọn wà.,0,yoruba "Fidio kan to n milẹ titi loju opo ikansiraẹni lori ayelujara lo ṣafihan bi iṣẹlẹ naa ṣe waye. Ninu fidio naa ni Naira Marley ti ṣi ferese ọkọ ayọkẹlẹ to wa ninu rẹ, to si n na owo jade si awọn ololufẹ rẹ lori popo. Bo tilẹ jẹ pe ọkọ ti Naira Marley wa ninu rẹ wa lori ere, awọn ololufẹ rẹ ọhun n kii ni mẹsan an mẹwaa, ti wọn si n pariwo ""Marley, o pọ, o pọ."" Awọn kan lara awọn eeyan naa wa lori alupupu, ti awọn alupuipu naa si n sare tete tẹle ọkọ Naira Marley lori ere. Nigba ti Naira Marley na N500 jade si awọn meji kan lara awọn eeyan naa to wa lori alupupu, ti wọn si gba owo naa tan ni wọn ya bara sẹnu ọkọ ajagbe kan. Ni kete ti wọn ko si ẹnu ọkọ ajagbe naa tan ni Naira Marley ke gbajare si dẹrẹba ọkọ ajagba naa, to si n ke si pe ko rifaasi. hhhhhh Gẹgẹ bii ohun to wa ninu fidio naa, awọn mejeji to wa lori alupupu naa ko farapa, ẹmi ẹnikẹni ko si ba iṣẹlẹ naa lọ. Ikorodu cult crisis:A máa gbé Orò síta lọ́jọ́kọ́jọ́ tí ìjà ẹgbẹ́ òkùnkùn bá tún ṣẹlẹ̀- Àwọ Bo tilẹ jẹ pe ori ko awọn eeyan naa yọ, iṣeju aaya perete si iṣẹlẹ naa ni ẹlomiran tun n ki Naira mMarley ni mẹsan an mẹwa ki oun naa le ri owo gba lọwọ olorin ọhun. Lasiko to fi fido ọhun soju opo Instagram rẹ, Naira Marley sọ pe ""Diẹ lo ku ki arakunrin yẹn padanu ẹsẹ rẹ."" Ọpọ awọn to wo fidio naa lo ti bẹrẹ si n fi erongba wọn lede lori iṣẹlẹ ọhun. Bi awọn kan ṣe n kan sara si naira Marley fun aajo ololufẹ rẹ to ṣe, lawọn mii n sọ pe iṣẹ ati iya to wa lode le mu ki odidi gende fi ẹmi ara wewu nitori ₦500 pere. Akomolede ati Aṣa lori BBC Yoruba: Ẹ̀yà Ara Ifọ̀ ní olùkọ́ Adedokun kọ́ wa",0,yoruba agbègbè tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba "RT @user: Ọ̀pọ̀ ló fẹ́ láàpa láì lápá, bí èèyàn ò sì lápá, kò leè láàpa. / Many want to make a mark without effort, yet without…",0,yoruba Àìmọ́ ni ó ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọmọ lo ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba Ìyalẹnu ti wa ni iṣẹ́ aláwọ̀ lo je gbogbo ise ibile tèmi.,0,yoruba "Gẹgẹ bii ajọ NAFDAC ṣe sọ ninu awọn ẹya ara ẹja naa bii ẹdọ, ifun ati awọ ara rẹ ni awọn majele fara sinko si Ajọ to n gbogun ti ilokulo ounjẹ, ohun mimu ati ogun lorilẹede Naijiria, NAFDAC lo ṣe ikilọ yii ni ọjọ ẹti. Lati orilẹede Japan, China ati Korea ni ajọ NAFDAC ni ẹja yii ti n wa si orilẹede orilẹede Naijiria. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ikú Bademosi- Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí alásè Ganduje: Mi Ò gba rìbá lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni rí láyé mi Bi eeyan se ẹja yii tabi koo pamọ sinu ẹrọ amohuntutu, kaka ki majele ara rẹ parẹ, n ṣe ni yoo maa rin kaakiri agọ ara rẹ ""Ẹja yii ni majele kan ni ara rẹ eleyi to lee ṣakoba fun ẹnikẹni to ba jẹ ẹ. Aisan ni yoo ko ba ẹni bẹẹ eleyii ti o si lee ja si iku fun un."" Gẹgẹ bii ajọ NAFDAC ṣe sọ ninu awọn ẹya ara ẹja naa bii ẹdọ, ifun ati awọ ara rẹ ni awọn majele fara sinko si. Ko si ohun ti a lee ṣe lati fi yọ majele yii kuro lara ẹjọ yii-boya sise e tabi kikoo pamọ sinu ẹrọ amohun tutu ko ran an. Lati orilẹede Japan, China ati Korea ni ajọ NAFDAC ni ẹja yii ti n wa si orilẹede orilẹede Naijiria Gẹgẹ bi wọn ṣe sọ, bi eeyan se ẹja yii tabi koo pamọ sinu ẹrọ amohuntutu, kaka ki majele ara rẹ parẹ, n ṣe ni yoo maa rin kaakiri agọ ara rẹ. Nibayii, ajọ NAFDAC ti pariwo sita lori ẹja yii ati ọṣẹ ti o n ṣe lagọ ara ti wọn si ti kilọ f'awọn onile ounjẹ gbogbo ati oniṣowo ẹja lati maṣe ta ẹja yii fun ẹnikẹni nitori ọta ilera ni. NAFDAC: A ń se ìwádìí pínpín oògùn ikọ́ Coedine délẹ̀ NAFDAC ti ṣetan láti wádìí àwọn ilé iṣẹ́ apoògùn fínnífínní lórí ọ̀rọ̀ coedine Fídíò Coedine BBC ṣí ojú NAFDAC sí iṣẹ́ ìwádìí tó yé kí wọ́n ṣe Ní kété tí BBC ti gbé fídíò àwón ọ̀dọ́ ti wọ́n n mu òògùn ikọ́ olómi Coedine síta ní ó ti n so èso rere fún iṣẹ́ ìwádìí àti òfin ìlera túntún. Bayii, ìjóba Naijiria ti fi ofin de lilo Coedine ati Tramadol ninu òògùn ikọ́ pípò. Ile igbimo aṣofin agba ni Abuja naa ti sọ̀rọ̀ lori koko yii. Aya aare, Aisha Buhari atawon èèkàn kaakiri Naijiria ti bẹ̀rẹ̀ ifowosopọ̀ lori gbigbogun ti iwa ibaje yii. Lọ́wọ́lọ́wọ́, awon ile ise ijoba apapo ni Naijiria to n mojuto gbigbogunti àṣìlò ohun jijẹ ati oogun lilo, NAFDAC, ti kede pe wọn ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí nínú awọn ilé isẹ́ mẹ́rẹẹrin ti Fídíò BBC menuba. Ọ̀jọ̀gbọ́n Mojisola Adeyeye, to je oludari ajọ NAFDAC, ni ""A o gbé igbesé to ba yẹ ni kete ti a ba pari ìwádìí nínú awọn ile ise mereerin ti Fídíò BBC tú síta"". O ṣeleri pe ìyà tótọ́ nijoba yoo fi jẹ ile iṣẹ to ba lùgbàdì òfin ìlera. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àìsàn ibà; Àwọn ènìyàn sọ̀rọ̀ nípa lílo ewé áti egbò",0,yoruba "Gẹgẹ bi awọn agbabọọlu Naijiria ṣe ti n gbara di fun ifẹsẹwọnsẹ wọn pẹ̀lú ikọ agbabọọlu ti Cameroon, ọkan awọn ọmọ Naijiria naa ti wa loke. Ṣe ni ọpọlọpọ ti n gbiyanju lati Sọ àsọtẹ́lẹ̀ orílẹ̀èdè tí yóò borí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ t'òní Awọn ololufẹ ikọ super Eagles to n gbe orillẹ̀ede wọn larugẹ ni o yẹ ki awọn agbabọọlu gan ni imọ lara eyi ki wọn si lo gbogbo ọgbọn ati agbara ti wọn ba ni lati mu ori awọn ololufẹ wọn wu. Bi awọn kan ṣe n sọ idi ti wọn ko fi ro pe Naijiria yoo bori Cameroon bẹẹ ni awọn mii n ṣa n fẹ́ẹ̀ ki Naijiria bori.",0,yoruba "Àkóbì níjó òní nípa ayé ọ̀ṣun. Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.. Eyi ni adetokun ninu ilu.",0,yoruba AFCON 2019: Báwo ni ìdíje Super Eagles àkọ́kọ́ yóò ṣe lọ?,0,yoruba Ènìyan ti nilo ẹka fun àgbà tabi ibini.,0,yoruba Àwọn aláìì dé sí ìbàdandun láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó jẹ́ dára jù...,0,yoruba eyin orekelewa omoge ile kaaro ojire to mo faajie kan si arabinrin lati ra sokoto igbalode ti won pe ni pallazo,0,yoruba "James Omiyinka Olanrewaju gangan ni orukọ abisọ Baba Ijesha ṣugbọn ọpọlọpọ ni ko mọ ọ ju orukọ ori itage rẹ lọ. Baba Ijesha bẹrẹ ifọrọwanilẹnuwo rẹ pẹlu gbajugbaja ọrọ to maa n sọ ninu ere ""Oyinbo sọrọ o fi Psychology sinu rẹ..."" ""Ọmọ bibi ilu Ijẹfẹ ni mi tori wi pe Ile Ifẹ ni mama mi, Ijesha ni Baba mi. Awọn Yoruba ni a kii nilee baba ka ma nile iya ni mo ṣe da mejeji pọ si ilu Ijefẹ"". Èmi àti Sanyeri ti tọrọ oúnjẹ jẹ rí nílé oninawo torí ebi, ká tó di gbajumọ oṣere Ta ni Yusuf Satia ti iku mu lọ? Say no to rape: Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá pariwo síta lórí wàhálà ìfipábánilòpọ̀ Àwọn fíìmì òde òní ń kọ́mọ lólè àti ọ̀pọ̀ ìwà burúkú Niyi Akinmolayan tó ṣe fíìmu àwòrán-dèèyàn Cartoon nípa COVID-19 tó la ayé já ní N Ṣe abinibi ni ede Ijesha ninu fiimu ni tabi ""ability""? James ni igba mii ogun tabi ọta lo maa n ti eeyan de ọdọ oloore eeyan. O fi eyi ṣalaye bo ṣe bẹrẹ ere Tiata. O ni ere kolekole bii adigunjale loun fi bẹrẹ ere Tiata ṣugbọn lọjọ ti o yẹ ki oun kopa ninu ere Saheed Balogun kan to yẹ ki oun ti kopa gẹgẹ bii adigunjale ni ọkan lara awọn aṣaraloge ba ni awọn ti wọn koun tunraṣe fun ti pe. Ẹẹmẹẹdọgbọn lo yẹ ko fara han ṣugbọn ko pada ri anfani kankan lati sọ fawẹli A lasan ninu ere naa. Baba Ijeṣha ni Wọn pada ni ki oun kan duro soju kan lẹgbẹ Fathia Balogun to yẹ ko fọwọ leran lori itage, wọn ni ko ma sọ ọrọ kankan ko kan maa jo. Baba Ijesha ni: Ọlọrun wa kọ si mi nibi ti mo dede jokoo si mo ni (léde Ijesha) ""Anti mi... Fathia: Ki lo de? Baba Ijesha: Ọkan mi kan baa yin sọ̀rọ̀ nii Fathia: What for? Baba Ijesha: Nigba ti ọga mi ti dide lọ la toosti ọrẹ rin, ẹ jẹ ki emi naa ti mo jẹ mọnija ki mo mọ nipa owo gan ka jọ maa fi kii, ka maa fi lu pọ Fathia: Are you mad? Baba Ijesha: Afi ki e fọọlu o, bẹẹ ba i le fọọlu, iya laa jẹ yin... Oyinbo sọrọ o fi Saikọlọji sinu rẹ... Bi ede Ijesha ṣe sun James Omiyinka de bi ire to di gbajugbaja alawada oṣere Yoruba. Ohun tẹ́ẹ gbúdọ mọ nípa kókó orí ọyàn yín lásìkò fífọ́mọlọ́yàn Ṣé lóòtọ́ ni aya ààrẹ, Aisha Buhari fò lọ sí Dubai fún ìtọ́jú? A ó fún ẹbí akẹ́kọ̀ọ́ Fásitì Ibadan tó dolóògbé ní owóo gbà mábìnú - Ìjọba Oyo ""Mo bọ̀wọ̀ fún Fathia Balogun púpọ̀, ẹ̀dá ọ̀tọ̀ táwọn èèyàn ò fura sí ni"". O ni awọn kan wa laye to jẹ pe tẹẹ ba rọra fọwọ kan wọn lasan, aye ẹ maa dara gidi gan. Baba Ijesha mẹnu ba a pe Alagbe ni Yoruba oni Tiata ka ma fi nkankan bo o loju o si ṣalaye idi to fi sọ bẹẹ pe iṣẹ awọn jẹ iṣẹ igba tori naa ẹni to ba pe eeyan si ere naa ni eeyan le ba ṣere. O ni awọn ẹya kan wa to maa n dide iranwọ si ẹbun ẹni. Lọwọlọwọ, akẹkọọ ni James Omiyinka ni ipele aṣekagba ni fasiti ilu Eko nibi to ti n kọ imọ ẹkọ Tiata to si sọ ninu fidio ifọrọwanilẹnuwo wa pẹlu rẹ awọn nkan tuntun ti ẹ o maa reti latọdọ rẹ. Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀",0,yoruba "Wọ́n ti ṣe àlàyé ìjàmbá tí àwọn ọkọ̀ ojú irin náà ti fà fún ẹranko inú ìgbẹ́ tí ó wà ní agbègbè náà , àti dín àwọn ọmọ ènìyàn lọ́wọ́ láti fọ́n ká sí agbègbè .",0,yoruba "Ìròyìn fi yé wípé àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú tí ó wà lórí ipò ìyẹn Awami League ( AL ) gbé ẹ̀rọ tatapùpù wá sí ibẹ̀ , wọ́n sì da ilé náà wó .",0,yoruba ihoho la ka ra wa ni gba ti moimoi n shoge lol for yorubas only,0,yoruba "RT @user: #Lokoja-Abuja rd""""""""""""""""@user: Ẹkáàrọ̀ ní #Naija o! Ẹ kú súnkẹrẹ-fàkẹrẹ :) cc @user #Lagos #Ibadan #Kano #Onitsha""""""""""""""""",0,yoruba "Ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò yóò bẹ̀rẹ̀ láìpẹ́ yìí láti fún wọn lánfàní láti jẹ́rìí sí ohun tí wọn mọ Àwọn ìdílé tó pàdánù àwọn ènìyàn wọn níbi ilé alájà mẹ́rìlélógún ti Grenfell Tower tó jóná ní Keshinton, west London yóò rí ìdájọ́ fún àwọn ẹni wọn to pàdánu ẹ̀mí níbẹ̀. Òsẹ̀ méjì ní o yẹ kí ètò ìwádìí òhún lò tí ẹnìkọ̀ọ̀kan yóò sì sọ̀rọ̀ bó ṣe wùú láì fi gbèdéke síi ibi tí wọn le sọ̀rọ̀ mọ Ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò yóò bẹ̀rẹ̀ láìpẹ́ yìí láti fún wọn lánfàní láti jẹ́rìí sí ohun tí wọn mọ Ọ̀pọ̀ àwọn tí yóò kópa ní wọn nírètí pé yóò ka ọ̀rọ̀ tàbí sàfihàn fọ́rán-án àwọn olólùfẹ́ wọn tó ti kú. Òsẹ̀ méjì ní o yẹ kí ètò ìwádìí òhún lò tí ẹnìkọ̀ọ̀kan yóò sì sọ̀rọ̀ bó ṣe wùú láì fi gbèdéke síi ibi tí wọn le sọ̀rọ̀ mọ Ìwádìí ọ̀hún yóò sàyẹ̀wò sí ikú ènìyàn méjìléláàdọ́rin, tó fi mọ́ ọ́kan lára wọn tó wà ní ilé ìwòsàn láti inú oṣù kẹfà ọdún 2017, to ṣẹ̀ṣẹ̀ saláìsí nínú oṣu kíní ọdún yìí. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọlọ́pàá mú èèyan mẹ́ta pé wọ́n so akẹ́kọ̀ọ́ mọ́gi NDLEA gbéṣèlé tọ́ọ̀nù mẹ́rìn oogun Tramadol Ọmọọba Harry ati Meghan Markle ti di tọkọtaya Àjọ ọlọ́pàá: kọ́kọ́ sàyẹ̀wò ọlọ́pàá kó tó yẹ̀ ọ́ wò Ọ̀pọ̀ àwọn tí yóò kópa ní wọn nírètí pé yóò ka ọ̀rọ̀ tàbí sàfihàn fọ́rán-án àwọn olólùfẹ́ wọn tó ti kú. Orúkọ gbogbo àwọn tó ti saláìsí ní wọn ò kà síta nibi ìgbẹ́jọ́ tí yóò wáyé ní ilé ìgbáfẹ́ Millennium Gloucester, ní Gúúsù Kensington, west London, sùgbọ́n kìí ṣe gbogbo ebí ní yóò lánfàní láti sọ̀rọ̀ níbẹ̀ Sir Martin Moore-Bick tó jẹ́ adájọ́ fẹ̀yìntí ni yóò jẹ́ alága ìwádìí, tí yóò sì máa gba ẹ̀rí láti ọ̀dọ̀ àwọn ọlọ́dani, àwọn ilé-iṣẹ́ àti àwọn akọ́ṣẹ́mọṣẹ́.",0,yoruba "Ọpọ eeyan kaakiri agbaye lo ti n woye ibi ti esi idibo naa yoo fori sọ. Ṣe Aarẹ Donald Trump ni yoo tun wọle fun saa keji ni tabi Joe Biden ni yoo yẹ aga mọ nidii? Fun ẹnikẹni to ba wọle ninu Trump tabi Biden, iru akọle iroyin to lee jade ree: 1.Irọrun ni Joe Biden fi yẹ aga mọ Trump nidii Ohun akọkọ to lee ṣẹlẹ ni ki Joe Biden jaweolubori pẹlu irọrun. Lati igba ti ipolongo ibo ọhun ti bẹrẹ ni Joe Bide ti n tiraka lati bori ninu idibo naa. Bi Biden ṣe n lakaka naa ni Aarẹ Donald Trump naa ṣe n gbiyanju lati wọle fun saa keji. Gẹgẹ bi awọn kan ṣe sọ, lara akitiyan Biden lati wọle ni bo ṣe yan obinrin to jẹ alawọm dudu gẹge bi igabkeji rẹ, iyẹn Kamala Harris. 2.Trump jaweolubori lọna to ya awọn eeyan lẹnu Ohun keji to lee ṣẹlẹ ni ki Donald Trump bori lọna ti yoo ya awọn eeyan kan lẹnu. Lara ohun to lee sọ bi aṣeyọri Trump yoo ṣe ri ni awọn esi ti yoo wa lati Pennsylvania ati Florida. Iwadii kan fi han pe ogunlọgọ awọn oloufẹ Trump lo n gbe ni awọn ilu nla kan bii Florida, Ohio, Tennessee, Pennsylvania, North Carolina, Georgia ati Virginia. Iroyin ni awọn eeyan naa fẹran Trump to bẹ ti o fẹẹ jọ bi pe wọn lee fi ẹmi wọn lelẹ fun ọkunrin ọhun. Idi miran ti awọn onwoye tun fi sọ pe o ṣeṣe ki Trumnp bori lọna ti yoo jọ awọn eeyan kan loju ni igbagbọ pe o mọ bi wọn ṣe n polongo ibo ju Biden lọ. 3.Biden gbo ewuro soju Trump Ohun kẹta ti awọn onimọ nipa eto oṣelu Amẹrika tun sọ ni pe o ṣeṣe ki Biden bori Trump ni ọna ara ti awọn eeyan ko lero. Eyii to n tumọ si pe, kii ṣe pe Biden bori Trump nikan, ṣugbọn o gbo ewuro soju Trump lọna ti awọn eeyan ko lero. Ni nnkan bi ọjọ diẹ si idibo naa ni arun Covid-19 lekenka si l'Amẹrika, eyii to mu Biden sọ ninu ọkan lara ipolongo rẹ pe Trump ti kuna nipa eto ilera ilẹ Amẹrika. Yatọ si eyii, lara awọ nnkan ti awọn eeyan korira nipà Trump ni bo ṣe sọ pe oun fẹ kọ odi, eyii ti yoo dena mọ awọn to n wọle sorilẹ-ede naa lọna aitọ. Bẹẹ lo tun sọrọ alufaṣa si awọn Musulumi, to si pe awọn awọn kan lara wọn ni alakakiti ẹsin.",0,yoruba "Ọsẹ ayelujara ni ipinlẹ Eko n waye laarin ọjọ kẹtalelogun oṣu keji o si ti ni ọpọlọpọ eto alakalẹ ti wọn ni fun un yin lati lee mu aye ode oni tii ṣe ti awọn ọdọ dara sii. Lọdun yii ninu eto naa, abala meji ni ileeṣẹ BBC yoo dari eyi ti wọn pe ni ""Gbigbe ohun obinrin s'oke"" eyi ti yoo waye lọjọ ẹti ọj kejidinlọgbọn. Akori abala keji ti waye lọjọ aje ọjọ kẹtalelogun oṣu keji. Abala to ni ṣe pẹlu obinrin yii yoo da lori akanṣe iṣẹ kan ti ileeṣẹ BBc pe ni 50/50 eyi to n gba ọpọ obinrin niyanju lati maa kopa ninu awọn eto jakejado BBC. Awọn olujiroro yoo fọrọwerọ lori oriṣiriṣi ọna ti ṣiṣe iroyin lee jẹ ki obinrin atawọn ọdọ pọ si i lati fun wọn ni ohun to ja oke lori awọn iroyin to wu wọn lati ka ati lati pin. Awọn oṣiṣẹ BBC to wa lara awọn olujiroro yoo ṣafihan bi wọn ṣe ti mu eleyii wa si imuṣẹ kaakiri ilẹ Afirika lori ẹrọ mohunmaworan wọn, ẹr rẹdio ati lori awọn itakun ayelujara. Mi ò kí ń ṣèèyàn burúkú tàbí Babalawo bí ẹ ṣe mọ̀ mí nínú eré - Fadeyi Oloro Abala ti BBC yoo ti sọrọ yoo yananan bi ẹ ṣe le fi obinrin sinu iroyin yin ati ọna ati bọ sori ayelujara ggẹ bi o ṣe ti n gbilẹ kan lasiko yii. Itakun ayelujara ti di ohun kan ti ọpọlọpọ n lo koda ti awọn kan ti sọ ọ di iṣẹ ti wọn n ṣẹ Ọsẹ itakun ayelujara (Social Media Week) ti di ọkan lara ipade apero nla eyi ti orilẹede mejila kaakiri agbaye maa n ṣe.",0,yoruba "Ará Èkó ò mọyì ará oko """""""" - the Lagos folks; urban no not the value of the farm dwellers; rural ► http://t.co/JzIV9Obs5L #Blogs",0,yoruba "Ògoò rẹ yóò ju tẹnikẹ́ni ń'nú ẹbíì rẹ lọ. ~~~ O ò ṣ'àmín àṣẹ, kí o sì gbé'tọ́ àmín mì",0,yoruba Ìlẹ̀ Ọ̀yọ́ jẹ́ ilẹ̀ agbègbè tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà.,0,yoruba "@user @user E kaaro eyin ara. Oni je ojo eti, mo dupe fun Oluwa. T'omo ba sise, o ye ko simi, ki o si se faaji. #TweetInYoruba",0,yoruba "#AfricanPraise 🎵🎶🎵 Halleluyah [4x] Halleluyah, ogo ni fun (Halleluyah! Glory to) ‘go ni fun (Glory to) ‘go ni fun baba (Glory be to God) 🎵🎶🎵 #Yoruba #ThanksgivingService #NoLimits #RccgWca https://t.co/ClrywE4XCK",0,yoruba oluwa oshe to jen ri ojo eni module lowo re olorun make she iyanu ninu aye like,0,yoruba "nípa àìkú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba àsa. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà.,0,yoruba ìjẹ̀bú communities lagos mọ́lájoyè kétu odò ẹ̀gírí ìrayè òdómọ́lá imòkùn odò gbọ́nlé odò ṣíwọnlóyè tẹ̀mù ìrágùṣì igbó ńlá ìjì jégbéndé ògùn ìjẹ̀bú igbó ìjẹ̀bú òde imodi ìjàsí odò lẹ́mọ odò rẹ́mọ ìmàkà odògbólú atan ìláàdó mámu,0,yoruba Ọba mú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó wáyé..,0,yoruba RT @user: Ẹ kú ojúmọ́ o. Ẹ sì kú àlàjá ọ̀sẹ̀. #Ekaaaro #OlorunSeun,0,yoruba ni a ní láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó jáde nìlẹ̀̀ní sáàrí ti nípa ìtànká àti ire ènìyàn.,0,yoruba ọlọ́run rẹ́rìnín múṣẹ́ ó hàn gbangba pé ara obìnrin ló bá irú iṣẹ́ náà mu,0,yoruba ẹkọ́ ṣẹlẹ ni Ibadan ti gbogbo eniyan sọ o ṣe pataki. (2012),0,yoruba ẹkọ́ ṣẹlẹ ni Ibadan ti gbogbo eniyan sọ o ṣe pataki. (2024),0,yoruba "Emiliano Sala n pada si Cardiff lọjọ Aje lẹyin to buwọlu iwe adehun iṣẹ tuntun, lo kagbako iṣẹlẹ naa Ọmọ orilẹede Argentina ọhun, to jẹ ẹni ọdun mejidinlọgbọn, ati awakọ ofurufu kan lo jọ wa ninu ọkọ baalu naa to deede poora ni erekusu Channel lalẹ ọjọ Aje. Ọga agba fun ṣiṣe awari loju ofurufu ni Erekusu Channel, John Fitzgerald, sọ pe ''ẹni ti ara a rẹ pe julọ'' ko le lo ju wakati diẹ lọ ninu omi. Murphy Elégungun Rọba: Mo fẹ́ di ẹnití egungun rẹ rọ jùlọ ní àgbáyé Awọn adoola ẹmi tun ti pada bẹrẹ si ni wa ọkọ oju ofurufu naa to poora ati awọn to wa ninu rẹ, lọjọru. Iroyin kan sọ pe Sala fi atẹjiṣẹ ranṣẹ si awọn mọlẹbi rẹ lori ẹrọ ayeluja Whatsapp, pe ''ẹru ba oun pupọ.'' Awọn ileeṣẹ iroyin l'orilẹede Argentina jabọ iroyin pe Sala sọ fun mọlẹbi rẹ pe ''Mo wa ninu ọkọ ofurufu kan to dabi ẹni pe o fẹ ẹ jabọ.'' Awọn eniyan ti gbe òdòdó àti ọrọ iwunilori silẹ ni ita paapa iṣere Cardiff Ni nkan bi aago mọkanla aabọ owurọ l'Ọjọru, ileeṣẹ ọlọpaa ni Guernsey sọ pe ọkọ ofurufu mẹta ati baalu kekere kan wa loju ofurufu, bi wọn ṣe n wa baalu Piper Malibu. Bakan naa ni awọn ọlọpaa sọ pe 'awọn ti n ṣayẹwo akọsilẹ ẹrọ ibaraẹnisọrọ lati mọ boya iranlọwọ kankan le ti ibẹ jade. Ṣugbọn titi di asiko yii, ko ti i si iroyin kankan nipa baalu to poora naa. Olu ilu orilẹede Welsh ni Sala n lọ lẹyin to buwọlu iwe adehun iṣẹ miliọnu mẹẹdogun Pọun pẹlu ikọ Bluebirds.",0,yoruba "Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu ọkunrin kan, Abass Abiodun Owonikoko, tii se onisowo ounjẹ lọja Bodija nilu Ibadan. Awọn isẹlẹ Kayeefi miran ti ẹ le nifẹ si: Ija ni Owonikoko atawọn ọrẹ rẹ mẹrin miran lọ ja lẹyin eegun lọdun 1993, ti wọn si pa eeyan meji. Eyi lo ba de ọgba ẹwọn, ti wọn fi dajọ iku fun, sugbọn ti gomina Ibikunle Amosun ba yi pada , to si gba idande lẹyin ọdun mẹtadinlọgbọn. Inu ọgba yii lo wa to fi di imaamu, o keu, to si gba alukurani. Àwọn ìtàn Mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹnu onikan la ti n gbọ kanun, ẹ gbọ ọrọ latẹnu ọkunrin yii funra yin.",0,yoruba "Igboho, lasiko to n kopa lori eto kan lori ayelujara ti agba akọroyin, Dele Momodu se agbatẹru rẹ, lo ti salaye nipa ohun to da oun ati Tinubu pọ. Igboho ni lootọ ni oun lọ sepade pọ pẹlu Tinubu nile rẹ to wa ni Bourdillion nilu Eko nitori Sẹnetọ Rashidi Adewolu Ladoja to jẹ baba fun oun lo pasẹ pe ki oun lọ. Ajijagbara fun ilẹ Yoruba naa ni lasiko ti eto idibo gomina fẹ waye nipinlẹ Ondo, ti Olusegun Mimiko ti kopa ninu rẹ, ni isẹlẹ naa waye. O salaye pe lasiko ipade naa ni Tinubu sọ fun mi pe n ko gbọdọ se atilẹyin fun ẹgbẹ oselu PDP lasiko eto idibo naa nitori iwa aidaa ti wọn hu si Ladoja, to jẹ baba fun oun. Igboho ni ""N kò gbà owó lọwọ Tinubu rí àmọ́ o fún mi ní miliọnu meji naira lasiko abẹwo mi naa,pe kí n fi ra epo sì moto. Iya ti PDP fi jẹ ladoja ní ko jẹ ki n sisẹ fun PDP, mo sì ṣe ohun tí Tinubu fe ki n se lasiko naa."" Agbara to daju wa lọwọ iran Yoruba: Igboho, lasiko to n salaye iru agbara to ni sọ pe lootọ ni agbara wa nilẹ Yoruba, amọ awọn alaisootọ kan lo n mu ebu ẹyin ba a. ""Yoruba ni oogun lọwọ. Onirọ tí pọ ni kò jẹ ka naani nnkan ta ni. Ologun kii se ìkà báwọn Musulumi ati Kristiẹni tí lérò rẹ. Ọlọ́run dá èwe àti egbò, Ọlọrun lo máa ń fún èèyàn, tí èèyàn kò bá ti sí lo."" Ladoja ni baba mi, ko dalẹ mi ri: Nigba to n salaye iru ajọsepọ to ni pẹlu Rashidi Ladoja, Igboho ni baba oun lo jẹ, tori ọdọ rẹ ni oun de si lẹyin ti ogun Modakeke ati Ife pari, ninu eyi ti oun ti kopa. ""Lootọ ni n kii ba oloselu se amọ mo ba awọn mẹta kan se pupọ. Ladoja, bàbà dáadáa ni, mo fẹran wọn, kìí yẹ àdéhùn. A jọ dúró tì ara wa. Mo tẹ́lẹ̀ Lam Adesina fún ọdún kan, àti Ladoja. Mo tún bá Oyinlola ṣe ni Osun."" Seyi Makinde lo si ile mi to jona: Nigba to n dahun ibeere lori ibasepọ rẹ pẹlu gomina ipinlẹ Oyo, Enginia Seyi Makinde ati idi ti aarin wọn ko fi gun, Igboho ni eyi ko ri bẹẹ rara. ""Èmi àti Makinde, ibasepọ wá dán moran. Ladoja ni mo n tẹle. Ibi tí kò ba lọ, n kii lọ. Makinde lo ba mi sí ilé mi tó jọna. Ó tún fún mi ní ẹrọ amunawa alagbara 500KVA lati gbe mi larugẹ ni adugbo ti mo n gbe, bẹẹ ni Ladoja lo pasẹ fun wa pe ka dibo fún Seyi Makinde, ta si sisẹ fún wọn lọjọ idibo. Èmi kii se gìrì mọ oloselu miran lẹyin Ladoja. Ń ko dalẹ rẹ rí, ohun ti ko bá lọwọ sì, èmi kii se. Ọpọ lo fi owó lọ mi àmọ́ mo kò ọ, n ko le kúrò lẹyin Ladoja bo tilẹ jẹ pe a ko se oselu mọ."" Ko si ija laarin emi ati Gani Adams: Oloye Sunday Igboho tun mẹnuba bi aarin oun ati Aarẹ Ọna Kakanfo tilẹ Yoruba, Iba Gani Adams ti ri lasiko yii. O ni kò sí nkankan bíi ìjà laarin oun àti Gani Adams, awọn si jọ ń ṣiṣẹ ohun tó ń ṣẹlẹ̀ yìí ni. O fikun pe Gani Adams gan ti ke sita lori bawọn ọdaran kan laarin awọn Fulani se n huwa ika nilẹ Yoruba, eyi ti ko ba oun naa lara mu rara. ""Òun náà tí sọrọ tako ìwà àwọn darandaran yìí, a si dijọ n sisẹ pọ ni, ko si ija rara laarin wa."" N ko mọ Nnamdi Kanu ri, a ko sọrọ ri: Lori ajọsepọ rẹ pẹlu ajijagbara fun ilẹ Igbo, Nnamdi Kanu, Sunday Igboho salaye pe oun kò mọ Nnamdi Kanu rí rara, bẹẹ ni ko si ajọsepọ kankan laarin awọn. ""Mo kọ ila soju, ọmọ Yoruba ni mi, mo maa n dọbalẹ ki awọn iya ati baba mi ni, èdè àti àṣà emi ati Kanu kò papọ rara. Koda, ako sọrọ si ara wa ri, kò sì sí ajọseps kankan pẹlu emi ati Kanu rara. Lakota, Igboho tun leri leka pe oun si duro lori ipinnu oun pe awọn ọdaran Fulani gbọdọ fi ilẹ Yoiruba silẹ ni, ki alaafia le jọba, ki oun to sinmi.",0,yoruba ọ̀gbọ́n. Bàbá lo ni ẹ̀ká àwẹ eyti o gbe lori iwa rere.,0,yoruba Telegram naa ní ègé olóótọ fún àwọn ìkòkò tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba lòdì Ìbàdàn. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba Àkóbì níjó òní nípa àwẹ ọba. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé.. Eyi ni adetokun ninu ilu.,0,yoruba "Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Osun, Yemisi Opalola to fi idi ọrọ naa mulẹ ni awọn ọdọ to le ni ogun lo yabọ ileẹ̀kọ́ naa pẹlu ada ati ọkọ ti wọn si da rogbodiyan silẹ. Ọpalọla ni ipe pajawiri ni wọn pe oun, ni ileẹ̀kọ́ naa ti awọn si ko awọn ọlọpaa lọ si ileewe naa. Opalola ni: ''A fi panpẹ mu afurasi kan pẹlu ada lọwọ, ati eleyii ti wọn ti sa ni ada ni apa ati ori.'' ''Iwadii ṣi n lọ lọwọ, amọ o ṣeeṣe ki awọn janduku naa jẹ awọn ọmọ ẹlẹgbẹ okunkun.'' Femi Falana, Endsars: Awolowo kò fáààyè gba kí èèyàn máa yàgò fún Màálù nígboro ''Bakan naa ni a ti gbe awọn ti wọn farapa ninu iṣẹlẹ naa lọ si ileewosan ijọba ti Osogbo Central Hospital fun iwosan to peye. Amọ, Adari ẹka ileeṣẹ eto ẹkọ nipinlẹ naa, Kehinde Olaniyan sọ wi pe awọn gbe igbesẹ lati ti ileewe naa pa, ki rogbodiyan ma bẹ silẹ nibẹ. Oladele Ogbeyemi Albert: Irin tí mò ń lò máa ń bá mi sọ̀rọ̀ nínú ẹ̀mí kí ń tó gbẹ́ wọn sóh O ni awọn janduku ati awọn ẹlẹgbẹ okunkun ti wọn n ṣe bi akẹkọọ lo yabọ ileewe naa. ''A fẹ kesi awọn obi ati ojulumọ lati sọ fun wọn pe Kọmisọnna fun eto ẹkọ ti paṣẹ ki wọn ti ileewe Ifeoluwa Grammar School fun igba kan naa.;; Lori iro: Ká ni àwọn Òbí mi gbà fún mí, èmi àti Sunny Ade á jọ máa 'Compete- Baba Lórí ir ''Eyi ni lati ri wi pe omi alaafia ilu ko daru nitori awọn oni jagidijagan yii ti wọn n pe ara wọn ni akẹkọọ'' ''Nitori naa ni a fi kesi awọn obi lati jẹ ki awọn ọmọ wọn duro silẹ, titi iwadii yoo fi pari.'' Bakan naa ni ijọba ipinlẹ Osun fikun wi pe awọn ti n tpasẹ awọn janduku naa, ti awọn yoo si fi wọn jofin laipẹ.",0,yoruba àkerekere. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò.,0,yoruba "Ọmọ fè lọ, Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Njẹ o mọ? Njẹ o mọpe kò lẹtọ fún ọlọpa ọkunrin lati wa ẹru tabi ara obinrin? O lẹtọ ki ọlọpa ọkunrin yẹ ọkunrin wo, ki ọlọpa obirin si yẹ obirin wo, lai si iwa palapala kankan. #Yoruba #EndPoliceBrutalityinNigera #EndSARS #EndSWATNow https://t.co/Gw21o3sBzY",0,yoruba ojo ayo ojo itura ni o n ro bayii nise ni o dabi eni wipe ki n pada loo sun,0,yoruba ọ̀rọ̀ àfetíyá ní èdè yorùbá borrowed words via sound university yunifásítì motor mọ́tò ball bọ́ọ̀lù radio rédíò fan fáànù sharia sèréyà apple ápù number nọ́ḿbà umbrella ọ̀m̀búrẹ́là cement símẹ́ǹtì,0,yoruba Ọjọ omi àgbayé lòní o. Omi o ni gbé wá lọ o. #ekaaaro #WorldWaterDay http://t.co/Cls9ZuGEub,0,yoruba fífi òfin de tako abala orí kejì àti abala orí kẹta ìwé òfin nàìjíríà ọdún,0,yoruba àwọn ìkòkò tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba Ọ̀bún ríkú ọkọ dìrọ̀ mọ́n. #EsinOro #Yoruba @user #June12,0,yoruba ẹkáàárọ̀ o ẹ sì kú afẹ́rẹ́ òní ò ní jọ àná èmi wíi alèwílèṣe á ṣe bẹ́ẹ̀ a á ṣẹ bẹ́ẹ̀,0,yoruba "Agba ti ko kehun soro, o daju wipe yoo ketan sare #YorubaProverbs",0,yoruba Olohun maa fi ikan gbakan lowomi🙏 #Yoruba https://t.co/JexSkvt7Pn,0,yoruba "Ko ti daju ẹni ti yoo jamọ lọwọ laarin Lawal ati Ndume Idi ree ti awọn eeyan Naijiria ṣe n foju sọna lati mọ ẹni ti yoo di ipo aarẹ ile aṣofin agba mu labẹ saa kẹsan ile aṣofin Naijiria. Lọjọ kọkanla oṣu Kaarun ni awọn ọmọ ile aṣofin agba yoo dibo yan ẹni ti yoo jẹ olori wọn. Tani yoo jẹ aarẹ laarin awọn to n du ipo yi ni ibeere nla ti awọn eeyan n reti idahun si. Awọn to n du ipo naa Odu lawọn mejeeji ti wọn du ipo aarẹ lẹyin ti Bukola Saraki pari saa rẹ. Ifidirẹmi ninu idibo gbogbogbo to kọja lo sokunfa bi Bukola Saraki ko ṣe pada wa si ile aṣofin agba bo tilẹ jẹ pe yoo fẹ ṣoro diẹ fun un lati di ipo naa mu. Awọn meji to lewaju lati di ipo yii mu ni Sẹnẹtọ Ahmad Ibrahim Lawan to n ṣoju ẹkun ariwa ipinlẹ Yobe. Ali Ndume Akẹgbẹ rẹ ni Sẹnẹtọ Mohammed Ali Ndume lati ipinlẹ Borno to n soju ẹkun guusu Borno. Lati ọdun 2011 lo ti wa ni ile gẹgẹ bi Sẹnẹtọ labẹ asia ẹgbẹ PDP. Ṣugbọn nigba ti awọn kan kora jọ lati gba ijọba lọwọ ẹgbẹ PDP, o darapọ mọ wọn ti o si jẹ olori ọmọ ile to pọ ju lọ labẹ asia APC. Adebo bórí l'Oyo, Oluomo ní ìpínlẹ̀ Ogun gẹ́gẹ́ bí adarí ilé aṣòfin Ó dára kí ìjọba ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ní àjọ tó ń gbógun ti ìwà ìbàjẹ́! Òfin má wàásù láì gbàṣẹ nìpínlẹ̀ Kaduna ti ń gba àpérò Iba Gani Adams: Bẹ́ẹ gbé màláíkà kan lọ sí Aso Rock, kò lè ṣàṣeyọrí Kini awọn mejeeji n gbero lati ṣe ti wọn ba de ori aleefa? Sẹnẹtọ Ndume ni adisọkan oun ni bi ile aṣofin yoo ṣe ni ominira tirẹ ti ko si ni si wi pe eeyan kan yoo ma dunkoko mọ awọn aṣofin nidi iṣẹ wọn. O ni oun yoo rii pe atunto ba ipo aarẹ ile asofin agba ti oun yoo si ṣapa lati koju iwa jẹgudujẹra. Ko fẹrẹẹ si iyatọ pupọ ninu nnkan ti Sẹnẹtọ Lawan naa fẹ ṣe ti o ba di aarẹ ile asofin agba. Ahmad Lawan Ohun naa ko fẹ ki awuyewuye pupọ wa laarin ẹka aṣofin ati ti alaṣẹ ijọba. Lawan kii ṣe aimọ lagbo oṣelu ti ọpọ awọn Sẹnẹtọ si ti lawọn yoo gbaruku ti lati di aarẹ ile asofin. Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun Bawo ni idibo naa yoo ti ṣe lọ? Ati aarẹ ile asofin ati igbakeji rẹ ni wọn yoo yan lọjọ iṣẹgun. Gbogbo awọn asofin mọ́kàndínláàdọ́fà ni yoo dibo yan ẹni tọkan wọn fẹ. Labẹ ofin idibo ile,idibo bonkẹlẹ alafihan(open secret ballot) ni iwe ofin la kalẹ. Ko ti daju boya wọn yoo fi ibo tẹnikọọkan ba di han ṣugbọn eyi keyi to ba jẹ,bi oludije kan ba ti le ni ibo to pọju tẹni keji rẹ, oun ni yoo di aarẹ. Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú Ṣe aṣẹ ẹgbẹ APC yoo ṣẹ lọtẹ yi? Awọn onwoye ni idanwo ni idibo aarẹ ile asofin yi yoo jẹ lati mọ boya awọn ọmọ ẹgbẹ APC yoo tẹle aṣẹ ẹgbẹ. Aṣẹ ti a n sọ yi ni eleyi ti o wa lati ọdọ awọn adari ẹgbẹ to fi mọ aarẹ Buhari pe ki awọn ọmọ gbẹ dibo fun sẹnẹtọ Lawan ati Omo Agege gẹgẹ bi aarẹ ati igbakeji aarẹ. Sẹnẹtọ Bukola Saraki ati Ike Ekweremadu ni won di ipo aarẹ ati igbakeji aarẹ ile asofin mu ni saa to kọja Bi a ko ba gbagbe, lasiko ti idibo ile asofin agba waye ni saa to kọja ẹnu ẹgbẹ ko ṣebi ẹni papọ soju kan eleyi to mu ki Sẹnẹtọ Bukola Saraki ati Sẹnẹtọ Ike Ekweremadu gbegba oroke. Ninu iwoye tirẹ, amofin kan to fi ilu Ibadan ṣe ibujoko, Saliu Adebayo, ni APC ti kọgbọn latara ohun to ṣẹlẹ ni saa to kọja. ''Gbogbo wahala ti aarẹ koju pẹlu ile aṣofin ni saa to kọja ko ṣẹyin pe ẹnu ẹgbẹ ko ko. O da mi loju pe wọn ko ni fi ina sori orule sun lọtẹ yi'' Amofin Adebayo tẹsiwaju pe esi abajade ibo yi yoo tubọ fi rinlẹ boya APC ṣetan lati di agbara mu ni gbogbo ẹka ijọba lalai fi ọkan jafara. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:",0,yoruba "Awọn oṣiṣẹ kan kan daṣẹ silẹ, bẹẹ lawọn mii ti lugbadi arun naa iha ila-oorun Cape Town, ko da, awọn nọọsi kan funra wọn lo n gbalẹ, awọn to n ṣiṣẹ abẹ lo n fọ aṣọ ti wọn n wọ, bẹẹ la tun gbọ iroyin pe ọpọ awọn alaboyun kun ẹka ti wọn ti n bimọ ti ko si si ẹni ti yoo da si wọn. Bi awọn dokita ṣe n tiraka lati lo awọn irinṣẹ ti ko to lati gba ẹmi awọn eeyan la lọwọ iku, wọn ti bu ẹnu atẹ lu ijọba fun iṣẹ ajanbaku to ṣe si ẹka eto ilera ilẹ ọhun. Aarẹ ilẹ naa, Cyril Ramaphosa ti wa kede pe ọrọ arun Covid-19 kii ṣe ohun ti ijọba ilẹ naa lee fi ọwọ yẹpẹrẹ mu, o si ti pe e ni iji lile. Ọkan lara awọn dokita to n ṣiṣẹ ni Port Elizabeth, John Black sọ pe ṣaaju arun Covid-19 ni awọn oṣiṣẹ wọn ko ti to n kan, arun naa si tun mu ki nnkan buru sii. O ni ""Ootọ ni pe a ko ni awọn oṣiṣẹ to to niye tẹlẹ, ṣugbọn lẹyin ti Coronavirus bẹrẹ, awọn oṣisẹ wa tun din sii pẹlu ida ọgbọn. Dokita Black tẹsiwaju pe ""Gbogbo nnkan ti bẹrẹ si n dojuru,"" lẹyin naa lo fidi rẹ mulẹ fun BBC pe awọn alaisan ma n ja si ẹrọ to n ran eemi lọwọ nile iwosan Livingstone to wa ni Port Elizabeth. Black yii nikan lo ba BBC sọrọ, bo tilẹ jẹ pe wọn dokita ati nọọsi miran ba BBC sọrọ, ṣugbọn wọn ni ki a ma fi orukọ wọn lede nitori ibẹru pe iṣẹ lee bọ lọwọ wọn. Ile iwosan di ile ekute Awọn dokita ati nọọsi to n ṣiṣẹ nile iwosan Port Elizbeth sọ pe ile iwosan naa dabi eyi to wa loju ogun ni, nitori ẹjẹ ma n wa nilẹ kaakiri, bẹẹ lawọn eku maa n sare kiri nile iwosan naa. Akọroyin ileeṣẹ BBC to yọju si ile iwosan ọhun ri awọn eku to n jẹun kiri nibi ti wọn da idọti si. Ọkan lara awọn dokita ọhun to fi iwe ranṣẹ si BBC ni iṣẹ abẹ to ba ṣe koko julọ ni wọn ma n dojukọ nitori pe awọn oṣiṣẹ ko to. Nọọsi mii tun sọ pe pẹlu ibẹrubojo ni oun fi n lọ si ibi iṣẹ lojojumọ. Iya ati ọmọ n ku Ibanujẹ ti dori awọn dokita kan kodo lẹyin ti wọn ri bi awọn obinirin ati ọmọ wọn ṣe dagbere faye laipẹ yii latari bi wọn ko ṣe ri oṣiṣẹ ti yoo ṣetọju wọn nitori pe awọn alaisan pọ ju olutọju lọ nile iwosan Dora Nginza ni Port Elizbeth. Wọn ni awọn iku ọhun ki ba mati waye, ṣugbọn ko si awọn ti yoo ṣetọju awọn ọhun ni, fun apẹrẹ, alaboyun to nilo iṣẹ abẹ. Ọkan lara wọn tilẹ sọ pe arun Covid-19 to de lo fun wọn ni anfani lati lee sọ ohun ti oju wọn n ri lẹnu iṣẹ ọhun. Pẹlu bi gbogbo nnkan wọnyi ṣe n ṣẹlẹ, awọn nọọsi ati dokita naa tun n gunle iyanṣẹlodi. 'A ko lee fi ẹmi awọn nọọsi wewu' Awọn aṣoju ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ ti sọ pe ko si ohun to buru ti wọn ba daṣẹ silẹ. Akọwe agbegbe fun ẹgbẹ awọn nọọsi nilẹ naa, Khaya Sodidi, sọ pe ""A ko le fi ẹmi awọn nọọsi sinu ewu nitori awọn oṣiṣẹ to n gbalẹ nile iwosan ti daṣẹ silẹ."" ""Awọn nọọsi funra wọn lo n gbalẹ bayii, eeyan lawọn naa, a ko si lee fi ẹmi wọn wewu."" Ẹwẹ, nigba to n sọrọ lori awọn ohun ti oṣiṣẹ eto ilera sọ, akọwe agba ileeṣẹ to n ri si eto ilera ni iha ila-oorun Cape Town, Thobile Mbengashe sọ pe ootọ ni. O ni ọpọ ninu awọn dokita ati nọọsi naa ni ẹru n ba lati ṣe ojuṣe wọn lẹnu iṣẹ. Ṣugbọn o fi kun pe awọn ile iwosan to wa labẹ rẹ n ṣe ojuṣe wọn.",0,yoruba "tí Ọba fè lọ, Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..",0,yoruba "Ẹmi ọpọ ọmọ Naijiria lo ti bọ nitori ikọlu Boko Haram, awọn ajinigbe ati ajijagbara Afunrasi naa lo n ta ibọn fun awọn ikọ agbebọn kaakiri Naijiria. Wọn fi ẹsun kan afunrasi naa wi pe o n ta ibọn atawọn ohun ija oloro gbogbo fun awọn ikọ agbebọn gbogbo kaakiri orilẹede Naijiria. Oniruru awọn eeyan ni wọn ti di ero ọrun lati ipasẹ awọn wahala ati rogbodiyan kaakiri orilẹede Naijiria. Eyi seese ko jẹ ọna abayọ kan gboogi, lọna ati se awari bi awọn ohun ija se n de ọwọ awọn ikọ agbebọn ati alakatakiti gbogbo lorilẹede Naijiria. Awọn osisẹ ọtẹlẹmuyẹ ni afurasi naa, Jonah Abbey lo n ko ohun ija oloro fun awọn ẹgbẹ agbebọn kaakiri Naijiria, paapaa julọ lẹkun Niger Delta, ila oorun gusu ati awọn agbegbe kan lẹkun aringbungbun orilẹede Naijiria. Lẹyin ọdun mẹwa, ọwọ awọn agbofinro tẹ afunrasi ọdaran to n ta ibọn fawọn agbebọn Laipẹ yii lawọn osisẹ ọtẹlẹmuyẹ tọpinpin awọn ohun ija oloro kan lati ilu Konduga nipinlẹ Borno, nibi ti awọn agbebọn Boko Haram ti n sọsẹ, lọ sipinlẹ Taraba nibiti wahala darandaran Fulani ati awọn agbẹ ti nbawọn finra. Afurasi naa pẹlu awakọ rẹ, Agyo Saviour ni ọwọ awọn osisẹ ọtẹlẹmuyẹ tẹ. Fun ọdun mẹwa ni awọn agbofinro fi n wa arakunrin jonah Abey pe o lọwọ ninu okoowo ibọn ati ohun ija oloro. Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Gẹgẹbii awọn osisẹ ọtẹlẹmuyẹ se sọ, lati orilẹede Cameroon ati apa ila oorun ariwa orilẹede Naijiria ni ọgbẹni Jonah Abbey ti n ko awọn ohun ija oloro yii wọle. Afunrasi naa ni oun ko jẹbi ẹsun ti wọn fi kan oun o, sugbọn awọn osisẹ ọtẹlẹmuyẹ ni, yoo fi oju ba ile ẹjọ laipẹ.",0,yoruba nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o nuni ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo.,0,yoruba yi fi ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa aráyé: ti o ní wúlò.,0,yoruba "àtọ́wọ́dá, àwọn oníṣẹ́ ìṣẹ́ ni a ní nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o nuni ti o nuni ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó jẹ́ dára jù...",0,yoruba "Ẹ káàárọ̀ o. Ẹ kú ìsimi òpin ọ̀sẹ̀. Ẹ̀bẹ̀ la bẹ̀ Olúwa fún wa nísimi, ẹ ò ṣàmín #YorubaCulture #yoruba #morning #weekend",0,yoruba "Akọwe Arẹwa to salaye ọrọ yii fawọn akọroyin , tun fikun pe, ẹgbẹ Arẹwa kede atilẹyin rẹ fun oludije fẹgbẹ oselu APC, aarẹ Muhammadu Buhari lẹyin to ti se agbeyẹwo afojusun ẹgbẹ oselu kọọkan, ileri ohun ti wọn fẹ se se ati bi oludije kọọkan se kun oju osuwọn si. Sani to gba pe lootọ ni kii se asa ati ise ẹgbẹ Arẹwa lati pọn sẹyin oludije ẹgbẹ oselu kan fikun pe, awọn ti fi iroyin nipa oludije si etigbọ awọn oludibo, ki wọn si se idajọ fun wọn. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: O ni awọn fọwọsi aarẹ Muhammadu Buhari lasiko eto idibo to kọja lai naani awọn aise deede ẹgbẹ oselu APC to n sejọba lọwọ, nitori ilọsiwaju ilẹ Naijiria ni. O fikun pe, ẹgbẹ arẹwa to sẹyin Buhari ko ba lee rọrun fun lati pada wa se afikun awọn aseyọri to ti se tẹlẹ ni saa akọkọ rẹ. World TB Day: Funkẹ Dosunmu ni ikọ́ ife kìí pani, ta bá lo òògùn rẹ̀ déédé Sani ni, ko si ẹgbẹkẹgbẹ tabi ẹnikẹni to wa eekanna mọ ẹgbẹ Arẹwa lọrun lati se atilẹyin fun Buhari amọ awọn aseyọri rẹ, afojusun rẹ ninu ileri ipolongo ibo rẹ ati agbara ti ẹgbẹ oselu kọọkan ni, ni awọn se agbeyẹwo rẹ. Akọwe ẹgbẹ Arẹwa ni, ẹgbẹ naa kẹyin si oludije fun ipo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ oselu PDP, Atiku Abubakar, nitori bo se n polongo kiri pe oun yoo se atunto ilẹ yii, ti oun yoo si tun ta awọn dukia ajọni wa kan bii ileesẹ NNPC. Oshisko twins: Ojú wa rí, ṣùgbọ́nÌgbọ́raẹniyé ló ń ràn wá lọ́wọ́ O fikun pe, gbogbo awọn dukia ti wọn ti ta nilẹ Naijiria tẹlẹ ko mu eso rere kan wa, bakan naa si ni eto atunto to n polongo ko nitumọ mọ ni asiko yii, tori pe, atunto ti ba awọn ẹka isejọba wa tẹlẹ bii ẹka eto iselu, ọrọ aje ati ẹkun idibo kọọkan. Antony Sani ni ohun to ja ju lakoko yii ni akoso to peye nipa awọn ohun alumọni orilẹede yii, to si fi ohun to n waye nipinlẹ Eko se apẹẹrẹ.",0,yoruba "Kọmiṣonna fun eto ẹkọ ipinlẹ ọhun, Badamasi Lawal Chiranci sọ fun BBC pe ijọba ipinlẹ naa ti pese 580 miliọnu ti wọn yoo fi kọ ogiri yii awọn ile ẹkọ naa ka. O fi kun pe wọn yoo tun lo lara owo ọhun lati ra awọn aja lọna ati koju eto abo to mẹhẹ. Chiranci ṣalaye pe awọn aja naa yoo maa ta awọn agbofinro lolobo ni gbogbo igba ti nnkan ko ba fẹ ṣẹnu ire nipa ti eto abo. Gẹgẹ bo ṣe sọ ""Ti awọn aja naa ba ti kofiri ohunkohun to le ṣakoba fun eto abo, wọn yoo tete ta awọn agbofinro lolobo, eyii ti yoo wulo fun gbogbo araalu."" aaaaaaaaaaaaaaa Kọmiṣọnna naa fikun pe awọn yoo tun ṣe idanilẹkọọ fun awọn akẹkọ lori ọna ti wọn yoo fi da awọn janduku mọ, ki wọn le maa tete ke si awọn ọlọpaa. O pari ọrọ rẹ pe, iṣẹlẹ ijinigbe to waye ni Katsina kiba ma ti waye to ba jẹ pe awọn akẹkọọ mọ bi wọn ṣe le bojuto eto abo ara wọn. Slain Ekiti Police woman: Ìyá rẹ̀ ní àìrìṣẹ́ṣe ló mú kí Bukola Olawoye gba iṣẹ́ ọlọ́pàá",0,yoruba N jẹ ẹyin mọ pe orin gbigbọ fawọn ọmọ tuntun jojolo maa n ṣe iranwọ nla fun ati dagba ọpọlọ wọn? Awọn oluwadii kan nileewe giga fasiti ilu Geneva lo fidi rẹ mu lẹ gbigbọ orin maa ṣe atunṣe ọpọlọ awọn ọmọde. Awọn oluwadii naa sọ siwaju pe orun orin yii maa n ran awọn ọmọ ti wọn bi nigba toṣu wọn ko tii pe lọwọ lati dagba.,0,yoruba "♪ ÌṢẸ̀ṢE dọwọ́ ẹ̀yin baba wa! Ẹ̀ máà jẹ́ ó bàjẹ́ o, ẹ̀sìn'ṢẸ̀ṢE dọwọ́ ẹ̀yin baba wa""""""""""""""""- lóhùn Àṣàbí Ọ̀jẹ̀. #IseseDay https://t.co/qgNiIxGQv6",0,yoruba ẹ kú ìrọ̀lẹ́ o ẹ̀yin tèmi ṣé ká ṣeré kan,0,yoruba ọlọ́run ọba ṣèyíówùú náà ló gbéwa dìde lórí ìtẹ́ kó má ṣàì dáàbò rẹ̀ bòwá lọ́jọ́ òní,0,yoruba "Nígbà tí Ìyá fè fi, Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba "Ilẹ n jẹ èèyan, Ikú ti mú Olanrewaju Malcolm ọkọ Bisola lọ Malcolm to jẹ alakoso oṣere nigba aye rẹ niroyin to n tẹ wa lọwọ sọ pe o ku laarọ oni, ọjọ Abamẹta si ile iwosan kan ni agbegbe Surulere, nilu Eko. End of Twitter post, 1 Iroyin naa sọ pe ọgbẹni Malcolm papoda lẹyin ti o ti ba aisan kan finra fun ọjọ pipẹ ni ẹni ọmọ ọdun mẹtadinlogoji. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Olanrewaju Malcolm kú lẹ́yìn àìsàn ọjọ́ pípẹ́ Eyi ni ọrọ asọkẹyin oloogbe lori opo Instagram rẹ ni yi pe, iyipada ti de ba oun. Ilẹ n jeeyan, ko si awaye-ma-lọ. Aarun ọpọlọ kii se idajọ iku Wo fidio ikede iku Hawking to ku lẹni ọdun mẹrindinlọgọrin (76)",0,yoruba "Araba ilu Osogbo, Oloye Yemi Elebuibon t i sọ pe awọn ẹlẹsin ibilẹ naa fẹ ki awọn ọmọ awọn naa maa wọ ilẹkẹ lọ si ile ẹkọ. Laipẹ yii ni ija bẹ silẹ niluu Ilorin lori awọn akẹkọọ musulumi tawọn alaṣẹ ileewe girama kristẹni ko gba laaye lati maa wọ Hijaabu wa si ileewe. Awọn alaṣẹ ileewe naa naa yari pe ilana ẹsin kristẹni lawọn fi da awọn ile ẹkọ ọhun silẹ. Fun idi eyi, wọn gbagbọ pe ko yẹ ki awọn akẹkọọ musulumi maa wọ hijaabu wa si iru ile ẹkọ bẹẹ. Amọ, awọn musulumi ni ijọba ipinlẹ Kwara ti gba awọn ile ẹkọ yii lọwọ awọn ijọ kristẹni to dawọn silẹ. Nitori naa, awọn musulumi sọ pe o yẹ kawọn ọmọ awọn to jẹ akẹkọọ lawọn iru ileewe bẹẹ lanfaani lati maa wọ hijaabu. Nigba ti o n ba BBC Yoruba sọrọ, Elebuibon ni awọn ẹlẹsin abalaye naa lẹtọ labẹ ofin gẹgẹ bi awọn ẹlẹsin musulumi ati kristẹni. ''Ko lẹtọ ko jẹ pe ki wọn maa sọ fawọn ọmọ oniṣẹṣe pe ki wọn maa bọ ilẹkẹ to wa lọwọ wọn. Awa o ni kawọn ọmọ musulumi maa wọ hijaabu, a o ni kawọn ọmọ kristẹni maa mu ilẹkẹ ''Rosary'' ni, ṣugbọn ki wọn jẹ ki awa naa ṣe ti wa. Ki wọn jẹ ki onifa bọ Ifa, ki ọlọṣun bọ Osun, ki olodu bọ Odu, ki aye ba le dara,''Elebuibon ṣalaye. Agba babalawo naa fikun ọrọ rẹ gbogbo ẹsin mẹtẹẹta loyẹ ki ijọba fun laaye lati ṣe ẹsin wọn lai ṣegbe fẹni kan. Elebuibon ni ''ooṣa lo ni gbogbo ilẹkẹ ti a ni nilẹ Yoruba. Ilẹkẹ otutu ọpọn ni wọn maa n fi dawọn oniṣẹṣe mọ, awọn oni Sango le mu irọkẹ lọwọ.'' Elebuibon ni o jẹ iyalẹnu pe nnkan ti ara wa ni kii wu wa. Araba ilu Osogbo sọ pe awọn musulumi atawọn kristẹni to bara wọn lori ọrọ wiwọ hijaabu, ai si ifẹ lo n fa iru iṣẹlẹ bẹẹ. Elebuibon rọ awọn kristẹni ati musulumi papaa julọ niluu Ilorin pe ki wọn lọ wa imọ nipa ẹsin miiran nitori ko yẹ ki ẹsin fa ija rara. Agba babalawo naa ṣalaye pe awọn oniṣẹṣe yoo gbe aba naa lọ si iwaju ijọba lati ṣe agbekalẹ ofin ti yoo fawọn oniṣẹṣe naa lanfaani lati maa ṣe ẹsin gẹgẹ bi wọn ṣe fẹ.",0,yoruba "Ní igba mi owó àkokò, Ìyá lo tun se se.",0,yoruba Ẹ gbọ́'yìí o. Orin aládùn --> #AwaOTushOh ~ http://t.co/8t5ZxITH #Dobale ~ http://t.co/3ZVj8iMA,0,yoruba "Yatọ si Dagrin, awọn orukọ bi i Barack O'Grin, Lyricle Wayray, Akogun, Omo ogun, ni wọn tun mọ ọ si. Ọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu Kẹwa ọdun 1984 ni wọn bi , ṣugbọn o ku lẹni ọdun mẹẹdọgbọn, ni ọjọ kejilelogun, oṣu Kẹrin, ọdun 2010 lẹyin to ni ijamba ọkọ nilu Eko. Ọjọ kẹrinla, oṣu Kẹrin ni ijamba alagbara naa waye, lasiko ti ọkọ ayọkẹlẹ rẹ forigbari pẹlu ọkọ akẹru kan ni adugbo Mushin. Ileewe alakọbẹrẹ Meiran Community Primary school, Roseille nursery and primary school, Meiran Community High school, ati Egbado College lo lọ. Iya rẹ ni iyawo kẹta ninu iyawo mẹta ti baba rẹ ni Baba rẹ jẹ oniṣowo rẹkọọdu orin, o si ni ile itaja kan, House of Nelly sounds, ni ibudokọ Meiran nigba kan. Nigba aye rẹ, orukọ Dagrin lori Twitter ni @Dagrinfimile, o si n lo Dagrin fimilejo lori Facebook. Ọjọ kẹjọ, oṣu Kẹrin, ọdun 2010 lo lo ayelujara Twitter gbẹyin. Lootọ lo ti ku, awọn eniyan ṣi n fi ọrọ iranti si oju opo Twitter rẹ. Ọna ti Dagrin n gba kọ orin rẹ gbajumọ pupọ laarin igboro nigba naa, nitori pe awọn orin rẹ ma n ba idojukọ ogunlọgọ awọn ọdọ Naijiria mu. Awo orin rẹ, Chief Executive Omota, gba ami ẹyẹ Hip hop World Award fun orin 'rap' lọdun 2010. O ba awọn akọrin bi i 9ice, Y.Q, M.I, Iceberg Slim, Omobaba, Terry G, Omawumi, ati Konga kọrin pọ. Orin 'if I die', to tu mọ si 'Ti mo ba ku', lo gbe jade kẹhin. Ko si pẹ ti orin naa jade lo ku. Eyi to mu ki ọpọ o sọ nigba naa pe boya o ti mọ pe oun fẹ ẹ ku lo ṣe kọ orin naa. Diẹ lara awọn orin to kọ ni:",0,yoruba ohun tí ó bá gbà ni a máa fi fún un aláyìnrín gbàyìnrín ẹbọ ní iléeṣẹ́ aṣojú orílẹ̀èdè nàìjíríà ní france,0,yoruba iṣẹ́ ni nkan pataki lojiji. Ọba lo tun se fi. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba nilo ayẹwo wey ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó wáyé..,0,yoruba lẹ ìkòkò wey ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọba lo ojú odò.,0,yoruba wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọmọ lo aye àìlẹ̀.,0,yoruba "Igba akọkọ kọ niyii ti wọn yoo fi orukọ Burna Boy silẹ fun ami ẹyẹ Grammy, amọ ko gba a ri Awo orin rẹ, 'Twice as Tall', ni wọn fi orukọ rẹ silẹ fun, ni iṣọri orin to dara julọ ni agbaye, Best Global Music Award. Isọri naa wa fun awọn awo orin to ni o kere tan, ìdá mọkanlelaadọta ohùn orin igbalode. Burna Boy ati akọrin mẹrin miran ni wọn jọ fi orukọ wọn silẹ fun isọri yii. FU CHRONICLES Antibalas TWICE AS TALL Burna Boy AGORA Bebel Gilberto LOVE LETTERS Anoushka Shankar AMADJAR Tinariwen Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ̀ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí Igba wo lo maa waye? Ọjọ kọkanlelọgbọn, oṣu Kinni, ọdun 2021, ni eto ami ẹyẹ Grammy yoo waye. Ohun si ni ikẹtalelọgọta ti yoo waye, pẹlu isọri ami ẹyẹ ọgọrin. Ṣugbọn ko ti i si aridaju lori bi eto naa yoo ṣe lọ, tabi awọn akọrin ti yoo ṣere nibẹ, nitori aarun covid-19. Awọn isọri to ku ni 1.Awo orin fun ọdun 2020 BLACK PARADE Beyoncé Beyoncé & Derek Dixie, olootu; Stuart White, omojuẹrọ/alasopọ orin; Colin Leonard, amojuẹrọ COLORS Black Pumas Adrian Quesada, olootu; Adrian Quesada, amojuẹrọ/alasopọ orin; JJ Golden, amojuẹrọ Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ ROCKSTAR DaBaby Featuring Roddy Ricch SethinTheKitchen, olootu; Derek ""MixedByAli"" Ali, Chris Dennis & Liz Robson, amojuẹrọ/alasopọ orin; Susan Tabor, amojuẹrọ SAY SO Doja Cat Tyson Trax, olootu; Clint Gibbs, amojuẹrọ/alasopọ; Mike Bozzi, amojuẹrọ EVERYTHING I WANTED Billie Eilish Finneas O'Connell, olootu; Rob Kinelski & Finneas O'Connell, amojuẹrọ/alasopọ orin; John Greenham, amojuẹrọ DON'T START NOW Dua Lipa Caroline Ailin & Ian Kirkpatrick, olootu; Josh Gudwin, Drew Jurecka & Ian Kirkpatrick, amojuẹrọ/alasopọ orin; Chris Gehringer, amojuẹsrọ CIRCLES Post Malone Louis Bell, Frank Dukes & Post Malone, olootu; Louis Bell & Manny Marroquin, amojuẹrọ/alasopọ orin; Mike Bozzi, amojuẹrọ SAVAGE Megan Thee Stallion Featuring Beyoncé Beyoncé & J. White Did It, olootu; Stuart White, amojuẹrọ/alasopọ orin; Colin Leonard, amojuẹrọ Ẹ wo ẹkunrẹrẹ orukọ nibi",0,yoruba "Wàhálà tó ń bẹ́ sílẹ̀ lágbo òṣèlú APC ti ń kọ àwọn eeyan lominu; pàápàá láàárín Oyegun àti Gómìnà Okorocha Ko pẹ yii ti ariwo rukerudo sọ laarin ẹgbẹ oṣelu APC to n ṣejọba lorilẹede Naijiria; eyi ko si tii jo lọlẹ ti aye tun gbọ ariwo ija agba meji laarin ẹgbẹ oṣelu APC. Alaga apapọ ẹgbẹ oṣelu APC, John Oyegun ati Rochas Okorocha to jẹ alaga igbimọ awọn gomina ipinlẹ labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu APC ni wọn n gbena wo oju ara wọn bayii. Oyegun ni ogun afọwọfa lo n ja Gomina Okorocha Idi wahala wọn ko si ṣẹyin abajade idibo abẹnu ẹgbẹ oṣelu naa eleyii ti Gomina Okorocha ni awọn alagbara kan laarin ẹgbẹ oṣelu naa n lo lati yọ ọwọ oun lawo bi nkan ṣe n lọ si lẹgbẹ oṣelu naa, papaajulọ , ni ipinlẹ Imo. Kato wi kato fọ, alaga ẹgbẹ oṣelu naa, John Oyegun ni iroyin sọ pe o da gomina Okorocha lohun ọrọ rẹ ni kia pe ko ṣẹri pada sile lọ yẹ ara rẹ wo lati mọ ibi ti bata ti n taa lẹsẹ. Ninu ọrọ Oyegun, ogun afọwọfa lo n ja Gomina Okorocha nitori ninu iwoye rẹ awọn igbesẹ gomina ipinlẹ Imo naa lo n mu kawọn eeyan rẹ o kọ ipakọ sii. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Nigba to wa n ba BBC sọrọ, amugbalẹgbẹ fun fun Gomina Ipinlẹ Imo, Rochas Okorocha lori ọrọ ibanisọrọ ayelujara, Ebere Nzewuji ni ọrọ ti Jọhn oyegun n sọ ko ta leti awọn eeyan ipinlẹ naa 'to mọ pataki iṣẹ ti Gomina Okorocha ti gbe ṣe nibẹ.' ""Ọrọ alaarẹ ni John Oyegun n sọ. Ikanra kikuna to kuna lati ri anfani alaga apapọ ẹgbẹ oṣelu APC gba lẹẹkeji ni oloye Oyegun fẹ fi mọ gomina Okorocha.""",0,yoruba "Isoro oju ọna to di pa naa waye nitori bi ileesẹ Berger to n se atunse abala kan ni opopona Marosẹ Ibadan silu Eko, se tun ti abala kan oju ọna naa pa, eyi to lọ si Ibadan lati Eko. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Bẹẹ ba gbagbe, oju awọn araalu ri mabo lopin ọdun 2019 nigba ti ileeẹ to n se oju sna ọhun ti abala kan pa ladugbo Kara si Berger, eyi to nira fun ọpọ eeyan lati gba oju ọna ọhun wọ ilu Eko. Lọwọlọwọ bayii, wahala naa tun ti peleke si lati Ọjọ Aje, ọjọ Kẹfa osu Kinni ọdun 2020 nigba ti wọn tun ti abala titi naa pa, ti ọpọ awọn eeyan to n gba opopona ọhun si n lo wakati mẹta, o kere tan, ki wọn to ri ọna kọja. Iroyin to n tẹ wa lọwọ bayii ti wa fidi rẹ mulẹ pe, se ni awọn ọkọ duro lai lee lọ siwaju abi sẹyin lopopona marosẹ to wọ Ibadan si Eko ati eyi to lọ lati Eko si Ibadan nitori ọna ti wọn ti pa naa. Nigba to n sọrọ lori bi wọn se ti ọna ọhun pa, Ademọla Kuti, tii se oludari feto isẹ ode nileesẹ to wa fọrọ isẹ ode labẹ ijọba apapọ, fi ọwọ gbaya pe isẹ yoo ya kiakia lori atunse opopona naa nitori akoko ẹẹrun ti a wa. BIAFRA at 50: Ìhàlẹ̀ ológun ni Gowon ni ká kọ́kọ́ fi bẹ̀rẹ̀- Aladejẹbi Kuti fikun pe ti yoo ba fi di idaji osu Keji shun 2020, o seese ki awọn isẹ atunse oju ọna Ibadan si Eko ti buse ki ojo too bẹrẹ. Ìjàmbà ọkọ̀ akẹ́rù ní Ikòròdú fa súnkẹrẹ-fàkẹrẹ ọkọ̀ ní Márosẹ̀ Ijamba ọkọ Akẹru naa n fi kun asiko irinajo awọn eniayn Laarọ ni wọn ni awọn ọkọ akẹru meji kọkọ gba ara wọn ni agbegbe Ikorodu ni ipinlẹ Eko ni Guusu Naijiria. Iroyin ni ijamba yii fa sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ ni eyi to fi kan awọn ọkọ to n rin ni opopona mejeeji awọn to n lọ ati awọn to n bọ pada wọnu Eko. Ko pẹ ti ijamba yii ṣẹlẹ ni wọn ni awọn ajọ ẹṣọ alaabo oju popo (FRSC) ti de sibẹ lati pese iranwọ to yẹ. Ìjàmbà ọkọ̀ akẹ́rù ní Ikòròdú fa súnkẹrẹ-fàkẹrẹ ọkọ̀ ní Márosẹ̀ Awọn eniyan ti n gbọ sọ fun ara wọn lati yago fun opopona Ikorodu bayii nitori pe ijamba to ṣẹlẹ nitosi agbegbe Obanikoro naa ko kere Ìjàmbà ọkọ̀ akẹ́rù ní Ikòròdú fa súnkẹrẹ-fàkẹrẹ ọkọ̀ ní Márosẹ̀ Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni pe awọn oṣiṣẹ to n mojuto igbokegbodo ọkọ nipinlẹ Eko, LASTMA ti de sibẹ wọn si ti di ọna naa pa ki wọn le raaye wọ awọn ọkọ akẹru naa kuro. Ijamba oko akeru ni Obanikoro ti fa sunkere fakere oko Idásilẹ̀ Amotekun ko ba òfin ọdún 1999 mu- Malami Ọ̀gá mi fẹ́ fi tipá bámi lòpọ̀ ní Lebanon àmọ́ ìjọba yọ mí l'óko ẹrú - Ọmọ Nàíjíríà míì Bí ìtàn ayé Toyosi Arigbabuwo ṣe lọ rèé láti ẹnu Musiliu Dasofunjo àti Ogun Majek Àsọtẹ́lẹ̀ Fada Mbaka, tó yẹ àga mọ́ gómìnà Imo nídìí rèè BIAFRA at 50: Ìhàlẹ̀ ológun ni Gowon ni ká kọ́kọ́ fi bẹ̀rẹ̀- Aladejẹbi",0,yoruba "Ilé ìgbọ̀nsẹ̀ tóo lọ lọ́dún tó kọjá, ó yẹ kóo dúpẹ́, fun gbogbo ohun too ṣe lọdun to kọja, o yẹ koo dupẹ. Gbajugbaja ojiṣẹ Ọlọrun ni, Woli Samuel Abiara to jẹ oludari agba ijọ Christ Apostolic Church (CAC) lagbaye gbadura fawọn eniyan pe 2020 a dara. Nigba ti BBC Yoruba ba Baba SK Abiara lalejo, ọpọ ọ̀rọ̀ lo fi gba awọn ọmọ Naijiria niyanju. Baba ni ""o ṣàgbèrè lọ́dún tó kọjá, má ṣe irú ẹ̀ mọ́, iṣekuṣe, ole, ma ṣe bẹẹ mọ. Ṣe ni koo faye rẹ ati ọkan rẹ fun Ọlọrun"". Awọn adura kabiti kabiti ni baba fi kasẹ ọrọ ikini ku ọdun tuntun nilẹ.",0,yoruba "Pasitọ Biodun Fatoyinbo àti Busola Dakolo Eyi ni ero agbẹjọro kan, Mohammed Ghali Alaaya ti o ba ile iṣẹ BBC Yoruba sọrọ lori ọrọ yi. Laipẹ́ yi ni awọn akojọpọ agbẹjọro kan ati awọn ajafẹtọ-ọmọniyan kan sọ pe awọn ko fẹ ki wọn gbọ ẹjọ naa ni Abuja bi ko ṣe ni Eko ti wọn ti mẹsun naa wa. Ilu Ilorin nipinlẹ Kwara ni wọn ni Biodun Fatoyinbo ti da ẹsẹ naa ni nnkan bi ogun dun sẹyin amọ lọwọ bayi ilu Abuja lo fi ṣe ibujoko. Ninu alaye agbẹjọro Ghali Alaaya ti ile iṣẹ agbẹjọro Tafa Ahmed & Co, o ni ''ilu ti ọdaran ba ti da ẹsẹ ti ile ẹjọ to si kaju oṣunwọn lati gbẹjọ naa ba ti wa nibẹ lo jẹ ibi akọkọ ti a ti n gbọ iru ẹjọ bẹẹ.'' O ni: ''Nkan mẹta lo máa n ṣe atọna ibi ti a ti le gbẹjọ ọdaran.Akọkọ ni awọn tọrọ naa kan,iru ẹṣẹ ti wọn gbe lọ si ile ẹjọ ati iru agbara ti ile ẹjọ naa ni lati gbọ iru ẹjọ bẹ'' Ghali sọ pe ti ile ẹjọ to ba lagbara lati gbọ ẹjọ naa ba ti wa ni ilu ti wọn ti da ẹsẹ ti ọdaran naa si n gbe ilu naa,ibẹ ni wọn yoo ti gbẹjọ rẹ. O tẹsiwaju pe ti ko ba rọrun lati gbọ ẹjọ naa ni ile ẹjọ yi to ri pe ọdaran naa ko gbe ilu ohun,ibi ti o n gbe nibi ti ọrọ kan lati gbọ ẹjọ naa''lopin igba ti ile ẹjọ to ba ka oju osunwọn ba ti wa nibẹ.'' Nipa ọrọ Fatoyinbo to jẹ pe ilu Eko ni wọn ti fẹsun kan an ṣugbọn to n gbe ilu Abuja, Alaaya ni ohun to sunmọ ju pe yoo ṣẹlẹ ni ''ki wọn gbẹjọ naa ni lọ ilu to ba ti dẹsẹ naa''. ''Amọ ti idiwọ ba wa ti ko ni jẹ ki igbẹjọ nibẹ rọrun,ilu ti ọdaran n gbe ni ibi to kan lati gbẹjọ naa.'' O wa fi kun ọrọ rẹ pe o ṣeeṣe lẹyin ti ọrọ naa ba de iwaju adajọ ko jẹ Eko ni wọn yoo ti gbẹjọ naa ṣugbọn ọrọ ku si ọwọ adajọ.",0,yoruba "Ẹyín tèmi, ẹ k'áàsán o! Ẹ jọ̀wọ́, ẹ jẹ a ṣ'ayé re k'ayé lè ṣe wá re... Ire o. #yoruba",0,yoruba Corona Virus: Àyẹwò fi han pé kìí ṣe àìsàn naa lo ń se àkẹkọọ ti wọ́n fura si Sùgbọ́n ìdùnú subu lú ayọ fun gbogbo ènìyàn ilẹ Afirika wi pé àbájade àwọn àyẹwò ti wọ́n ṣe fun àkẹkọ̀ọ́ náà fi han pe ko ni àìsàn náà. Corona Virus: Àyẹwò fi han pé kìí ṣe àìsàn naa lo ń se àkẹkọọ ti wọ́n fura si Iroyin to fi ìdí ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀ wáye nínú àtẹjáde kan ti ile iṣẹ́ ètò iléra orílẹ̀-èdè náà gbé jáde ti wọ́n si fi si lóri àtẹjisẹ Facebook Kokoko lára akẹkọ̀ọ́ náà le ti o sì ti padà si ọ̀dọ̀ àwọn ẹbi rẹ̀.,0,yoruba "ọlọ́run fẹ. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba """"""""" fún ọdún méjì gbáko , New Times Rwanda jíyìn ìròhìn .",0,yoruba Messi àti Músá ló ń ta #idanoripapa #SuperEagles #Argentina,0,yoruba 11. Ìran awo kì í sán bàntẹ́ awo ẹgbẹ́ 'ẹ̀. Ìran Ògúnfúnminírè kì í jẹ ẹran ejò. Ìran Oníkòyí kì í jẹ ẹran_______ #Ibeere #Yoruba #Eewo #Ikoyi #Akesan #Iseri #Oriki,0,yoruba Àwa wá ń kọ́ o? #Ebola #Nigeria #africa,0,yoruba "Emmanuel Ameneke Eyi waye lẹyin ti Taifa Stars ti wọn ṣẹṣẹ kopa ninu idije ife ẹyẹ Nations Cup lati ọdun 1980 ko lee tẹsiwaju mọ ninu idije to n waye ni Egypt tori wọn ja kulẹ lẹẹmẹta. A ó jà fitafita láti ríi pé a ò já kulẹ̀ lónìí - Genort Rohr Ọdun 2018 ni wọn yan ọmọ ẹgbẹ agbabọọlu Naijiria tẹlẹri, Amuneke gẹgẹ bii akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu orilẹede Tanzania. Ati ẹgbẹ agbabọọlu ati akọnimọọgba wọn, Amuneke jọ tọwọ bọwe adehun lati fopin si iṣẹ rẹ gẹgẹ bi TFF ṣe fi si oju opo ayelujara wọn. Fulani Kidnapping: Owó púpọ̀ la san kí wọ́n tó fi mi sílẹ̀ Ọgbẹ naa ni awọn yoo yan akọnimọọgba kan na fun 'gba diẹ lẹyin ti awọn ba ṣe ipade pajawiri lọjọbọ ọsẹ oun si ni yoo dari awọn fun idije ife ẹyẹ African Nations Championship (CHAN) eyi ti wọn yoo bẹrẹ loṣu yii. Amuneke to tun ti jẹ agbabọọlu fun Barcelona ni igbakeji akọnimọọgba Naijiria nigba ti Naijiria jawe olubori ni ife ẹyẹ agbaye FIFA U- 17 fun igba kẹẹrin i UAE lọdun 2013. Awọn Iroyin ti ẹ le nifẹ si Lẹyin ọdun meji lo dari Naijiria lọ si idije FIFA U- 17 ẹlẹẹkarun un ni chile eyi to mu ki o gba igbega di akọnimọọgba fun ikọ Flying Eagles U- 20. Gẹgẹ bii agbabọọlu, Amuneke ko ṣee fọwọ rọ sẹyin ninu ikọ Super Eagles, oun lo jẹ goolu mejeji ni AFCON 1994 lorilẹede Tunisia nibi ti Naijiria ti fi ami ayo meji si ẹyọkan pẹlu Zambia gba ipo keji nilẹ Afirika.",0,yoruba "ADDRESSING OF ELDERLY ONES Nínu agbo-ilé, ẹni tí ó bá ti dàgbà tó láti jẹ́ bàbá tàbí fún èèyàn, ohun ni a ma ń pè ní: BÀBÁ KÉKERÉ ÌYÁ KÉKERÉ. Anyone old enough to be someone's parent, in a family house, is who they call: SMALL FATHER SMALL MOTHER",0,yoruba "Ijọba ti pinnu láti gbé ìgbẹ́sẹ̀ to nípọn lóri ẹni to ba ń sùn lẹ́nu iṣẹ́. John Berr to jẹ onímọ nípa oorun sọ pe bó tilẹ̀ jé pé àwọn òṣiṣẹ́ ìjọba tí ń ja ìjà yìí típẹ̀, ṣùgbọ́n ti ìjọba ko kọbíara síi. ""Wọn ò gbà àwọn ènìyàn láàyẹ lati sùn ní ẹnu iṣẹ́ pàápàá jùlọ ni àwọn ilé iṣẹ́ ìjọba àyàfi tí ẹni náà ba gba àṣẹ, èyí wà nínú àtẹjáde ti ìjọba fi síta nínú oṣù yìí. Kò si ẹni to yé ìdí ti ìjọba fi gbé ìgbésẹ̀ yìí ṣugbọn wọ́n si kọ̀ láti sọ ǹkankan lée lóri bí gbogbo ènìyàn ṣe ń bẹnu ẹ̀tẹ́ lùú. Ǹjẹ o yẹ kí èèyàn máa sùn lẹ́nu iṣẹ́? Ní ọdun 2018 ọfíísì agbẹjọrò àgbà fún ìpínlẹ̀ California fí àbájade ìwádìí kan nípa òṣìṣẹ́ ilé iṣẹ́ mọ́tò kan to ń sún oorun wákàti mẹ́ta lójòòjúmọ lẹ́nu iṣẹ́ sita. Ìròyìn sọ pé ẹgbẹ̀rún lọ́nà ogójì dọ́la ni ìjọba ń pàdànú láàrin ọdún mẹrin. Black women live matters: Ọdún 2015 ní àwọn ọlọ́pàá pa India Kager láìní ìdí- Gina Best Bákan náà ní òṣìṣẹ́ tó ń sùn lẹ́nu iṣẹ́ n kó ìnira bá àwọn òṣìṣẹ́ to kù ni, nítorí àwọn kan ló ń ṣe iṣẹ́ rẹ̀ lásìkò tó n sùn. Ọgá àgbà ilé ẹkọ kan ni iporuuru dé bi pé o ró pé òṣìṣẹ́ òhun ni àìsàn kan ti o ń mú kí o maa sùn lẹ́nú iṣẹ́. Ó di dandan kí ará India yìí sọ ìdí tó fi ń sìn kìnìhún- Egbeyemi Bó tilẹ̀ jẹ́ pé bi ìjọba ṣe dẹkun ki òṣìṣẹ́ máa sùn lẹ́nu iṣẹ́ lé mu ọkàn pòruuru, síbẹ̀ ìfọ̀rọ̀wérọ̀ o dúró lóri rẹ̀. Ààrẹ ilé ìwòsàn obinrin Boston, Ọniṣegun oyinbo Lawrence Epstein, sọ pé o lé ni èèyan ààdọrin mílíọnù to ni ìṣòrò oorun ni ilẹ̀ Amerika.",0,yoruba Kí la tún ń wọ́ọ̀kì! Ìjọba wa ò mọ rírì ọrọ̀ ènìyàn àti ọgbọ́n àtinúdá tí Olódùmarè fi jínìnkẹ́ ọmọ orílẹ̀-èdè yìí. #Kilawanwork,0,yoruba [Cubaaz Yorùbá] Anfani nlanla wa fun awọn 300 ti o ba kọkọ darapọ mọ Cubaaz. Anfani wo ni yẹn o? E o ni anfani lati jere 20% bonus lori iyekiye ti ẹ ba nawo sori cubaaz. Jubẹlọ ẹ tu jere '100% bonus' lori iyekiye ti ẹ ba mu sile. #Cryptocurrency #Yoruba #Blockchain https://t.co/H5cfBfUxZh,0,yoruba "RT @user: O fẹ mu, ko ma le mu o... @user @user",0,yoruba "Urban Study Group , ẹgbẹ́ aṣiṣẹ́ ọ̀fẹ́ - tí - kò - ní - èrè tí ó máa ń fi ààbò fún àwọn ohun àjogúnbá Dhaka Àtijọ́ fi ìwé ẹ̀dùn ìdáwọ́dúróo àdàwólulẹ̀ náà ránṣẹ́ sí àwọn tí ọ̀rán kàn , tí ó sì mẹ́nu ba àṣẹ Ilé - ẹjọ́ Gíga .",0,yoruba Kò bá dára kí a kó àwọn arúgbó wa jọ kí wọ́n dá wa lẹ́kọ̀ọ́ nípa àṣà àti ìtàn wa kí a kọ gbogbo kalẹ̀ fún ọjọ́'wájú.,0,yoruba "Tinubu ni baba isalẹ fun Buhari lati di aarẹ lọdun 2015 Iroyin kan to faharan lori opo ikansiraẹni tuwita ti ileesẹ aarẹ Naijiria fisita salaye wipe Aarẹ Buhari yan asiwaju Bola Tinubu lati se aayan ijiroro, ifinukonu, ati irapada igbẹkẹle awọn ọmọ ẹgbẹ ninu isọkan ẹgbẹ oselu naa. Kii se iroyin mọ wi pe lẹnu lọọlọọ yii, nkan o rọgbọ fun ẹgbẹ oselu APC pẹlu oniruru iroyin nipa edeaiyede, ẹhonu ati ibinu awọn igun kan ati eeyan kan lẹgbẹ oselu naa. Lara isẹ tuntun ti wọn gbe le Tinubu lọwọ yii, ni pipẹtu si aawọ laarin awọn ọmọ ẹgbẹ oselu naa, ati laarin awọn asiwaju ẹgbẹ pẹlu awọn to di ipo oselu mu nibẹ. Ko ti han faye ọna ti Asiwaju Tinubu yoo gba mu isẹ yii se tabi awọn ti yoo ko mọra fun isẹ yii, sugbọn ohun ti awọn eeyan n sọ nipe eyiun bi awọn iroyin to n lọ kaakiri ba see gbagbọ, Tinubu funrarẹ naa ni awọn ẹhonu kan si ẹgbẹ oselu yii, tawọn eeyan si n beere pe tanni yoo tan ẹhonu tirẹ? ""Gẹgẹbii ara igbesẹ to n lọ lọwọ lati tubọ mu ilọsiwaju ba isọkan laarin ẹgbẹ oselu All Progressive party, APC, Aarẹ Buhari ti yan Asiwaju Bola Ahmed Tinubu lati dari awọn eto ijiroro, ifinukonu ati dida igbẹkẹle awọn ọmọ ẹgbẹ naa pada."" Kini Tinubu sọ? Nigba ti BBC Yoruba kan si ọgbẹni Tunde Rahman to jẹ agbẹnusọ fun Asiwaju Bọla Tinubu lori ọrọ yii, o ni ileesẹ aarẹ ko tii pe Tinubu gan an lati salaye isẹ tuntun yii fun. ""Ori iwe iroyin la ti n ka iroyin yii sugbọn ni kete ti ileesẹ aarẹ ba ti kan si Asiwaju Tinubu, a o sọrọ lori rẹ"" Kini awọn onwoye ri si igbesẹ yii? Agba akọroyin kan, to tun jẹ alẹnulọrọ ninu ọrọ gbogbo to n lọ, Lasisi Olagunju ni, igbesẹ naa ko jọ eyi to lee so eso rere pẹlu bo se jẹ wipe tinubu funrarẹ gan ni ẹhonu. O ni 'iwa ibajẹ ni igbesẹ naa jẹ fun aarẹ lati maa lo irinsẹ ijọba lati mojuto aawọ ẹgbẹ oselu rẹ ati pe lai fọtape, igbesẹ yii ti kuna ko to tilẹ gberasọ' Ọpọ awọn to darapọ mọ ẹgbẹ oselu APC saaju idibo 2015 lo ti n kun fun idi kan tabi omiran Ileesẹ aarẹ si ni isẹ lati se lori sise idamọ awọn to ni ẹhonu ati awọn ti yoo lewaju eto ipẹtu si aawọ yii, igbayi gan an ni a to lee mọ boya Tinubu gan lo tọ si lati lewaju eto ọhun. Gbogbo wa la mọ wipe ni ẹkun iwọ oorun gusu ilẹẹwa, APC o si ni ọkan. Se Tinubu ni yoo lọ maa bẹ awọn ọmọlẹyin rẹ tẹlẹ ti wọn ti jaa ju silẹ ni abi awọn lo maa bẹ Tinubu? ""Aarẹ gan lo yẹ ko gbe igbesẹ lori pipẹtu si aawọ gbogbo lẹgbẹ oselu naa. Mi o ni tan yin, ko si aawọ kan bi alara lẹgbẹ oselu APC, ohun to wa nilẹ nibẹ ni ikunsinu awọn ọmọ ẹgbẹ si iha kokanmi ti aarẹ Buhari kọ ati bo se n ta kete si ẹgbẹ oselu naa. ọna kan ti aarẹ si le gba pari aawọ ẹgbẹ oselu yii ni ki oun pẹlu yi iwa ati ise rẹ pada.""",0,yoruba "Lẹyin iṣẹju mẹta pere ti wọn bẹrẹ ere bọọlu ọhun ni ẹlẹsẹ ayo, Odion Ighalo gba bọọlu sawọn eyi fun Naijiria lanfani lati siwaju ninu ifẹsẹwọnsẹ to kangun su aṣekagba. Ighalo ti gba goolu marun un wọ le bayii lati igba ti idije AFCON 2019 ti bẹrẹ. O ṣeesẹ ko jẹ pe Ighalo lo maa gbami ẹyẹ agbabọọlu to gbayo sawọn julọ ninu idije AFCON 2019. Ẹwẹ, akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu Naijiria, Gernot Rohr sọ ṣaaju ifẹsẹwọnsẹ alẹ Ọjọru pe lẹyin ere bọọlu pẹlu Tunisia l'oun yoo kede bo ya oun yoo tẹsiwaju pẹlu ikọ agbabọọlu Naijiria. AFCON 2019: Ìjà ẹlẹyẹ méjì láàrin Nàìjíríà àti Tunisia Ẹgbẹ agbabọọlu Naijiria ati ti orilẹede Tunisia yoo jọ ta kanungbọn lalẹ Ọjọru lati ja fun ipo kẹta ninu idije AFCON 2019 lorilẹede Egypt. O ku iṣẹju aaya ki ifẹsẹwọnsẹ to kangun si aṣekagba laarin Super Eagles ti Naijiria ati Algeria tan ni Riyad Mahraz gbayo keji wọ le Naijiria. Eleyi to jẹ ki Algeria fi Naijiria ṣatẹgun si ipele aṣekagba pẹlu ami ayo meji sẹyọ kan. Eleyi to jẹ ki Algeria fi Naijiria ṣatẹgun si ipele aṣekagba pẹlu ami ayo meji sẹyọ kan. Ẹgbẹ agbabọọlu Tunisia kuna lati de ipele aṣekagba lẹyin ti Senegal fagba han wọn pẹlu ami ayo kan sodo. Igba akọkọ ree ti ẹgbẹ agbabọọlu Tunisia yoo de ipele to kangun si aṣekagba lati igba ti wọn ti gba ife ẹyẹ AFCON lọdun 2004 ti wọn gbalejo idije ọhun. AFCON 2019: Ki akọnimọọgba Naijira bá wọn sọ̀rọ̀ kóríyá Ọmi ni ikọ agbabọọlu Tunisia ta ninu ifẹsẹwọnsẹ mẹta ti wọn kọkọ gba, ki wọn to na Ghana pẹlu wo mi ki n gba siọ ni ipele ẹlẹni mẹrindinlogun. Eleyi to jẹ ki Algeria fi Naijiria ṣatẹgun si ipele aṣekagba pẹlu ami ayo meji sẹyọ kan. Ṣugbọn wọn fakọyọ ni ipele ẹlẹni mẹjọ lẹyin ti wọn fiya jẹ Madagascar pẹlu ami ayo mẹta sodo. Ikọ Super Eagles jawe olubori ninu ifẹsẹwọnsẹ meji ti wọn kọkọ gba pẹlu Burundi ati Guinea ki Madagascar to fiya jẹ wọn lai ro tẹlẹ. Naijiria fi Cameroon paa ni ipele ẹlẹni mẹrindinlogun pẹlu ami ayo mẹta si meji ki wọn to ṣeya fun South Africa ni ipele ẹlẹni mẹjọ. Algeria lo ṣẹ Naijiria leegun ẹyin ninu ifẹsẹwọnsẹ to kangun si aṣekagba.",0,yoruba RT @user: Àìní ìforítì àparò ló sọ ọ́ di aláṣọ pípọ́n. / Patridge's lack of perseverance is what gave it its dirty garb. [Persev…,0,yoruba Darapọ̀ mọ́ sáfà tó jìn,0,yoruba nípa ìbadandun. A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba "N ò ṣe ojúṣàájú fún àwọn ará Tibet láti ní àwọn ẹ̀tọ́ wọn yìí nìkan , ó wù mí kí àwọn tí wọ́n wá láti Hong Kong àti Taiwan , ìwọ̀ - oòrùn Turkey , àwọn ẹgbẹẹgbẹ̀rún lọ́nà ẹgbẹ̀rún ní ìlọ́po méjì 60 ẹni ogúnléndé tí ó wà ní kárí ayé àti fún gbogbo àwọn ènìyàn láti jàǹfààní ẹ̀tọ̀ wọ̀nyí .",0,yoruba .@user oku ori ire. Oti lo GBA lowo e ko mo lo fun @user A paro wa fun @user ki won ye se slow Eti won di si ikilo,0,yoruba òkú ògálántá ni òkú tí a fi aṣọ wé kí a tó ó gbé e sin sínú ibojì kí ni à ń pe òkú tí a ò fi aṣọ wé ká tó ó sin ín a òkú àìwé b òkú ògolonto d òkú onípàkìtì ️,0,yoruba "Àbẹ́òkúta. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba Rauf Aregbesola sọ bó ṣe yẹ kí òbí máa fètò sọ́mọ bíbí,0,yoruba "Laye atijọ, ati ọmọde ati agba ni wọn maa n kọ orukọ si ara wọn lati fi ṣe ẹsọ ara, tabi fun idanimọ ẹbi tabi ara ti eniyan ti wa. Amọ arabinrin kan rugi oyin nigba to dapara, to tatoo baba isalẹ rẹ, Asiwaju Bola Ahmed Tinubu si ara rẹ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ni Oju opo ikansiraẹni Twitter, ni arabinrin AyokunmiBabato1 ti ke gbajare pe, oun ti ru igi oyin o, oun si ti kọja aye oun pẹlu aworan Tinubu ti oun ya si ẹyin oun. O ni eebu yii ti pọju loju opo ayelujara, nitori naa ọkọ oun to si jẹ baba ọmọ oun ti le oun kuro ni ile bayii, ti oun si ti da alainilelori. O kesi awọn eniyan loju opo Twitter ki wọn ran oun lọwọ nitori oun ṣetan lati yọ aworan ti oun ya si ara naa kuro ni kiakia. Arabinrin naa fikun pe, inira ati eebu to tẹlẹ tatoo Tinubu ni ara oun ti pọju fun oun lati farada. Amọ, awọn eniyan to fesi si tatoo naa ni arabinrin naa n wa ki Tinubu se akiyesi oun ni, amọ o ti wa doju rẹ bayii. Ọkan tilẹ sọ wi pe tatoo naa dara, amọ ko yẹ ko ya a si ẹyin ara rẹ gẹgẹ bi abileko. Igba akọkọ kọ ni yii ti awọn eniyan ti ma n ya aworan gbajugbaja eniyan si ara wọn. Egbejila Fish Village: Àwọn ọlọ́sìn ẹja ní àwọn fi iṣẹ́ báńkì sílẹ̀ wá ṣe ọ̀sìn ẹja ni Laipẹ yii ni ọmọ Naijiria ọkunrin ti o ma n mura bi obinrin, Bobrisky fun awọn ololufẹ rẹ ni ẹbun nitori wọn ya tatoo rẹ si ara wọn.",0,yoruba "Ẹ kú làákàyè o jàre, b'ó ṣe jẹ́ gẹ́lẹ́ nù n. @user @user @user @user @user @user @user @user",0,yoruba "Akọwe Toyin Ajamu pẹlu Ijapa Ogbomoso Gẹgẹ bí awọn akọṣẹmọṣẹ atawọn onimọ nipa itọju ẹranko ṣe sọ ọ, aaringbugbun gbekede ti ijapa n lo laye ni aadọjọ ọdun bẹẹ si ni eyi ti eeyan ti ri ri to ju bẹẹ lọ ṣaaju ti Alagba ni o lo Igba ọdun laye. Ẹwẹ, Alagba ṣe o lo odidi ọdun mejilelọọdunrun loke eepẹ ko to faye silẹ. Lara ohun ti ẹ ko mọ nipa oloogbe ijapa to wa lafin Ṣọun Ogbomoso ree. Agba Inaki n ṣe'daro Alagba Ogbologbo ijapa l'aafin Sọun Imam tó ṣí Mọ́ṣálásì fáwọn Krístẹ́nì sọ ìdí tí kò fi lè ta wọ́n nù Àwọn àrídájú 'ọ̀rọ̀ yìí wá látẹ́nu akọ̀wé àgbà Toyin Ajamu ní ààfin Kábíyèsí Ṣọun ti ilu Ogbomosho fún BBC Yorùbá.",0,yoruba Kukuru bilisi. Emo wo ilu Ado Ekiti Gomina lola @user ya igbaju gbigbona lu adajo ni Kotuu. Fayose wipe ohun ba adajo da apara ni..,0,yoruba ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó ga.,0,yoruba nipa aabo ailewu ti awọn kokoro ti o le jẹun titi di bayi a ko ti ri boya spp tabi ati awọn kii kekere ti itumọ nipa google tumọ si laisi ẹri,0,yoruba ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìṣẹ̀: ti o nuni ti o wulo.,0,yoruba "Abilekọ Ọlayẹmi James Adeṣemọwọ gba pe òun kò ni wo telemundo ati Zee world ti òun fẹran julọ lasiko ìdíje ife ẹyẹ agbaye. Oun ati awọn ọmọ rẹ mẹtẹẹta ni wọn ti yọnda ohun èèlo ti a fi n dari eto ti a n wo lori amohunmaworan, rìmóòtù, ile wọn fún ọkọ rẹ̀ lati fi wo idije World Cup 2018 to n lọ lọwọ ni Russia. Awọn ọmọ rẹ naa, Gabriella, Mark ati Simon, ni àwọn kò ni wo 'Cartoon' ati 'PJ max' ti awọn fẹran julọ ki baba wọn, Ọgbẹni James le ṣatilẹyin to yẹ fun Super Eagles. Ọgbẹni James to jẹ baale ile ọhun ni oun féran lati maa gbọ iroyin ati lati maa wo bọọlu ni eyi ti awọn to ku kò fẹran ṣugbọn inu oun dun pe ẹbi oun ti gbagbọ ninu Naijiria pe, Super Eagles a de ipele keji to kangun si aṣekagba ni Russia.",0,yoruba Omo Kerubu 👉 Yorùbátv ẸGBẸ ỌMỌ OLÚWA BÍ GBOGBO ÀGBÁYÉ Ojú òpó ìkànsíraẹni 🇳🇬🇹🇬🇧🇯🇧🇷🇨🇴🇨🇺🇬🇭🇨🇮______________________________□ Yoruba TV 🥰😘🔥 #yoruba #yorubatv #yorubaweddings #ebi #asoebi #nigerianwedding #hausa #igbo… https://t.co/DeuZtayG1Y,0,yoruba ìkòkò wey ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó wáyé..,0,yoruba "RT @user: Iyen maa le die o! ☹ """"""""""""""""@user: Kini + 1 ni Yoruba? RT @user: Ah! Omi sì fẹ́ẹ̀ẹ́ má bọ́ lójú olúwa rẹ̀ :') ...",0,yoruba "Iroyin taa gbọ́ ni wipe ile ẹjọ ilu PortHarcourt ti dajọ iku nipa yiyẹgi fun afurasi apaayan, Gracious David West ti wọn ni o n pa awọn obinrin kaakiri ilu PortHacourt ti ọwọ si tẹ ni nkan bii oṣu melo sẹyin. Ẹsun ipaniyan ọdọbínrin mẹsan an kaakiri awọn ile itura niluu Port Harcourt ni wọn fi kan David-West ti adajọ to da ẹjọ rẹ, Adolphus Enebeli ṣe fi lede. Afurasi mii ti orukọ rẹ n jẹ Nimi Thankgod, oun naa gba idajọ lori ẹsun pe o tabuku oku eeyan. Igbẹjọ naa ti n lọ fun bi ọdun kan lẹyin tawọn eeyan bẹrẹ si ni ri oku awọn ọdọbinrin kaakiri ile itura niluu Portharcourt, ọna kan naa si ni gbogbo wọn n gba ku. Awọn ọdọbínrin mẹsan an ti afurasi David-West ṣekupa niyii: 1. Maureen Ewuru l'ọgbọnjọ oṣu keje, 2019 nile itura Hotel D/Line. 2. Wọn ri oku Jennifer Nkwocha ni Venice Hotel GRA Phase 2, Port Harcourt lọjọ kẹrinla oṣu kẹjọ ọdun 2019. 3. Ni Toki Hotel Port Harcourt wọn ti ri oku Blessing Effiong. 4. Linda Waripa ku si Avery Guest House, Oyigbo lọjọ kẹfa oṣu kẹsan an, 2019 ni Port Harcourt. 5. Dorcas Francis ni wọn rí oku tiẹ ni Imperial Hotel Trans Amadi, Port Harcourt lọjọ kẹsan an oṣu kẹsan an ọdun 2019. 6. Wọn ri oku Rose Samuel ni Lasus Steve Hotel ni Omoku lọjọ kejila oṣu kẹsan an ọdun 2019. 7. Kelechi Bridget Onuoha ku si Pachik Hotel lọjọ kẹtala oṣu kẹsan an ọdun 2019. 8. Lọjọ kejidinlogun oṣu kẹsan an ọdun 2019 ni won ri oku Patience Hamo ni Torox Guest House ni Port Harcourt. 9. Anthonia Ibe ku si TM Hotel Wimpey Port Harcourt. Benita Etim nikan lo mori bọ. Ọga ọlọpaa ipinlẹ Rivers lasiko naa, Dandaura ṣalaye pe yatọ si awọn obinrin mẹsan an yii, David-West tun jẹwọ pe oun tun ṣekupa obinrin kan niluu Eko, ọkan ni Owerri, omiran ni Sapele, ọkan ni ilu Aba, ọkan ni Benin ati ọkan ni ilu Ibadan. Pẹlu mẹsan an niluu Port Harcourt, obinrin mẹẹdogun lo jẹ lapapọ ti afurasi naa sọ dero ọrun alakeji. ''Ẹ gbudọ̀ ṣe àwọn ǹkan wọ̀nyí lọ́jọ́ ìdìbò gómìnà l'Ondo bí bẹ́ẹ̀ kọ́ ...'",0,yoruba "Awọn ọlọpaa ni awọn yoo bẹrẹ iwadii lori iku rẹ Amọṣa awọn ẹni ibi bẹẹ wo pẹlu iku lẹyin bii oṣu mẹta to gunlẹ si ilu Ikorodu nibi to n gbe. Iroyin sọ pe ile igbafẹ Island club ni alagba naa ti de nibi to ti lọ ba awọn ọrẹ rẹ ṣe faaji lawọn eeyan kan ti wọn fura si gẹgẹ bi agbenipa kọ luu. Wọn ṣaa si wẹlẹwẹlẹ lẹyin ti wọn yinbọn fun un, wọn si gbe oku rẹ sọ sinu ọkọ kan ki wọn to dana sun un. Mobile App: Àsìkò tó wu àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ni olùkọ́ máa jáde wa kọ́ wọn láti inú fóònù wọn Ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn ti mu ẹṣọ ile oloogbe naa to wa ni Ginti Estate, lagbegbe Ijede, ni Ikorodu. Atẹjade kan ti ileeṣẹ ọlọpaa fi sita ṣalaye pe Kọmiṣọnna ọlọpaa ni ipinlẹ Eko, Hakeem Odumoṣu ti paṣẹ iwadii to jinlẹ si iṣẹlẹ naa. Africa Eye: Ohun tí ọ̀rẹ́ mi fí sórí 'Social Media'ló wọ̀ mí lójú- Grace Gẹgẹ bi atẹjade ọlọpaa ṣe sọ, nnkan bii agogo meji abọ oru ni ọjọ Aiku, ni ẹṣọ naa ti orukọ rẹ n jẹ Rohis Adamu Dana de agọ ọlọpaa lati fi iṣẹlẹ naa to wọn leti. Gẹgẹ bi atẹjade ọhun tun ṣe fi sita, ẹṣọ oloogbe Agboṣaṣa ni nnkan bii agogo mẹwaa abọ ọjọ Satide, ọjọ kẹrinla, oṣu kejila toun ṣi geeti fun ọga oun lati wa ọkọ wọle ni awọn ọkunrin mẹrin kan ṣa deede ya wọ ọgba bi oun ti ṣe fẹ maa tii. Ondo disability day: Ijọba ẹ gbà wá ní ariwo tí àkàndá ẹ̀dá ń pa O ni pe ṣa deede ni oun gbọ ti ọga oun n pariwo si oun pe ki oun lọ pe awọn ọlọpaa. Mike Ifabunmi: Òrìṣà ló gbè wà jù ni Brazil",0,yoruba dídì. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé.,0,yoruba Ọba eléré bọ́ọ̀lù àti èmi: Àwọn ohun mánigbàgbé nípa akọni agbábọ́ọ̀lù,0,yoruba "Ilumọọka akọrin Tungba nni, Yinka Ayefele, ti sapejuwe iku gomina tẹ́lẹ̀ ni ipinlẹ Oyo, Otunba Adebayo Alao Akala, gẹgẹ bi adanu nla fun oun gẹgẹ bi ẹnikan ati idile oun. ""Ko si bi mo ṣe le kọ nipa itan igbesi aye mi laye ti mi o ni kọ nipa Otunba Adebayo Christopher Alao Akala"". Ninu atẹjade kan to fi sita, Ayefele sọ pe lara awọn oluranlọwọ kadara oun ni Alao Akala wa, to si tun jẹ ẹ̀bùn Ọlọrun fun ipinlẹ Oyo ati Naijiria lapapọ. Ọgbẹni Ayefele sọ pe oun dupẹ fun bi oloogbe naa ṣe ṣe atọna bi oun se n kọrin fun àwọn olokiki ati awọn eniyan nla, to fi mọ ileesẹ aarẹ, paapaa igbakeji aarẹ tẹlẹ, Atiku Abubakar ati awọn mii. Wo àwọn èèkàn mẹ́rin tí Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ pàdánù láàárín oṣù kan Ìrọ̀rùn dé! Yinka Ayefele le è dúró kọrin pẹ̀lú kẹ̀kẹ́ tuntun Bí Otunba Adebayo Alao Akala ṣe kú rèé, àti ibi tó dákẹ́ sí gangan - Amúgbálẹ́gbẹ́ Alao Akala Bí EFCC ṣe mú ayédèrú ọ̀gágun sọ́jà Bolarinwa tó tún ní ẹ̀sùn jìbìtì owó N270m Àjọ NDLEA tanná wòdí Cubana O ni ""ko si bi ma a ṣe kọ ìtàn igbe aye mi, ti mi o ni kọ ọpọlọpọ nkan nipa àwọn oore ti Otunba Alao Akala ṣe fun mi. O salaye pe Akala jẹ ẹnikan lara awọn ti Ọlọrun lò fun oun. Ati bi oun ṣe di aayo olorin fun Aso Rock, debi pe lati igba naa ni oun ti n kọrin fun ẹbi Atiku ni gbogbo igba ti wọn ba n ṣe ayẹyẹ. Bakan ni Ayefele sọ pe o ṣòro fun oun lati gbagbọ pe Akala ti ku. ""Afunni ma wo ibẹ ni, ti kii ní olódì."" Ayefele to ba ẹbi oloogbe kẹdun tun sọ pe titi lai ni iranti Alao Akala yoo wa ni ọkàn gbogbo àwọn to ran lọwọ. O.Y.O ni Tinubu wa o, a kò ní ṣ'àtìlẹ̀yìn fún un ní 2023 àyàfi ... - Afenifere, Ilana Omo Oodua Wo àwọn ọ̀rọ̀ táwọn ọmọ Naijiria fi kí Twitter kúàbọ̀ bí ìjọba ṣe gbẹ́sẹ̀ kúrò lórí rẹ̀ 'Mo mọ̀ pé ọmọ mi tí wọ́n ló pa ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ n mu igbó, ó sì ní àìsàn ọpọlọ' A tí ṣé tań láti díje fuń ipò ààre ní ọdún 2023",0,yoruba Yoruba movie: Kìí ṣe Iya Esabod tó fẹ máa fi wa pawo lóríi YouTube rẹ ló má máa da ẹgbẹ TAMPAN rú,0,yoruba ìwé orisirisi. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Bàbá lo ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "Iroyin naa ni ọkọ akẹru ọhun, ti nọnba rẹ jẹ XE331MKA lo ko ero bii mejidinlọgọta, to si n bọ lati ilu Sokoto wa si Ijẹbu Ode lasiko to rebọ sinu odo Ogun ni idaji kutu hai ana. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Gẹgẹ bi oludari fun ajọ ẹsọ oju popo, FRSC, ẹka tipinlẹ Ogun, Clement Oladele yi sọ fun awọn akọroyin, o seese ko jẹ pe o ti rẹ awọn arinrinajo naa dẹnu lo mu ki ijamba naa waye. ""Ni kete ti isẹlẹ yii to wa leti, lawọn osisẹ wa lati ẹka ti Ijẹbu Ode ati Ago Iwoye, yara lọ sibi ti isẹlẹ ọhun ti waye, ti wọn si ko awọn oku to fori sọta ijamba naa lọ sile igbokusi, nigba tawọn to farapa wa ni ile iwosan ijọba nilu Ijẹbu Ode."" Africa Eye: Ìrírí àwọn ọ̀dọ́bìnrin tó dágbà sójú pópó àti ìrètí wọn fún ọjọ́ ọ̀la Oladele wa rọ awọn ero lati maa rinrinajo pẹlu ọkọ ti wọn se fun ẹru kiko nikan nitori awọn ijoko wọn ko wa fun ijoko.",0,yoruba "Ọba Adéyẹmí gan sọ lọ́pọ̀ ìgbà pé ipò Àrẹ̀mọ yàtọ̀, tó sì se pàtàkì nínú ìlànà oyè jíjẹ ní ìlú Ọ̀yọ́. Àtẹ̀jáde kan tí àwọn aṣojú ìdílé náà, Azeez Ládìgbòlù, Moshood Agbábíàká, Matilda Gbádégẹṣin àti Adémọ́lá Adéládùn fọwọ́sí ní, èròǹgbà kíkọ́ pápá ìṣeré ìdáráyá náà, tí Akeem Adéyẹmí ní yóò ná òun tó mílíọ̀ọ̀nù márùúdínlọ́gọ́rin náírà, yóò pa gbàgede àwọn Àrẹ̀mọ tó jẹ́ ti àbáláyé rẹ́. Wọ́n wá ń rọ Ọba alayé náà láti pàrọwà fun ọmọ rẹ̀ lórí ìdí tí wọn ṣe dáàbò bo gbàgede Àrẹ̀mọ tó jẹ́ ti àbáláyé náà. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Gẹ́gẹ́ bí àtẹ̀jáde náà ti wí, "" Ẹniọ̀wọ̀ Samuel Johnson tíí se Òǹpìtàn ṣàlàyé pé ojúṣe àkọ́kọ́ tí ọba alayé náà gbọdọ̀ se ni kó ṣèdásílẹ̀ ipò Àrẹ̀mọ àti Ọmọọbabìnrin tàbí èyí tó fi ara pẹ́ẹ. Èyí tó túmọ̀ sí Àrólé e tìlú Ọ̀yọ́."" Ìdílé Ọba Agúnlóyè ń pe àkíyèsí ilé aṣòfin àpapọ̀ sí ọ̀rọ̀ náà ""Bákanáà ni Ọba Adéyẹmí ti sọ lọ́pọ̀ ìgbà pé ipò Àrẹ̀mọ yàtọ̀, tó sì ṣe pàtàkì nínú ìlànà oyè jíjẹ ní ìlú Ọ̀yọ́. Òun ni Àrẹ̀mọ Aláàfin, tí káà rẹ̀ sì wà nísàlẹ̀ Ààfin, ṣùgbọ́n ẹnu yà wá nígbàtí Akeem Adéyẹmí ń gbèrò láti wó káà náà."" Ìdílé Ọba Agúnlóyè wá ń pe àkíyèsí ilé aṣòfin àpapọ̀, ilé asòfin ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, iléesẹ́ tó wà fún ọ̀rọ̀ àsà àti Ọba Adéyẹmí láti tètè dásí ọ̀rọ̀ yìí, kí wọn tó yí ìtàn po.",0,yoruba "Ori ade naa waja lọjọ Iṣẹgun, ogunjọ, oṣu Kẹrin, ọdun 2021 ti a wa yii. Iroyin ti a gbọ sọ pe Kabiesi mi imi ikẹyin rẹ nile iwosan kan lẹyin aisan ranpẹ. Wọn bi Ọba Almoroof Adekunle Magbagbeola ni bi i ọdun 1950. Bo tilẹ jẹ pe ọmọ Yoruba ni, to si jẹ ọmọ Naijiria, orilẹ-ede Ghana ni wọn bii si, nitori pe ibẹ ni awọn obi rẹ fi ṣe ibugbe lasiko naa. Ọdun 1964 ni igba akọkọ to wa si orilẹ-ede Naijiria lẹyin ti iya agba rẹ sọ pe dandan ni fun un lati pada si Naijiria. Nitori naa si lo ṣe fi Ghana silẹ, to wa si ilu Oṣogbo lati ma a gbe pẹlu iya agba naa. Budo Ikoko water problem: Ìyàwó wa ti sá lọ kúrò ní Asa nítorí àìsí omi- Alhaji Sunmonu Ṣugbọn lẹyin to pari ileewe alakọbẹrẹ, Magbagbeọla sa pada si Ghana, nitori pe ko gbọ, bẹẹni ko le sọ ede Yoruba daadaa. Ede Ashanti ati Gẹẹsi lo mọ. Akomolede ati Aṣa lori BBC Yoruba: Ẹ̀yà Ara Ifọ̀ ní olùkọ́ Adedokun kọ́ wa Itan sọ pe awọn obi rẹ ni ile to pọ ni Ghana, ṣugbọn wọn fi gbogbo rẹ tọrẹ nigba ti wọn fẹ ẹ pada si Naijiria lọdun 1967 lasiko ti awọn alaṣẹ Ghana paṣẹ pe ki gbogbo ọmọ Naijiria to wa nibẹ pada si orilẹ-ede wọn. Idile marun-un lo maa n jẹ ọba ni ilu Ifon-Orolu, lara wọn ni Olumoyero ti Ọba Magbagbeọla ti wa. aaaaaaaaaaaaaaa Ọjọ kejidinlọgbọn, oṣu Karun-un, ọdun 2007 ni wọn fi jọba ilu Ifon nipinlẹ Ọṣun. Ṣugbọn ṣaaju asiko naa, oṣiṣẹ ajọ to n mojuto epo rọbi ni Naijiria, NNPC ni. Ipo alamojuto (supervisor) lo wa ni ẹka iṣakoso ileeṣẹ NNPC nilu Warri, nipinlẹ Delta. hhhhhh Ọdun mẹẹdọọgbọn lo fi ṣiṣẹ pẹlu NNPC. Yatọ si pe o jẹ ọba ilu Ifọn nipinlẹ Ọṣun, oun naa tun ni ọba ilu Ilobu ati Erin-Osun. Ẹwẹ, awọn abanikẹdun, ti ọpọ ninu wọn jẹ ọmọ ilu ti kabiesi naa jọba le lori nigabaye rẹ ti n korajọ si aafin rẹ lati ṣedaro. Adura wa ni pe ki Ọlọrun tẹ baba si afẹfẹ rere, ẹyin ti wọn fi silẹ ko si ni bajẹ. Yemi Farounbi: Yorùbá yóò dáàbò bo ara rẹ́, bí ìjọ́ba bá kùnà láti ràgà bò wọ́n",0,yoruba ọba ṣèyíówùú ọba tó jẹ́ pé o le ṣe ìhà ibìkan ní tútù kó ṣèmíì ní gbígbóná kábiíòsí o,0,yoruba "Yoruba ni iku kii jẹ ki a dagbere fun ẹnikeji ẹni, ko to maa mu ni lọ. Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu iku gbajumọ akọrin ẹmi nni, Tope Ajogbajesu, ẹni ti yoo wọ kaa ilẹ sun lonii. BBC Yoruba se abẹwo si ile oloogbe naa, nibi ta ti ba aya rẹ, ibeji rẹ ati awọn mọlẹbi rẹ miran sọrọ lori ipa ti iku rẹ yoo ni lara wọn. Aya oloogbe naa ni aisan ọgbẹ inu, taa mọ si Ulcer lo mu Tope ni oru Ọjọbọ, to si ku ni ọjọ Ẹti, bẹẹ lo yẹ ko gba ami ẹyẹ kan ni ọjọ Sunday. O ni aisan ọgbẹ inu naa ti n yọ ọkọ oun lẹnu, ọjọ ti pẹ amọ oun dupẹ pe inu ifẹ Kristi ni ọkọ oun ku si, ti ko si jẹ ki Jesu bọ lọwọ oun. Nigba toun naa n sọrọ, ikeji Tope Ajogbajesu ni oro ati ọgbẹ ọkan nla ni iku ẹnikeji oun fun oun nitori inu ifẹ nla ni awọn dijọ n gbe. Mọlẹbi kan wa salaye pe isin kan ti Tope lọ ni ọsẹ to ku lo ti n kọrin pe iku ọdun yii fo oun ru laimọ pe ọsẹ naa ni yoo ku.",0,yoruba agba to lomi ninu kan kii pariwo,0,yoruba "Ìjì tó jà tó kó aṣọ ní yàrá, ẹni tó wọ tiẹ̀ sọ́rù kó má ṣàfira o"""""""""""""""". Òwe àwọn àgbà Yoòbá ni. #BokoHaram",0,yoruba lẹ. Gbogbo àwọn ènìyàn wà ní ìṣẹ́ ọ̀pọ́lọ̀.,0,yoruba Baba Ijesha: Princess ní òjú gba òun tì fún Iya Rainbow,0,yoruba ó mà ṣe o àjànàkúu ti pa koríko orí papá ìṣerée,0,yoruba "Ara eni lo ni ọ̀gbọ́n. Ọba lo ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Nínú ọ̀rọ̀ - ọ rẹ̀ níbi ayẹyẹ Ọjọ́ Ìsinmi CAX 2018 ní Cario , ọ̀kọrin ọmọ orílẹ̀ - èdèe Nàìjíríà D'Banj sọ fún àwọn òṣìṣẹ́ Ilé - ìfowópamọ́sí àti olùdókoòwò :",0,yoruba Àkójú ọ̀rọ̀ yi kún fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "ìbadandun. Nitori eyi, ara eni lo ni ìgbà àkerekere ni nfàn ojú kakaaki.",0,yoruba "Kí ó tó rin ìrìnàjò lọ sí Canada ní ọmọ ọdún mọ́kànlá , Chemi Lhamo jẹ́ ẹni ogúnléndé tí kò rí ibùgbé kan gbé ní India .",0,yoruba "ìbàdandun láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba Odù yìí ń fi hàn wá ohun tí a lè ṣe kí ọmọ aráyé ó fi nífẹ̀ẹ́ wa. Ó dárúkọ ohun èlò tí a nílò láti ṣe ẹ̀yọ̀-inú ayé kí wọn ba fẹ́ 'ni. #Ife,0,yoruba "Ọrọ Serena Williams, agbabọọlu ẹlẹyin ori papa ati ilepa rẹ lati gba ife ẹyẹ idije lawn tennis Grandslam fun igba kẹrinlelogun tun ti dete. Wang Qiang, ọmọ orilẹede China lo bomi pana ala yii lẹẹkan sii nibi idije Australian Open to n lọ lọwọ. Serena Williams jẹ ọkan lara awọn odu elere idaraya Lawn Tennis ti itan agbaye ko lee gbagbe laye lẹyin awọn bẹbẹ loriṣiriṣi to ti gbe ṣe lere idaraya naa. Ẹ̀yin obìnrin tẹ́ẹ fẹ́ wá bímọ ní America, ọ̀nà ti tì pa látònì! - Trump Amọṣa, lẹyin to gba idije Australian open ni ọdun 2017, eyi to mu ki iye ife ẹyẹ grandslam to ti gba o jẹ mẹtalelogun lo ti n lepa ati gba ẹyọkan sii ko lee jẹ mẹrinlelogun ti yoo si sọ ọ di elere idaraya Lawn tennis to da gba ami ẹyẹ Lawn tennis to pọ julọ ninu itan lagbaye. Amọṣa, lati igba yii wa ni o ti n ba ijakulẹ pade. Lẹni ọdun mejidinlogoji, ireti ọpọ nigba ti idije Australian open ti ọdun 2020 bẹrẹ ni pe ilakaka Serena Williams yoo so eso rere ki o to di pe o pade Wang Qiang ọmọ orilẹede China ni ipele kẹta idije naa. Wang gbo ewuro soju Serena eleyi to jẹ ipele to ya ju ti Serena ti jabọ ni idije Lawn Tennis lati ọdun mẹrinla sẹyin ti o ti ja kulẹ ni ipele yii kan naa nigba to koju Daniela Hantuchova. Williams ti kọkọ fẹyin Wang gbolẹ ni idije US open ni osu kẹsan ọdun to kọja ki Wang to wa gba ẹsan rẹ bayii",0,yoruba ọ̀run dídì. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.,0,yoruba "ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba gbe ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa àwọn ènìyàn: ti o dun.,0,yoruba "Ìyá joko. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba "Ọ̀rọ̀ n bọ̀rọ̀ bọ̀ lori ase Buhari fawon gomina. Onimọ nipa ọrọ eto oṣelu ni Naijiria, Festus Adedayo ti ni ko tọna bi Aarẹ Buhari ṣe kesi awọn gomina lati dibo yan ẹni ti oun yoo fa silẹ lati rọpọ oun gẹgẹ bi aarẹ orilẹede Naijiria. Eyi ko ṣẹyin ipade ti Aarẹ Buhari ṣe pẹlu awọ̣n gomina lati inu ẹ̣gbẹ̣ oṣelu APC, pe ki wọn fun oun ni aaye ati ifọwọ̣sowọpọ pẹlu oun lati yan ẹni ti yoo gbe asia ẹgbẹ oselu naa ninu ẹto idibo abẹle ti o n bọ. Adedayo to jẹ onwoye oṣelu ni aarẹ Buhari sọrọ bi ẹni pe oye idile ni ipo aarẹ lorilẹede Naijiria, ti eniyan si le fa ẹni to ba wu u silẹ, o ni aarẹ ko lẹtọ lati ṣe eyi. ‘’Ṣe oye idilẹ ni aarẹ Buhari fẹ sọ oṣelu Naijiria da ni? Eto oṣelu tiwantiwa la n ṣe ni Naijiria kii ṣe ijọba ologun.’’ ‘’Ninu iṣẹ awọn ologun, nkan ti aarẹ ba sọ ni abẹ gẹ. Ni ti temi, aarẹ fẹ ka pada si ẹsẹ aarọ, nipa ti ologun’’ ’Aarẹ fẹ ṣe bi Ologun le awọn eniyan lori, eto oṣelu tiwantiwa ko si fi aye gba nkan ti aarẹ Buhari fe ̣se’’ ‘’Gbogbo awọn gomina ti aarẹ Buhari jọ ṣe ipade pẹlu, ko si ẹni to le gbena woju aarẹ ninu wọn.’’\n\n‘’Lerefe, o dabi ẹni pe aarẹ n rọ wọn ni, amọ ti a ba wo oro naa finifini,oun pase fun won ni. ‘’ Bakan naa ni onimọ nipa eto oṣelu naa bu ẹnu atẹ lu ọrọ ti Aarẹ sọ lati gboriyin fun iwa aitọ ti awọn gomina n sẹ ni ipinlẹ wọn. O ni iwa lati ma a yan ẹni ti o ba wu wọn lati rọpo wọn ti wọn ba kuro ni ipo ko dara to, to si ni nkan ti wọn n ṣe ni awọn ipinlẹ wọn naa ni oun fẹ sẹ.’’ ‘’Aarẹ fi ontẹ tẹ iṣẹ laabi ti awọn gomina n ṣe ni iṣakoso ipinlẹ wọn ni.’’ ‘’Awọn ti wọn fẹ di ipo mu ti bẹrẹ si ni na owo -nara, amọ ṣadede ni gomina ilu a sọ wipe ẹni bayii ni oun fẹ ti yoo si jẹ ẹni ti yoo ba wọn fi ọwọ bo gbogbo kudiẹ-kudiẹ iṣejọba wọn ni.’’ Onimọ nipa eto oṣelu naa wa fikun un pe ohun ti awọn eniyan kan n sọ ni pe aarẹ fẹ bu omi tutu si ọkan awọn eniyan. O ni pe eyi ko seyin nitori ẹni to fẹ ko jẹ aarẹ kii ṣe ẹni ti awọn gomina fẹran, to si dabi ẹni pe aarẹ fẹ fi ontẹ lu ẹni naa.",0,yoruba Ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn iléeṣẹ́ ìròyìn ni wọ́n ti jábọ̀ lórí àwọn ìkọlù yìí ṣùgbọ́n kò tilẹ̀ wu àwọn ìjọba láti sọ̀rọ̀ lé e tàbí kí wọ́n fi ìdí àrídájú ẹ̀rí múlẹ̀ nínú àwọn ọ̀rọ̀ yìí .,0,yoruba "Ninu ifọrọwerọ pẹlu agbẹnusọ ajọ naa, Fabian Benjamine, o ni JAMB ṣi n ṣe awọn eto kan lọwọ eyii ti ko jẹ ko ṣeeṣẹ lati bẹrẹ iforukọsilẹ naa lọjọ kẹjọ. Gẹgẹ bo ṣe sọ fun BBC, ""ohun ti a ṣe ni pe, a gbero lati bẹrẹ iforukọsilẹ naa lọjọ kẹjọ, oṣu Kẹrin, ṣugbọn kii ṣe ikede ti a fi sita niyẹn."" Benjamine sọ pe ikede ti wọn ba fi lede nikan lo le sọ ni pato akoko ti iforukọsilẹ ọhun yoo bẹrẹ. O fikun pe awọn n ṣe awọn eto kan lọwọ ti yoo mu ki iforukọsilẹ naa rọrun, awọn ko si tii pari rẹ. Alukoro ajọ naa ṣo siwaju si pe lara awọn eto tuntun ti wọn ṣẹṣẹ fi kun iforukọsilẹ naa ni nọmba idanimọ NIN. Torí àti ṣe Kòkò irin, bí mo ṣe máa ǹ fara yá iná nìyìí - Amokoko Saki O ṣalaye pe nọmba idanimọ NIN ọhun yoo mu ko rọrun fun awọn lati gba awọn alaye nipa awọn to fẹ ṣe idanwo naa lọwọ ijọba apapọ O ni idi ree ti wọn ko tii ṣe bẹrẹ iforukọsilẹ naa, ki awọn to fẹ forukọsilẹ ma baa maa sa kiri nitori ọrọ NIN. Nigba ti akọroyin BBC bere akoko ti iforukọsilẹ naa yoo bẹrẹ ni pato, o fesi pe ""ọsẹ to n bọ ṣe pataki, ko si ohun ti yoo di wa lọwọ lati ma bẹrẹ lọsẹ to n bọ."" 'Bí ojú ọ̀nà agbàrá òjò tí ijọba ṣe n'IIorin ṣe ń pa àwọn ọmọ iléèwé wa rèé! Ẹ sàánú wa'",0,yoruba "Nínú eré wo ni fọ́nrán yìí wà. #TundeKelani #Yoruba #Nàìjíríà #Ibile #Saworoide #ÈdèYorùbárẹwà @user Birmingham, United Kingdom https://t.co/MYc7JrRgCd",0,yoruba "Obì máa ń ní akọ àti abo, bí a bá pa awẹ́ obì a óò rí 'yàtọ̀. #Obi #Yoruba",0,yoruba iṣẹ́ ṣẹlẹ ni Lagos ti gbogbo eniyan sọ o ṣe pataki. (2014),0,yoruba "kọ. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba nípa ẹkọ́: ti o nuni ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tó gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ àti ìbi tí wọn wà.,0,yoruba ejo se oluko yooba ni yin ni,0,yoruba "Ọmọ lo ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "nígbà àkerekere, Ìyá ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa òkè: ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó wáyé..",0,yoruba RT @user: @user E karo o! E ji re bi? Olorun maje a baraiye fowo tii! Ka waiye ka jeniyan lo sunwon!,0,yoruba "Iṣọ́ẹ̀ ìṣẹ́ ni a ní nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà.",0,yoruba "Wọn kilọ pe àwọn kò ní fi àyè sílẹ̀ fún òṣèrè tíátà kankan láti dójú ti ẹgbẹ́ mọ. Ede aiyede laarin awọn oṣere mejeeji yii bẹrẹ nigba ti iroyin jade sita pe Toyin Abraham to ṣẹṣẹ bimọ laipẹ yii kọ lẹta ipẹjọ si Lizzy eleyi to mu ki Lizzy pẹlu gbana jẹ. Lẹyin eyi ni ọrọ naa wa di fa-ki-n-fa laarin awọn mejeeji. Lẹyin ọpọ awuyewuye, ipẹtu si alaafia laarin awọn mejeeji, ti o si jẹ pe kaka ki ewe agbọn ọrọ naa dẹ, lile lo tun n le sii, awọn alaṣẹ ẹgbẹ oṣere tiata Yoruba ti wa paroko ""Ẹ sinmẹdọ ranṣẹ si awọn mejeeji atawọn oṣere miran ti wọn ba ni iru rẹ lọwọ tabi lọkan. Ninu fọnran fidio kan ti wọn fi sita, aarẹ ẹgbẹ oṣere tiata Yoruba Ọgbẹni Bọlaji Amuṣan ati ọkan lara awọn agba ọjẹ ninu ere tiata lorilẹede Naijiria, Alhaji Yinka Quadri ti ti paṣẹ ki gbogbo awọn mejeeji lọ ree gbẹnu dakẹ tabi ki wọn fi kele ẹgbẹ gbe wọn. Nibayii awọn ololufẹ awọn oṣere tiata mejeeji ti n kan sara si igbesẹ naa eleyi ti wọn ni o tọna lati mu alaafia ati irẹpọ jọba laarin ẹgbẹ naa.",0,yoruba rere lojiji. Ìyá lo ni ẹ̀ká àwẹ eyti o gbe lori àìmọ́ kọ.,0,yoruba "Ọba fè fi, A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..",0,yoruba "Oloye Ìdòwú Olukunle so pe babalawo lo le mo òun ti ọ̀sándòru yóò já sí fun ara ilu. Lasiko to ba n sẹlẹ, ojú òrun yoo pawọ dá ti awọ òṣùpá yóò sì ṣadede di pupa bí awọ ẹjẹ. Ìṣẹlẹ yí tí awon oloyinbo n pe ni 'blood moon' yóò wáyé fún nnkán bi wakati kan ati ogójì iṣẹju le diẹ. Àlàyé tí awọn onimo sayensi ṣe nipa iṣele naa ni wipe òṣùpá yóò gbà arin ojiji orilẹ ayé ta wa yi ati òrun koja,ojiji ti orun ba tàn sara òṣùpá ni yóò mú kí awọ rẹ pupa bí ẹjẹ. Òun tí ifá sọ 'Irú ìṣẹlẹ bayi ki ṣéé túntún nilẹ Yoruba, kò ṣèṣe má wáyé.'' Ọrọ rẹ láti ẹnu Oloye Ìdòwú Olukunle ti ọ jẹ akoda awo ti ìjọba ibilẹ ọnà ará nílu Ibadan nigba ti wọn se alaye fún ilé iṣẹ BBC nipa ìṣẹlẹ òṣùpádeje tí yóò wáyé loní. Ọ̀ṣùpádẹ̀jẹ̀ O ni awọn onimo sayẹnsi le mọ nípa ọjọ ti iru ìṣẹlẹ yí yóò wáyé ṣugbọn ''Babalawo lo le mo òun ti yóò gbẹyin rẹ.' Fun ìdí èyí o so pe ''o yẹ kí àwọn aláṣẹ kesi Babalawo lati sọ 'boya ire ni yóò já sí ní tàbí ibi fun ara ilu' Bakanaa ni alagba Ìdòwú ṣàlàyé pé ètùtù ní í gbẹyin irú ìṣẹlẹ bayii sugbọn pẹlu bi nnkan ti se ri lode oni, awọn eeyan ko ka ọrọ etutu sise kun mọ Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí: Anfani de fun ọ lati lo internet lọfẹ 'Ọ̀jẹ̀lú ni àwọn tó ń fi APC sílẹ̀ fún PDP' Níbo gaan ni Òṣùpádẹ̀jẹ̀ yóò ti ṣẹlẹ̀ lágbàyé? Àwọn ibi tí ọ̀sándòru yìí yóò ti wáye ni Europe, ààrin gbùngbùn Ìlà Oòrùn, Africa, Australia Asia, South America àti ní UK láti nkan bíi agogo mẹ́sàán sí mẹ́wàá kọjá ìṣẹ́jú mẹ́ẹ̀dógún alẹ́ káàkiri. Lálẹ́ yii kan náà àt'àwọn ọjọ́ tó tẹ̀lé e ni yóò jẹ́ ìgbà tí Mars yóò sún mọ́ ayé jù láti ọdún 2003 tí yóò sì mọ́lẹ̀ bí ìràwọ̀ pupa níbi tí ojú ọ̀run ti mọ́. Àwòrán bí Ọ̀ṣùpádẹ̀jẹ̀ yóò ṣe wáyé Kí ló dé tí ìṣẹ̀lẹ̀ ọ̀ṣùpádẹ̀jẹ̀ náà yóò pẹ́? Òṣùpá yóò la àárin òjiji ayé kọjá lọ́gángán ibi tí òjiji náà ti fẹ̀ jù. Òṣùpá yóò fara hàn pẹ̀lú àwọ̀ pupa nínú ọ̀ṣùpádẹ̀jẹ̀ náà gẹ́gẹ́ bí ìtànsán oòrùn yóò ṣe gba inú ayé kọjá fẹ́ẹ́rẹ́fẹ́. Ọ̀jọ̀gbọ́n Tim O'Brien ti ilé ìwé gíga fásitì Manchester sàlàyé pé eléyìí ni yóò jẹ́ ìṣẹ̀lẹ̀ ọ̀ṣùpádẹ̀jẹ̀ tó gùn jù ní ọ̀ọ̀rùndúnrún yìí. Ìṣẹ́lẹ̀ ọ̀sándòru ní Montevideo, Uruguay, ọdún 2014 Bákan náà, kò kàn ṣe kòńgẹ́ bí Mars yóò ṣe súnmọ́ ayé nìkan sùgbọ́n yóò jẹ́ pẹ̀lúu ohun tí ọ̀jọ̀gbọ́n ṣàpèjúwe gẹ́gẹ́ bí títòjáde àwọ́n òfurufú òkè tí wọ́n jẹ́ amúgbálẹ́gbẹ̀ẹ́ òde ayé. Èyí ni yóò jẹ́ ànfàni fún àwọ́n awòràwọ̀ láti rí Venus, Jupiter, Saturn àti Mars dáadáa.",0,yoruba "Bi o tilẹ jẹ pe Gotabaya Rajapaksa ti ni oun loun jawe olubori ti ẹni to jẹ alatako rẹ naa ti gba bẹẹ ṣugbọn wọn ko tii gbe esi gangan jade. Idibo yii ni yoo jẹ igba akọkọ ti yoo waye lẹyin ikọlu nla kan to waye to si mu ẹmi eeyan to le ni igba le ni aadọta lọ ninu oṣu kẹrin ọdun yii. Oludije marundinlogoji lo du ipo aarẹ orilẹede naa eyi ti yoo jẹ aarẹ kẹta lati ọdun 2009 ti opin ti de si ogun abẹle ọlọdun gbọọrọ to n waye lorilẹede naa. Ọgbẹni Rajapaksa jẹ odu ti ko ṣee fọwọ rọ sẹyin to si jẹ ọkan lara awọn erin meji to n sare ije ipo aarẹ yii pẹlu minisita kan Sajith Premadasa. 'Àwa akódọ̀tí táà ń gba £1,500 lóṣù níbi sàn ju Sẹ́nétọ̀ lọ ní Nàìjíríà' Orukọ aarẹ to wa lori alefa bayii ko si lori iwe orukọ awọn oludije tori o pinnu lati ma dije lẹyin awọn ọrọ to jade si i latari iṣẹlẹ ado oloro to bugbamu lọjọ ọdun ajinde. Awọn alakatakiti ẹsin Islam doju kọ awọn ile ijọsin atawọn ile itura kaakiri orilẹede naa. Koda ikọlu yii ti mu ki ọrọ aje orilẹede naa wọkun to fi mọ ẹka igbafẹ. Ki la mọ nipa esi idibo naa Awọn oṣiṣẹ ajọ eleto idibo ni ida ọgọrin ninu ọgọrun oludibo lo jade wa dibo. Ọgbẹni Premadasa ni ida marundinlaadọta o le diẹ (45.3%) nigba ti Ọgbẹni Rajapaksa ni ida mejidinlaadọta o le diẹ (48.2%) Rajapaksa si ni oun yoo bori. ""Mo ni anfani lati gboriyin fun ipinu awọn araalu mo si ki Ọgbẹni Gotabaya Rajapaksa ku oriire idibo yii gẹgẹ bi aarẹ ikeeje Sri Lanka"". Ọgbẹni Premadasa sọ gẹgẹ bi ileeṣẹ iroyin AFP ṣe jabọ rẹ. Ajọ eleto idibo orilẹede naa sọ fun BBC pe esi idibo to tọ yoo jade ni aago mẹrin ti ilu wọn (aago mẹwa abọ lagbaye) lọjọ aje. 'Olùkọ̀ rẹ̀ tilẹ̀ sọ fún un pé ""ẹlẹ́sẹ̀ kan ni ẹ́, oò ní 'le wẹ̀'",0,yoruba "ojú òní.. Nitori eyi, ara eni lo ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba eni lo ni ẹ̀ká àwẹ eyti o gbe lori ọ̀run dídì.,0,yoruba "iṣẹ́ ayin. Nitori eyi, ara eni lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..",0,yoruba Àì lè jà ló ń jẹ 'Ìta baba mi ò dé bi'. Ọ̀lẹ lásán-làsàn ni FCMB ó jàre. #SterlingBank #BankWars #Yoruba https://t.co/k4SYjRvKJ6,0,yoruba "Aarẹ Muhammadu Buhari si tun tu igbimọ oludari ẹgbẹ naa ka, nibi ipade pajawiri naa to waye nile Aarẹ. Igbimọ oludari naa lo da Adams Oshiomole duro gẹgẹ bi alaga ẹgbẹ. Buhari si fi igbimọ ẹlẹni mẹtala rọpo wọn, to si jẹ pe gomina ipinlẹ Yobe, Mai Mala Buni ni alaga wọn. Awuyewuye ati arinyanjiyan oriṣiriṣi lo si ti n waye lori awọn ti ẹgbẹ oṣelu APC, ṣẹṣẹ yan sipo adari ẹgbẹ. Awọn ọmọ igbimọ oluṣakoso ẹgbẹ tẹlẹ sọ pe nkan ti aarẹ ṣe ko ba ofin mu. Awọn mejidinlogun naa, ti Hilliard Eta n dari, jẹ alatilẹyin Adams Oshiomole ti wọn yọ nipo alaga. Wọn si fẹnuko pe ipade igbimọ alaṣẹ ti ẹgbẹ ṣe lọjọ ẹti ko ba ofin mu. Wọn ni Alaga Apapọ ati awọn ọmọ igbimọ oludari nikan lo lẹtọ lati pe iru ipade bẹ ẹ. Wọn si tun gbọdọ fi ikede sita lọjọ mẹrinla ṣaaju ọjọ ipade, tabi ọjọ meje, to ba jẹ pajawiri ni. Pẹlu ikunsinu wọn yii, o ṣeeṣe ki wọn o lọ sile ẹjọ. Eyi lo mu ki a ṣe akọsilẹ diẹ lara ipenija to ṣeeṣe ki igbimọ tuntun yii koju. Aworan lati ibi ipade igbimọ oludari ẹgbẹ oṣelu APC to waye lọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu Kẹfa, ori ayelujara si ni awọn kan ti ko pa Ṣe ilaja laarin awọn ọmọ ẹgbẹ to n binu Ọkan lara ipenija to wa nilẹ fun awọn olori ẹgẹ naa lasiko yii ni lati pari ija to wa laarin awọn ọmọ ẹgbẹ, ki ọrs to de ile ẹjọ. Nitori o ṣeeṣe ki iru awọn aawọ bẹ ni ipa ti ko tọ lara ẹgbẹ naa ninu idibo gomina ipinlẹ Edo. Iṣọkan ẹgbẹ Ajeje ọwọ kan ko gbẹru d'ori, agbajọws la fi n sọya. Ireti ati iwoye ọpọ eeyan ni pe ki awọn olori tuntun yii o wa ọna ti wọn yoo fi fa awọn ọmọ ẹgbẹ wọn bi miliọnu mẹrindinlogun mọra. Awọn onimọ kan nipa oṣelu ti ẹ sọ pe awọn olori tuntun naa gbọds bẹrẹ ijiroro pẹlu awọn adari ẹgbẹ ni gbogbo ipinlẹ, lati wa ọna ti iṣọkan yoo gba pada sinu ẹgbẹ. Wọn ni eyi yoo le dena ki APC o ma ni iriri ohun to ṣe PDP l'ọdun 2015. Aṣeyọri ninu eto idibo Edo ati Ondo Nkan pataki ti igbimọ alamojuto tuntun naa gbọdọ mojuto ni ipalẹmọ fun idibo gomina ipinlẹ Edo ati Ondo. Wọn gbọdọ ṣe eto ati ilana to le mu ki ẹgbẹ wọn o bori. Eyi gbọdọ waye, paapa ni ipinlẹ Edo, nibi ti wahala ti waye lori idibo abẹnu wọn. Gomina Godwin Obaseki ti wọn ko fun ni tikẹẹti, ti darapọ mọ ẹgbẹ PDP, yoo si fẹ ẹ nira lati gba ipo naa lọwọ rẹ. Nipinlẹ Ondo, igun meji lo wa ninu ẹgbẹ APC. Ija si ti n waye ni olu ile ẹgbẹ, to si ṣe eṣe ko ni ipa lori ẹni tio yoo ṣoju ẹgbẹ. Ọjọ kọkandinlogun, oṣu Kẹsan, ati ọjọ kẹwa, oṣu Kẹwa, ọdun 2020, ni idibo mejeeji yoo waye. Tun orukọ ẹgbẹ naa ṣe l'oju awọn ọmọ Naijiria Lati bi ọdun melo kan, ni awọn ọmọ Naijiria lo da bi ẹni pe orukọ ẹgbẹ naa ati awọn olori ẹgbẹ APC, ti n dibajẹ lọkan awọn ọmọ Naijiria. Eyi ko ṣẹyin bi ọpọ ṣe ni wọn ko mu ileri ti wọn ṣe lasiko ipolongo ibo ṣẹ. Nitori naa, awọn olori tuntun naa gbọdọ tun orukọ naa ṣe. Ki wọn o si ri pe awọn gomina, ati awọn miran ti wọn dibo yan ninu ẹgbẹ naa n ṣe daada fun araalu. Ipagọ ẹgbẹ to ni akoyawọ Nkan miran ti igbimọ oludari ẹgbẹ APC tun gbọdọ mojuto ni ṣiṣe ipagọ/ipade ẹgbẹ, ti ko ni mago-mago ninu. Ọna ti wọn ba gbe e gba ni yoo sọ boya ẹgbẹ naa yoo duro, paapa iru awọn eeyan ti wọn ba fun ni tikẹẹti ẹgbẹ lati dije dupo. Nibi ipade kan to waye ni ile Aarẹ ni Abuja ni Aare Muhammadu Buhari ti tu Igbimọ Amuṣẹya ẹgbẹ oselu APC ka. Tinubu, oju ti ẹ, o ta ilẹ Yoruba fun ọta rẹ nitori adanikanjẹ- Femi Fani-Kayode Oloselu Femi Fani Kayode ti kọ lẹta ranṣe si Asiwaju Bola Ahmed Tinubu lẹyin ti Aarẹ Muhammadu Buhari yan Alaga fidiẹ tuntun fun ẹgbẹ oṣelu APC. Oloṣelu ni ẹgbẹ oṣelu PDP, Femi Fani-Kayode ti fi lẹta itagbangba ranṣẹ si Asiwaju Bola Ahmed Tinubu lori igbesẹ Aarẹ Buhari to yan gomina ipinlẹ Yobẹ gẹgẹ bi Alaga fidiẹ fun ẹgbẹ oṣelu APC. Fani Kayode ninu lẹta naa ni bi oun ṣe fẹran tilẹ jẹ iwa rẹ lo mu ki oun sa fun un nitori imọtara ẹni nikan n ba ja. O ni Aarẹ Buhari to fi ṣe ọrẹ ti sọ di ọta, ti gbogbo ero rẹ lori ẹgbẹ oṣelu APC si ti jasi pabo. Femi Fani Kayode ni bi o tilẹ jẹ pe Asiwaju ti gbekele ara rẹ wi pe oun ko le e ṣi ṣe, ọrọ yii ti ba ẹyin yọ pẹlu bu Aarẹ Buhari ṣe pada lẹyin rẹ, ti wọn si ri pe ko ni ipo kankan mọ ninu ẹgbẹ oṣelu APC. 'Tinubu ta ẹmi rẹ, ta ọkan rẹ, to si ta gbogbo ilẹ Yoruba, to fi mọ Guusu ati Ariwa orilẹede Naijiria lati le ri wi pe oun mu gbogbo ero ọkan rẹ to kun fun ibi ṣẹ. O fikun wi pe gbogbo ilakaka rẹ lati jẹ aarẹ orilẹede Naijiria ni ọdun 2015, 2019 ati 2023 lo ti ja si pabo bayii. Bakan naa lo ni kaka ki Tinubu o ba aarẹ Buhari sọrọ lati wuwa rẹrẹ si awọn ọmọ Naijiria, ki iya ma ba jẹ wọn, niṣe ni Asiwaju n gbe lẹyin Buhari, ẹni to wa jakulẹ bayii. Ọrọ ipari rẹ ninu lẹta naa ni wi pe o ti tan fun Tinubu ninu oṣelu orilẹede Naijiria, oun ti o ku ni ki o lọ rọkun nile, ki o si ma a sinmi. O gba ni adura pe lasiko ifẹyinti Tinubu, ohun gbogbo to ti bajẹ lorilẹede Naijiria yoo gba atunṣe. Oyè adelé alága APC kúrò ní gúúṣù Nàíjíríà, ó bọ́ sẹ́kùn àríwá Gomina ipinlẹ Yobe, Mai Mala Buni ti di Alaga ẹgbẹ oṣelu APC tuntun ni Naijiria. Eyi ko ṣẹyin bi Aarẹ Muhammadu Buhari ṣe tu igbimọ amuṣẹya ẹgbẹ oselu APC ka, ti o si fi igbimọ fidiẹ sibẹ. Oluranlọwọ fun Aarẹ Buhari lori ọrọ iroyin, Bashir Ahmad lo fi ọrọ yii lede loju opo ikansiraẹni Twitter rẹ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Bakan naa ni wọn fikun pe, laipẹ ni wọn yoo fi kede ọjọ ti wọn too ṣe ipade apapọ ẹgbẹ. Bẹẹ ba gbagbe, Adams Oshiomole lati ẹkun guusu Naijiria ni alaga tẹlẹ fun ẹgbẹ oselu APC, ko to di pe ileẹjọ yẹ aga mọ nidii. Ireti ọpọ ọmọ ẹgb oselu naa si ni pe ẹkun guusu Naijiria ni wọn yoo pada ti yan alaga afunsọ fun ẹgbẹ oselu naa. Koda, ẹgbẹ APC ti kọkọ yan gomina ana nipinlẹ Oyo, Abiola Ajimobi gẹ́gẹ bii adele Alaga ẹgbẹ, amọ Ọjọru ni wọn tun yan Geidom rọpo rẹ. Ibeere ti ọpọ eeyan wa n beere ni pe ki ni yoo jẹ ireti awọn ọmọ ẹgbẹ APC lẹkun guusu Naijiria ni bayii ti alaga afunsọ ẹgbẹ APC tun ti lọ si ẹkun ariwa Naijiria? Bẹẹ ba si gbagbe, ẹkun ariwa Naijiria yii naa ni aarẹ Muhammadu Buhari ti wa. Ta ni Victor Giadom? Ọmọ ipinlẹ Rivers ni ẹkun Gusu-Gusu Naijiria ni Victor Giadom, ti wọn ṣẹṣẹ kede ni Adele Alaga ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC. Giadom ti jẹ kọmiṣọnna fun akanṣe iṣẹ ni ipinlẹ Rivers, lasiko ti Minisita fun eto irinna ni Naijiria, Rotimi Amaechi fi jẹ gomina ipinlẹ naa. Awọn alaṣẹ ẹgbẹ APC ni ipinlẹ Rivers ti kọkọ da Giadom duro, ""fun pe o tako ilana ati agbakalẹ ẹgbẹ"". O ti fi igba kan jẹ ọmọ igbimọ amuṣẹya ẹgbẹ APC, ko to fi ipo naa silẹ lati dije fun ipo igbakeji gomina ipinlẹ Rivers l'ọdun 2019. Sugbọn ipo naa ko jamọ oun ati Tonye Cole to fẹ ẹ di gomina lọwọ. Lẹyin naa lo tun pada si ipo to fi silẹ gẹgẹ bi Igbakeji Akọwe Apapọ ẹgbẹ. Ṣaaju ki wọn o to kede rẹ gẹgẹ bi adele alaga ẹgbẹ APC, Giadom ni igbakeji Akọwe Apapọ ẹgbẹ naa. Ṣugbọn, ẹgbẹ ti da a duro l'ẹnu iṣẹ rẹ tẹlẹ. Awọn alaṣẹ ẹgbẹ naa ni ipinlẹ Rivers lo da a duro, ""fun pe o tako ilana ati agbakalẹ ẹgbẹ"". Koda, ile ẹjọ giga kan nipinlẹ Rivers fi ofin de Giadom pe ko gbọdọ pe ara rẹ ni ọmọ ẹgbẹ tabi oloye ninu ẹgbẹ APC mọ. Ni kete ti ile ẹjọ kotẹmilọrun fi idi idaduro alaga ẹgbẹ APC tẹlẹ mulẹ ni Giadom ti kede ara re, Adams Oshiomole ni ile ẹjọ yọ l'ọsẹ to kọja ti Giadom si ni oun ni Adele Alaga ẹgbẹ ni kete ti. Igbesẹ rẹ lati rọpo Oshiomole ti bẹrẹ lati igba ti Oshiomole ti n koju wahala idaduro ninu ẹgbẹ nibẹrẹ ọdun 2020. Lẹyin eyi lo kọwe si ajọ eleto idibo, INEC, pe oun ti fagile eto idibo abẹle lati yan oludije fun ipo gomina ipinlẹ Edo. O ni ko ba ofin mu, nitori pe oun ko fi aṣẹ sii. Ọjọru si ni gbogbo awuyewuye to n waye lori ẹni ti yoo jẹ alaga fun ẹgbẹ oselu APC da bi pe o ti dopin. Idi ni pe Aarẹ Muhammadu Buhari ti kede pe ẹni to yẹ nipo igbakeji alaga fun ẹgbẹ oselu APC ni igbakeji alaga ẹgbẹ tẹlẹ, Victor Giadom. Wakati diẹ lẹyin ti Aarẹ Buhari fi atilẹyin rẹ fun Giadom han, ni Giadom kede pe ipade igbimọ amuṣẹya ati igbimọ alaṣẹ ẹgbẹ yoo waye lọjọbọ. Oun fun'ra rẹ lo fi ọwọ si atẹjade ikede ipade naa ti yoo waye lori ayelujara. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Bi ẹ ko ba gbagbe, ileẹjọ lo yọ alaga tẹlẹ fun ẹgbẹ oselu APC, Adams Oshiomọlẹ, ti igbimọ amusẹya ẹgbẹ si kede pe Senatọ Abiola Ajimobi ni ipo naa tọ si. Lati igba naa si ni ara ko rọ okun, ti ko si rọ adiẹ ninu ẹgbẹ oselu APC. Atẹjade kan ti agbẹnusọ fun Aarẹ Muhammadu Buhari, Garba Shehu fi sita loju opo Twitter rẹ lorukọ aarẹ orilẹ-ede yii lo sisọ loju ọrọ naa. Shehu ni aarẹ ti gba imọran to daju nipa ohun ti ofin ilẹ wa sọ lori awọn isẹlẹ to n waye ninu ẹgbẹ oselu APC, to si fara mọ pe ẹyin Victor Giadom ni ofin gbe si. ""Bakan naa, nitori pe aarẹ Buhari maa n wa lẹyin ofin, aarẹ yoo ba adele alaga tuntun naa se ipade lati ori ẹrọ ayelujara ni ọsan ọla."" Ileesẹ aarẹ wa rọ awọn akọroyin lati dẹkun dida awuyewuye silẹ, ki wọn ma si faaye gba sise itumọ ofin lọna odi lori ọrọ naa. Ọ̀pọ̀lọpọ̀ awuyewuye ló tí súyọ lẹ́yìn tí ẹgbẹ́ òṣèlú APC kéde Abiola Ajimobi gẹ́gẹ́bí igbákejì alága APC. Mí ò bẹ̀bẹ̀ fún oyè igbákejì alága APC kí wọ́n tó ó fún mi - Abiola Ajimobi Gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ, Abiola Ajimobi ti sọ pe awọn alaṣẹ ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC gbagbọ ninu oun ni wọn ṣe fi oun jẹ igbakẹji alaga ẹgbẹ naa. Ajimobi ni kii ṣe pe oun bẹbẹ fun ipo ọhun, ṣugbọn awọn alakoso APC ri oun gẹgẹ bi ẹni to ṣe e fọkan tan ni wọn ṣe fi oun si ipo naa ni iha guusu Naijiria. Nigba to n fesi si ọrọ ti awọn alatako rẹ lori ipo tuntun naa, Ajimobi sọ pe ẹgbẹ APC mọ iru atunṣe rere ti oun lee mu ba ẹgbẹ naa ni guusu Naijiria ati ni orilẹ-ede yii lapapọ. Ajimobi, ninu ọrọ naa to fi sita latẹnu agbẹnusọ rẹ, Bolaji Tunji, sọ pe awọn eniyan ipinlẹ Oyo ko le gbagbe ipa ribiribi ti oun ko lasiko iṣejọba bii Gomina ipinlẹ Oyo. O sọ pe nitori naa, ti awọn alaṣẹ ẹgbẹ APC ba lero pe oun ni ipo naa yẹ, ko si alatako to le e yi pada.",0,yoruba ẹni tó jí ò tíì yó ẹni tó sùn ní wọn ò jí òun jẹun the person awake is not satisfied yet the one asleep complain,0,yoruba Omoluabi wa ni ọlọ́run lo je ti ibile.,0,yoruba @user Ó dùn yùngbà. Ẹṣeun. Ẹ̀yin náà ńkọ́? Ṣé Abuja dùn? Ẹ ṣọ́ra fún #BokoHaram ooo :(,0,yoruba ọ̀rọ̀ yi kún fún àwọn ìkòkò tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà.,0,yoruba a yi gbe ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó.,0,yoruba "Ọmọge Campus jáde láyé ní orílẹ̀èdè Canada ní ààrọ̀ ọjọ́rú, wọn sì sín síbẹ̀. Gẹ̀gẹ̀ bí àtẹ̀jáde láti ọwọ́ ẹgbẹ́ Golden Movie Ambassadors of Nigeria, ìsìnkú náà ti wáyé ni agogo mẹ́jọ àbọ̀ alẹ́ ti orílẹ̀èdè Naijiria. Aisha Abimbọla, tí ọ̀pọ̀ èèyàn mọ̀ sí ‘Ọmọge Campus’ ló jáde láyé ní orílẹ̀èdè Canada ní ààrọ̀ ọjọ́rú. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Aisha ni ìròyìn gbalẹ̀ kan ní ààrọ̀ ọjọ́rú pé ó ti mí kanlẹ̀ lásìkò àìsàn ọlọ́jọ́ gbọọrọ. O digba A gbọ́ pé àìsàn jẹjẹrẹ ọyàn tó ń bá Aisha fínra láti ọjọ́ díẹ̀, ló gba ẹ̀mi rẹ̀. Ọ̀pọ̀ àwọn òsèré tíátà, tí wọn jẹ́ akẹẹgbẹ́ rẹ̀ ni wọ́n ń se ìdárò ikú ìlúmọ̀ọ́ká òsèrè tíátá obìnrin náà, láwọn ojú òpó ìkànsíra ẹni wọn lórí ìtàkùn àgbáyé Facebook àti Instagram.",0,yoruba "Ààrẹ ilé ìgbìms aṣofin ko lọ́wọ́ nini bi àó ṣe yan ààrẹ ilé ìgbìmọ̀ túntún Àwọn sẹnatọ ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú PDP, nínú àtẹjade kan tí olori ọmọ ilé tó kéré jùlọ, Abiodun Olujimi àti Sẹnatọ Dino Melaye fọwọ́si sọ pé, ki wọn yọ ṣenatọ Bukola Saraki kúrò nínú awuyewuye àti eto ti wọn fẹ́ lò, láti yan ààrẹ ilé ìgbìmọ̀ asòfin kẹsán. PDP ní gbogbo àwọn sẹnatọ àti ọmọ ile ìgbìmọ̀ aṣojú ṣofin ti wọn dibò yan ló lẹ́tọ̀ọ́, láti dari ile ìgbìmọ̀ aṣofin. Atẹjade àwọn asofin agba PDP yìí wáye nitori àwọn ìròyìn kán tó ń nàka sí ààrẹ ilé ìgbìmọ̀ aṣofin àgbà, sẹnatọ Bukola Saraki pé o ń pinnu láti lọ́wọ́ si ọ̀nà ti ààrẹ tuntun ilé aṣofin ẹlẹkẹsan yóò fi dide. Kidnapped Girl: Iyá Ikimot ní lẹ́yìn ọ̀pọ̀ ìdààmú àti owó láti wá ọmọ náà, òun sọ ìrètí nù Lọjọ Ajé ni Oshimole ṣe ìpàdé pẹ̀lú àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ̀ asoju-sofin ti wọn dibo yàn pẹ́lú àṣẹ pé, dàndàn ni kí ẹgbẹ́ APC ṣe agbédide ẹni ti yóò dari láàrin ẹgbẹ́. Àwọn sẹnatọ nínú atẹjade ti wọn fi sita kìlọ̀ pé, àwọn aṣofin ẹgbẹ́ oṣèlú PDP kò ní gba ki ará ìta lọ́wọ́ nínú bi àwọn yóò se yan adari tuntun. Ki ẹgbẹ oselu APC lọ ki owo ọmọ wọn bọsọ oo, ko si éni to le fa ààrẹ kalẹ Awọn sẹnatọ ọ̀hún fẹ̀sùn kan pé, APC ń fún ara ilú ni òyé bi ẹni pé Saraki ni ipa tó ń ko láti yan olori ile igbimọ asofin agba fun sáà tó ń bọ.",0,yoruba "Igba la a ni ẹnikan ko le lo ile aye gbo, bayii lọrọ ri fun ẹgbẹ agbabọọlu Manchester City ti ife ẹyẹ idije Premier League wa lọwọ wọn. Orogun wọn ti wọn jọ wa niluu kan naa, Manchester United lo fiya ajẹtun iya jẹwọn lairo tẹlẹ nile wọn. Marcus Rashford lo gbayo alakọkọ wọle fun Man United nigba ti ẹrọ VAR fun wọn ni pẹnariti. Ere bọọlu mọ Man City loju nigba ti Anthony Martial gba goolu keji sawọn Man City, lo ba ayo meji sodo ti wọn fi n siwaju wọn. Nicolas Otamendi dayo kan pada, amọ ẹpa ko boro mọ fun Man City. Esi ifẹsẹwọnsẹ yii jẹ iyalẹnu fun ọpọlọpọ awọn ololufẹ ere bọọlu nitori ko si ẹni to le pe Man U le na Man City mọ le. Àkọ́já ewé akọ́nimọ̀ọ́gbá fìdíhẹẹ́ Everton, ìyà ló bádé fún Chelsea Ilẹ n yọ gbe Chelsea ṣubu yakata ni Goodison Park ti ṣe papa iṣere Everton Ẹgbẹ agbabọọlu Everton ṣẹṣẹ le akọnimọọgba wọn Marco Silva lọ ni, ki wọn to yan Duncan Ferguson gẹgẹ bi akọnimọọgba fidihẹ. Iyalẹnu lo jẹ pe iṣẹju marun un ti wọn bẹrẹ ifẹsẹwọnsẹ naa ni Richarlison gbayo kan wọle Chelsea lairo tẹlẹ. Ka to wi, ka to fọ, Dominic Calvert-Lewin gbayo keji sawọn Chelsea lẹyin iṣẹju mẹrin ti ipele keji ere bọọlu naa bẹrẹ. Mateo Kovacic dayo kan pada fun Chelsea, amọ Calvert-Lewin gbayo kẹta wọle fun Everton, ni okote ba bo niru fun Chelsea. Lẹyin ọ rẹyin, ami ayo mẹta sẹyọkan ni Everton fi gbo ewuro soju Chelsea",0,yoruba "RT @user: Odun tun tun Asan wa si Owo, Omo, Alaafia, Ayo, Idunnu ati Aiku ti i se baale oro... Amin!!! @user @user @user ...",0,yoruba ẹkọ́ ṣẹlẹ ni Ibadan ti gbogbo eniyan sọ o ṣe pataki. (1994),0,yoruba "Síbẹ̀síbẹ̀ , àtìlẹ́yìn kì í pọ̀ jù fún ìpínkárí alífábẹ́ẹ̀tì náà .",0,yoruba "Ọwọ ti tẹ Ọjo Kerin Oṣun Kẹrin ọdun 2018 lawọn afunrasi naa yabo ile ifowopamọ nilu Offa ti wọn si pa eeyan mẹtalelọgbọn Agbẹjọro awọn olujẹjọ naa Mathias Emeribe lo pe igbẹjọ laarin igbẹjọ to n waye lọwọlọwọ lati fi salaye bi awọn to n soju ko ti ṣe finu fẹdọ jẹwọ fun awọn ọlọpaa. Labẹ ofin,ile ẹjọ ko le gba ọrọ ti afunrasi ba fi ipa sọ fun ọlọpaa wole. Gẹgẹ bi ohun ti awọn afunrasi mẹta naa Ayoade Akinnibosun,Ibikunle Ogunleye ati Adeola Abraham sọ, niṣe ni awọn ọlọpaa de awọn ni ọwọ mejeeji pẹlu irin ti wọn si fi iya jẹ awọn lati s ohun ti wọn fẹ. Wọn tun fí ẹsun kan awọn ọlọ́pàá pe wọn yin awọn ni ibọn lẹsẹ. Awọn olujẹjọ naa ni awọn ọlọpaa SARS ni wọn gbe awọn lati ofisi wọn to wa nilu Ilorin lo si ile iṣẹ ọtẹlẹmuye Intelligent Response Team to wa labẹ akoso ọga ọlọpaa, Abba Kyari. Bakanna ni awọn afunrasi naa fi ẹsun kan awọn ọlọpaa pe wọn pa awọn Fulani maarun ati ọlọpaa tẹlẹri kan Micheal Adikwu ti o jẹ olori awọn adigunjale Offa naa. Awọn agbẹjoro mejeeji to n soju ijọba ati awọn afunrasi naa wi tẹnu wọn ni iwaju adajọ Agbẹjọro ìjọba, Bola Gold naa fí ọrọ wa awọn afunrasi naa lẹnu wo. Adájọ́ tó ń gbọ́ ẹjọ́ náà, Halima Salman mú Ìgbẹ́jọ́ náà wá sí òpin lẹ́yìn wákàtí méje tí ilé ẹjọ́ náà fí ọ̀rọ̀ wá afurasí náà lẹ́nu wò. Adájọ́ Salman sún ìgbẹ́jọ́ sí ọjọ́ kẹẹdọgbọn osùn kẹrin ọdún fún tí tẹ sìwájú ẹjọ́ náà. Lana ọ̀jọ́bọ ni Olujẹri (Police witness), Hassan Attila ṣe àlàyé fún ilé ẹjọ́ bí ọwọ sikun àwọn ọlọ́pàá tí ṣe tẹ àwọn afurasí náà tí wọ́n sì gbé wọn lọ olú ilé ìṣe àjọ ọlọ́pàá ní ìlú Abuja nínú osun karùn-ún ọdún 2018. Àwọn afurasí márùn-ún tó ń jẹjọ fún ẹsun idigunjale ati ipaniyan naa yabo awọn ile ifowopamọsi nìlú Ọ̀ffà nibi ti wn ti pe eeyan ọgbọn lOsu kẹrin ọdún tó kọjá .",0,yoruba ilera ṣẹlẹ ni Eko ti gbogbo eniyan sọ o dara. (1994),0,yoruba moja mosaa la a fin makinkanju okunrin loju ogun lo difa fun nnamudiiiii kanuu ati awon omo ogun ipob,0,yoruba "Ìmọ̀ tuntun ń jáde, bẹ́ẹ̀ ni ìmọ̀ titun nì ń fẹ́ kárí. À ń kọ ara wa nímọ̀. Ọmọ ọdún márùn ún ni a óò ti bẹ̀rẹ̀ ẹ̀kọ́. #Kiwontode",0,yoruba "joko, Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde sí ara ilẹ̀.",0,yoruba ni ara eni lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa aráyé: ti o dara.,0,yoruba ojú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde.,0,yoruba nìkan. Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "Ìyá fè fi, Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba Ẹ má fi ikú wé oorun. Ẹ má fi ọ̀dá wé ọ̀dà. Wọn ò jọra wọn. #Iseseday #Iseselagba #Yoruba #August20 #emafiwe,0,yoruba iṣẹ́ ṣẹlẹ ni Eko ti gbogbo eniyan sọ o ṣe pataki. (2002),0,yoruba yi fi ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọmọ lo aye àìlẹ̀.,0,yoruba Àìmọ́ ni ó pa Alàji lo tun se lọ.,0,yoruba àgbà ri pe nilo ayẹwo wey ti o pẹ jú nìlọ̀ ni ọ̀nà tí ẹ̀ọ́ kan máa ń gbé ìyẹ̀ alẹ́.,0,yoruba eku ori ire ekunlere iroyinka wazobia reporter ko irogbemi reporter ni,0,yoruba "Awọn eeyan naa ti wọn kọwọọ rin lọ sí olu ileeṣẹ ijọba ipinlẹ Oyo ni Agodi nibi ti wọn ti gbe oriṣiriṣi beba lọwọ p\wlu akọle oniruuru. Die ninu akọle naa ni eyi ti wọn kọ ọ si pe ""Ẹ dẹkun idẹyẹsi awọn ẹlẹsin ibilẹ, gbogbo wa ni ipinlẹ Oyo wa fun."" Bakan naa ni wọn rọ awọn kristẹni ati musulumi lati bawọn bẹ ijọba pe ki o maa fawọn naa lọlude bi awọn ẹlẹsin meji to ku. Akọwe agba ẹgbẹ awọn ẹlẹsin ibilẹ l'Oyo, Ọmọwe Fayemi Fakayode ṣalaye pe iha ti ijọba Gomina Seyi Makinde kọ si awọn ẹlẹsin ibilẹ lo jẹ k'awọn ṣewọde lati fi ẹhonu han. Ninu ọrọ tiẹ, aarẹ Iṣẹṣe Foundation nipinlẹ Oyo, Baale Olukanmi Egbelade sọ pe ohun ti awọn fẹ ni pe ki ijọba fi awọn si ipo to yẹ k'awọn wa lawujọ. Mayowa Omoniyi: Kò sí orin Obey, Sunny Ade abí tàkasúfèé tí ń kò le ta gìtá sí Aarẹ Egbelade ni ""a fẹ ki ijoba kede ọlude logunjo, oṣu kẹjọ lọdọọdun gẹgẹ bi ayajọ ọjọ Iṣẹẹṣe."" Ẹwẹ, oludamọran fun Gomina ipinlẹ Oyo lori ọrọ aabo, Ọgbẹni Odukoya Sunday to bawọn sọrọ ṣeleri lati jiṣẹ wọn fun Makinde.",0,yoruba "RT @user: Egbògi """"""""""""""""ayọ́bi"""""""""""""""" nìyí, ó dára kí aláboyún ó máa mu ú. Wẹ́rẹ́ l'ewé ń bọ́ lára igi, bẹ́ẹ̀ ni yóò rí bí ó bá d'ọjọ́ ìkúnlẹ̀,…",0,yoruba "tí Bàbá fè se, Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba "Àwọn olólùfẹ́ Fẹla Anikulapo-Kuti s'ayẹyẹ ọjọ́ ìbí ọgọ́rin ọdún rẹ̀ Ọdun 1938 ni wọn bi Fẹla nilu Abeokuta to jẹ olu ilu Ipinlẹ Ogun si idile Israel Oludọtun Ransome-Kuti to jẹ ọga ile iwe girama ati mama rẹ Oloye Funmilayọ Ransome-Kuti to jẹ ajafẹtọ ọmọniyan. Fẹla gba oriṣiriṣi ami ẹyẹ kakakiri agbaye ninu orin kikọ, bẹẹ naa ni o ja takuntakun lati ri pe ijọba ṣe ojuṣe wọn fawọn ara ilu nigba aye rẹ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Aláàfin ń se ọgọ́rin ọdún, àwọn àwòrán mánigbàgbé Ìjọba Ọ̀yọ́: Kò sí ilé kan tí wọn kò tíì bí ìbejì ní Igbó Ọrà Ṣọla Allyson: Obìnrin tí kò bá rẹwà ni yóò máa ṣí ara sílẹ̀ Fẹla dagbere faye lọjọ Keji, Oṣu kẹjọ ọdun 1997 ni ẹni ọdun mejidinlọgọta nilu Eko. Awọn eniyan ko le gbagbe Fela laelae Yẹni Anikulapo-Kuti to jẹ akọbi Fẹla gboṣuba fun Fẹla loju opo Twitter rẹ. O ni o daju pe Fẹla n ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ lajule ọrun bayii. Yẹni sọ pe oun ati ọgọrọ eeyan ko ni gbagbe Fẹla laelae. Fẹmi Anikulapo-Kuti naa ki Fẹla ku ọjọ ibi, o ni kosi ẹni to le gbagbe Fẹla laelae pẹlu ọpọ ohun to gbe ile aye ṣe. @Thereal_TommyB ṣe sandankata fun Fẹla , o ni Abami Ẹda sọrọ ko too ku pe oun ko le ku laelae nitori apo oun niku wa. Aarẹ ilẹ orilẹede Faranse, Emmanuel Macron se abẹwo si Fela Shrine ni Naijiria Ààrẹ ilẹ̀ Faranse, Emmanuel Macron yóò dé sí Nàíjíríà ní Ọjọ́ Isẹgun, níbi tí yóò ti má a se ìpàdé pẹ̀lú Ààrẹ Muhammadu Buhari. Aarẹ ilẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari yoo ma gbalejo Aarẹ ilẹ orilẹede Faranse, Emmanuel Macron fun ijiroro lori eto abo ati igbesunmọmi lorilẹede Naijiria. Lasiko abẹwo rẹ, Macron yoo tun se abẹwo si ibi igbafẹ, ‘Afrika Shrine’ ni ipinlẹ Eko nibi ti olorin afro- juju, Fela Anikulapo Kuti da si lẹ, ti ọmọ rẹ, Femi Kuti si se atunse si, to si pe orukọ rẹ ni ‘New Afrika Shrine’. Pẹlu abẹwo si ‘New Afrika Shrine’, Macron yoo jẹ aarẹ akọkọ ti yoo kọkọ wa si ile igbafẹ ti wọn mọ si agbegbe ti wọn ti n mu ogun oloro bi igbo, ati awọn obinrin ti wọn ki n wọ asọ to bo gbogbo ẹya ara wọn lati jo. Macron yoo jẹ aarẹ akọkọ ti yoo kọkọ wa si ile igbafẹ ti wọn mọ si agbegbe ti wọn ti n mu ogun oloro bi igbo. Lara awọn ayeye ti yoo ma waye ni ile igbafe naa ni, awọn olorin takasufe ti yoo ma lu ilu si awọn eniyan ni ibadi ati awọn alasọ alarabara ti yoo ma fi ẹwa wọn han nibi ayẹyẹ naa. LASTMA: Ẹ̀rí la nílò láti fi òsìsẹ́ tó ń gba rìbá jófin Ohun to yẹ ki o mọ nipa aarẹ ilẹ Faransẹ, Emmanuel Macron Lopin ọsẹ to kọja ni Aarẹ ilẹ Faranse naa, Emmanuel Macron darapọ mọ awọn adari awọn orilẹede to wa ni ilẹ Afirika, ni ipade ‘Ajọ Africa Union’ to waye ni olu ilu orilẹede Mauritania, Nouakchott. Iyawo Aarẹ Ilẹ Faranse, Brigitte Macron to jẹ olukọ rẹ Emmanuel Macron nigbati aarẹ naa wa ni ọmọ ọdun marundinlogun (15) , fi ọdun mẹrindinlogun (24) ju ọkọ rẹ lọ.",0,yoruba Iye àwọn òǹlò ẹ̀rọ ayélujára ní Nàìjíríà fò fẹ̀rẹ̀ sókè láti ẹgbẹẹgbẹ̀rún 98 . 3 ní ọdún - un 2017 sí ẹgbẹẹgbẹ̀rún 100 . 5 ní 2018 .,0,yoruba "Laarin isẹju kan ni ẹni to bori idije naa jẹ ata aadọta, to si gba ẹbun owo goolu to jẹ giramu mẹta. Oludije mejila lo kopa ninu idije naa. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:",0,yoruba kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbfi yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú.,0,yoruba ẹranko inú àwòrán yìí ni àwọn yorùbá máa pè ní agẹmọalágẹmọ ẹranko tí àwọ̀ rẹ̀ ma ń bá gbogbo ohun wà láyìíkáa rẹ̀ dọ́gba òun náà ni à ń pè ní ọ̀gà,0,yoruba "Tó bá jẹ́ òótọ́, a óò fi pánẹ́ẹ̀lì náà pamọ́ fún ra rẹ̀ sínú igun ojú kọ̀ǹpútà náà nígbà tí atọ́ka náà bá fi agbègbè pánẹ́ẹ̀lì náà sílẹ̀. Gbígbé atọ́ka náà lọ sí igun yẹn lẹ́ẹ̀kan si á fa kí pánẹ́ẹ̀lì náà tún farahàn.",0,yoruba Arsenal fọ́ Sevilla lẹ́nu pẹ̀lú góòlù 6-0,0,yoruba "ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìṣẹ́ ọ̀pọ́lọ̀.",0,yoruba "Harry Kane ni ọ̀pọ̀ olólùfẹ́ eré bọ́ọ̀lù lérò pé yóò ''Golden Boot'' ní Russia Ọgọ́jọ ayo o din mẹta ni awọn agbabọọlu ti gba sawọn ninu ifẹsẹwọnsẹ ọgọta ti wọn gba lati igba ti idije naa ti bẹ̀rẹ̀. Ẹlẹsẹ ayo to jẹ ọmọbibi ilẹ Gẹẹsi Harry Kane lo n siwaju ninu awọn ti wọn gba bọọlu sawọn ju ni Russia pẹlu ami ayo mẹfa. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kane yoo ni anfani lati fi kun ami ayo rẹ nigba ti ilẹ Gẹẹsi ba koju Croatia ninu ifẹsẹwọnsẹ to kangun si aṣekagba wọn l'Ọjọru. Ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sí dé ìpele tó kángun sí àṣekágbá nínú ìdíje ife ẹ̀yẹ àgbáyé fún ìgbà àkọ́kọ́ ní ọdún méjìdínlọ́gbọ̀n Agbaọjẹ agbabọọlu Cristiano Ronaldo to jẹ ọmọbibi orilẹede Portugal gba ayo mẹrin sawọn ki orilẹede naa to lọ'le lati Russia. Cristiano Ronaldo wá lára àwọn àgbàọ̀jẹ̀ agbábọ́ọ̀lù tí kò gba ife ẹ̀yẹ àgbáyé rí Ẹlẹsẹ ayo Romelu Lukaku to n gba bọọlu fun Belgium naa ti gba ayo mẹrin sawọn, o si ni anfani lati fikun ami ayo rẹ nigbati Belgium ba koju France. Ikọ̀ Belgium fakọyọ nígbàtí lé Brazil lọ'lé láti Russia Ọmọ ilẹ Russia ti wọn n gbalejo idije ife ẹyẹ agbaye Denis Cheryshev naa wa lara awọn to ti gb'ayo mẹrin sawọn ni Russia. Orílẹ́èdè Russia gbìyànjú ṣùgbọ́n wan kùnà láti kọjá ìpele ''quarter finals'' nínú ife ẹ̀yẹ àgbáyé Antoine Griezmann to jẹ agbabọọlu iwaju fun orilẹede France naa ko gbẹyin ninu awọn ẹlẹsẹ ayo lẹyin ti o ti gb'ayo mẹta wọle. Ọdún 1998 ni ikọ̀ France ti gba ife ẹ̀yẹ àgbáyé kẹ́yìn Kylian Mbappe ti oun naa jẹ ọmọbibi ilẹ France ni ami ayo mẹta ninu idije ife ẹyẹ agbaye to n lọ. Kylian Mbappe fakọyọ nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ láàrin France àti Uruguay Diego Costa ti o ti d'ero ile bayi pẹlu ẹgbẹ agbabọọlu Spain naa gb'ayo mẹta sawọn ki wọn to l'ọle lati Russia. Ọmọbíbí orílẹ́èdè Brazil ni Diego Costa ṣùgbọ́n ó pinu láti máa ṣojú ilẹ̀ Spain",0,yoruba Ahhhhhhhh! ewo aworan Zahra omo Ogagun @user ta ni ori iru omo ti o dun ti o lewa ti ko ni dibo fun baba re http://t.co/kJO89o4GzW,0,yoruba "dé jáde nípa àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn ẹ̀kọ́ ọmọ aláwọ̀ wà níṣẹ̀.",0,yoruba olukemi zaynab yorùbátv ẹgbẹ ọmọ olúwa bí gbogbo àgbáyé ojú òpó ìkànsíraẹni □ yoruba tv,0,yoruba ".@user Emo wolu Iwo ni Ipinle Osun. Abdulrasheed Adewale Akanbi ti fe ja si oja, e mu so o, ki Oba alade ile Yoruba ma so isokuso pe Oluwo ilu Iwo ti di oye itan, Akanbi ti yi Oye Oluiwo si Emir ile Yoruba. Nje ko kin se aisan opolo lo ya wo aafin Oluiwo ilu iwo bayi? https://t.co/3rj0aYXbO9",0,yoruba owo ṣẹlẹ ni Ibadan ti gbogbo eniyan sọ o dara. (2005),0,yoruba Àlá àti ìlépa mi láti gba ife ẹ̀yẹ ‘World Cup’ ti dópin – Cristiano Ronaldo,0,yoruba àwọn èrò àti àsà tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa aráyé: ti o ní wúlò.,0,yoruba "Ọ̀pọ̀ àwọn ènìyàn ló ń reti ki Damilola Adekoya tí gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Princess comedian sọ̀rọ̀ lórí àwọn ìsẹ̀lẹ̀ tuntun lórí ẹjọ́ Baba Ijesha. Láipẹ́ yìí ni ẹbi Baba Ijesha kan ke gbàjarè nilé ẹjọ pé ìyà ti Baba Ijesha n jẹ látimọ́lé ti pọ̀ jù lórí ẹ̀sẹ̀ tí kò mọwọ́. Ọmọbinrin náà fi kun pé, nítori Baba Ijesha kọ̀ lati fẹ Princess ni ó ṣe ko báa. O kú ogun àjàyé Tope Alabi, odò Jodani lo ṣẹ̀ṣẹ̀ là kọjà yìí o! Àmọ́ rántí pé ... - Mike Bamiloye Iyabo Ojo bẹ̀rẹ̀ ìjà rọ̀fọ̀rọ́fọ̀ pẹ̀lú máníjà rẹ̀ tẹ́lẹ̀ lórí ẹ̀sùn olè jíjà Èèyàn mẹ́ta ló kú níbi afẹ́fẹ́ gáàsì tó jó Chinese restaurant lágbègbè Sheraton ní Ikeja l'Eko - LASEMA Olùwọ́de EndSARS bímọ tuntun nínú ẹ̀wọ̀n lẹ́yìn tó ti lo oṣù mẹ́jọ ní àhámọ́ Rahmon ń múra láti lọ rí ìyàwó àti ìbèjì tó bí ní US ni wọ́n bá pa á níbi ìjà tó bẹ́ sílẹ̀ ní Iwo road Ṣùgbọ́n ninu ìtàkurọ̀sọ kan ti Damilola Adekoya ṣe Esther Aboderin (ESABOD) lo ti ṣàlàyé pé ko si ìyà kankan ti wọn fi n jẹ Baba Ijesha látìmọ́lé. Ó ni ọ̀rọ̀ tí kò ni ìtumọ̀ rárá ni ọmọbinrin náà ń sọ nítorí ọ̀nà wo ni ó fi mọ̀ pé irú nǹkan bẹ́ẹ̀ wáyé, ṣé àwọn méjèjì ni Baba Ijesha ń bá sùn papọ̀ ní? Princess ni ọ̀rọ̀ ti kò mú ọpọlọ dání ni ọ̀rọ̀ ọmọbinrin náà ń sọ, àti wípé, ẹni tí wọ́n ń tórí rẹ̀ sọ́rọ̀ gan fúnra rẹ̀ ń bẹ̀bẹ̀, àwọn ń pariwo kiri. Princess fẹ̀sùn kan pé tí àwọn ọgá ọlọ́pàá bá ti lọ ilé bi aago mẹ́sàn alẹ́, àwọn ọlọ́pàá má n mú Baba Ijesa jáde láti pààrọ aṣọ, ti ó sì máa n ṣe bi ó ṣe wù ú. Ó ní bí wọ́n ṣe n ṣe gbogbo nǹkan wọ̀nyí fún tó òun kò bínú, ""ṣùgbọ́n mo wòó pé, ibi ti ènìyàn kò sí Ọlọ́rùn wà níbẹ̀. ""Bí Baba Ijesha ṣe wà ní àháma ló n rán àwọn eǹìyàn sí mi láti bẹ̀bẹ̀, èyí tí Idowu Philips ti gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Iya Rainbow wà lára wọn. "" Nǹkan tí wọn kọ́kọ́ sọ ni pé Baba Ijesha ní kí maa bẹ̀ ẹ́, olóòre mi ni, mo fẹ́ kí ẹ bá mi bẹ Princess, alaanu mi ló jẹ́ mo dẹ̀ ti ṣẹ̀ ẹ́, kó dárí jì mí. Princess ni òun sọ fún Iya Rainbow, pé kí wọ́n jọ pé àgbalagbà ni wọn òun kò sì fẹ̀ ṣẹ̀ nítorí ò ń bọ̀wọ̀ fún un. Gbájúgbajà òṣèré náà fi kun pé, òun sọ fún iya Rainbow pé ó ni láti sọ nnkan tó ṣe, sùgbọ́n nígbà tí òun yóò fi parí alàyé pẹ̀lú Iya náà fẹ́ dákú ni. ""Nígbà ti mo ṣàlàyé ọ̀rọ̀ fún Shokoti àti Olaiya Igwe, Olaiya ń gbọ̀n ni, àti pé ó ni àwọn ọ̀rọ̀ kan tí kò ṣee sọ síta lórí afẹ́fẹ́, ṣùgbọ́n ó pọn dandan kí n sọ fún wọn.",0,yoruba "Dokita Ahmed Adeagbo, to jẹ oludari agba fun ileewosan ijọba, Federal Medical Centre, sọ fun BBC pe oku eeyan mẹfa ni wọn gbe de ileewosan naa. Yatọ si awọn yii, o ni eeyan bi ogún ni wọn gbe wa to ti farapa. Ileewosan FMC, Owo, ni ọkan lara awọn ileewosan ti wọn gbe awọn to farapa nibi ikọlu ti awọn agbebọn ṣe si ile ijọsin Aguda kan nilu naa. O tun sọ pe eeyan marun-un ni wọn sare gbe wọn yaara iṣẹ abẹ. “Ọgbẹ ọta ibọn ati bi i pe nkan jo eeyan ni ara, lo wa lara awọn ti wọn gbe wa sileewosan FMC.” Bakan naa lo sọ pe awọn ọmọde naa wa lara wọn. 'Kò sí àlùfàá tí wọ́n jígbé níbi ìkọlù sí ṣọ́ọ́ṣì ní Owo' Awọn olori ijọ Aguda nipinlẹ Ondo, ti koro oju si ipaniyan to waye ni ẹka ile ijọsin naa kan nilu Owo, nipinlẹ Ondo, lọjọ Aiku. Ninu atẹjade ti akọwe ikede ile ijọsin naa fi sita, Alufaa Augustine Ikwu, sọ pe ibanujẹ nla gba a ni iṣẹlẹ naa jẹ fun  ijọ. O ni gbogbo awọn alufa ati bisọọpu to wa ninu ijọ St. Francis Catholic church, ti iṣẹlẹ naa ti waye lo wa ni alaafia. O sọ eyi gẹgẹ bi esi si iroyin kan to n lọ lori ayelujara pe awọn agbebọn naa ji lara awọn alufaa gbe lọ. Ọ̀fọ̀ ayérayé n dúró de àwọn tó kọlu ilé ìjọsìn ní Owo - Buhari Aarẹ Muhammadu Buhari ti bu ẹnu atẹ lu ikọlu ti awọn agbebọn ṣe si ile ijọsin Aguda kan nipinlẹ Ondo lọjọ Aiku, ọjọ karun-un, oṣu Kẹfa, ọdun 2022. Ninu atẹjade ti agbẹnusọ rẹ, Femi Adesina fi sita lori ayelujara Facebook, ni Buhari ti sọ pe awọn ẹlẹmi okunkun nikan lo le ṣe iru iṣẹ buruku bẹẹ. “Aarẹ sọ pe ọ̀fọ̀ ayeraye lo n duro de awọn to sẹ ikọlu ọhun, ni aye ati ni ọrun.” O ni orilẹ-ede Naijiria ko nii fi aaye silẹ fun awọn oniṣẹ okunkun, lati bori imọlẹ rẹ. Gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu, ti koro oju si ikọlu to waye nile ijọsin kan nilu Owo lowurọ ọjọ Aiku. Iroyin sọ pe isin ọjọ isinmi ṣẹṣẹ pari ni, nigba ti awọn agbebọn ti ẹnikẹni ko mọ yabo ile ijọsin ọhun, ti wọn si n yinbọ mọ awọn olujọsin. Gomina Akeredolu sọ pe iṣẹlẹ naa jẹ eyi to jani laya, ti oun ko si nireti iru rẹ rara. “Iṣẹlẹ yii ba mi lojiji. Ṣugbọn ju gbogbo rẹ lọ, ao lo gbogbo nkan to wa ni ikapa wa, lati mu awọn to ṣe ikọlu yii. “Mo ba awọn eniyan mi nilu Owo kẹdun, paapaa mọlẹbi awọn to ku, ati ijọ Aguda.” Akeredolu rọ awọn eniyan ilu Owo, lati ma gbeja ara wọn, ki wọn o si ma a kiyesara. O ni oun ti ba awọn olori ileeṣẹ eto aabo sọrọ, idaniloju si ti wa pe awọn alaabo yoo da alaafia pada silu Owo. Ọpọ eeyan, to fi mọ awọn ọmọde ati obinrin, lo ku, to si farapa nibi iṣẹlẹ naa. Iroyin to n jade lati ilu Owo, nipinlẹ Ondo sọ pe ọpọ eeyan lo ku ninu agbara ẹjẹ ninu ile ijọsin Aguda kan lowurọ ọjọ Aiku. Gẹgẹ bi a ṣe gbọ, isin owurọ ọjọ isinmi n lọ lọwọ ninu ijọ naa, St. Francis Catholic Church, Owaluwa, Owo, ni awọn agbebọn yabo ṣọọṣi naa ti wọn si ṣina ibọn bo awọn olujọsin. Nkan ti akọroyin BBC Yoruba fojuri Akọroyin BBC to lọ sibi iṣẹlẹ naa jabọ pe, awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn sọ pe awọn afurasi darandaran lo kọlu ile ijọsin naa. O ni oun paapaa fi oju ri ẹjẹ rẹpẹtẹ ati oku eeyan ninu ile ijọsin naa. Awọn eeyan naa tun sọ pe wọn ti gbe awọn oku kan lọ si mọṣuari, ati awọn eeyan kan lọ si ileewosan ṣaaju ko to o de ibẹ Akọwe ẹgbẹ ọdọ ninu ijọ naa, sọ fun BBC pe, alufaa ti ṣe oore-ọfẹ ipari isin, ti awọn eeyan si fẹ ma a jade. “Ọkunrin kan to n ta nkan ẹlẹrindodo ni ẹnu ọna ṣọọṣi naa ni wọn kọkọ yinbọn mọ. “Bi a ṣe rii nkan to ṣẹlẹ, a sare ti ilẹkun lati daabo bo gbogbo wa. Lẹyin asiko diẹ, a ro pe iṣẹlẹ naa ti rọlẹ, a si ni ki awọn eniyan ma a lọ. “Sadeede ni awọn eeyan kan yawọ inu ṣọọṣi, ti wọn si ju nkan abugbamu ‘dynamite’, ki wọn o to bẹrẹ sini yinbọn mọ awọn olujọsin.",0,yoruba "Afẹ́fẹ́ ni òyì-àrá, irúfẹ́ òyì-iná kan ni. Bí kò bá sí òyì-àrá nínú ìpele ayé inú afẹ́fẹ́ ní ìta àgbáńlá ayé kò ní fi bẹ́ẹ̀ sí ohun abẹ̀mí tí ó tó bẹ́ẹ̀ lórí ilẹ̀ ayé. Ìpele òyì-àrá tí ó ti ń yinrin yìí, ní í mú kí oòrùn ó ràn láràn fẹjú. #KiEpoRobiKogbaWole",0,yoruba Sùgbọ́n ó seni láàánú pé àwọn igba ẹgbẹ̀rún ènìyàn ló ti jẹ́ Ọlọ́run nípè ( tí wọ́n ti kú ) .,0,yoruba "Nigba ti wọn n ba wa sọrọ, awọn ọmọ ẹgbẹ Yoruba dun lasa salaye pe, ko si bo ti wu ki awọn mura daada to, awọn ọkunrin ni Egypt yoo papa tẹ awọn lọyan, gba awọn ni idi, ti wọn yoo si tun da awọn laamu. Wọn ni suuru gidigidi ni awọn fi n ba awọn ọmọ Egypt gbe, ti ihuwasi ati asa wọn si yatọ gedegede si ti awa ọmọ Naijiria. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Koda, wọn sọ ọpọ aayan ti wọn n se lati ri daju pe awọn ko gbagbe asa ati ise wa, ti wọn si n fi kọ awọn ọmọ wọn ti wọn bi si ajo pẹlu. Ẹ wo ẹkunrẹrẹ fidio yii, lati mọ ohun ti oju awọn ọmọ Yoruba to wa ni Egypt n ri lọwọ awọn ọmọ onilu.",0,yoruba "Yatọ si pe isẹ rẹ gba ki gbogbo ọmọ Naijiria mọ ọ bii ẹni mọ owo, sibẹ, lọpọ igba to ba sọrọ, awọn araalu ki i fẹ́ gbọ ọrọ rẹ. Yala nitori pe wọn maa n ni ọrọ rẹ jinna sootọ ni tabi pe awọn ko tilẹ nigbagbọ ninu ijọba Naijiria. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: O ṣeese kẹ ti gbọ pe Lai Muhammed ni awọn akọroyin to n fẹnu tẹnbẹlu Naijiria, lo ṣokunfa bi alaṣẹ Twitter, Jack Dorsey ṣe gbe olu ileeṣẹ rẹ ni Afrika lọ si Ghana dipo Naijiria. Awuyewuye ọrọ yii ko ti tan nilẹ ṣugbọn ka fi eleyi ṣe iranti fun ara wa ni, nipa awọn igba marun un miran tọrọ Lai Mohammed mu inu bi awọn ọmọ Naijiria. Diẹ ree ninu wọn: Lai Mohammed ni ki Big Brother Naija kogba sile tori Covid-19 Lọdun 2020 ileeṣẹ iroyin kan ni Naijiria gbe iroyin jade pe, Minisita Lai Mohammed paṣẹ fun adele adari ajọ to n sakoto eto igbohunsafẹfẹ ni Naijiria, Armstrong Idachaba. Wọn ni Muhammed pasẹ fun Idachaba pe ko kọwe si awọn eleto ere idaraya Big Brother Africa, lati kogba sile. Muhammed, ggẹ bi wn se sọ ni o ṣeeṣe ki awọn eeyan ko arun Covid-19 lori eto naa. Ọrọ naa ko dun mọ awọn eeyan Naijiria ninu, paapa awọn ọdọ, ti wọn ni Lai Muhammed fẹ gba ohun to n mu inu awọn dun lọwọ awọn ni. Eto aabo munadoko labẹ aarẹ Buhari Ni osu kinni lọdun 2021, lasiko to n ba awọn akọroyin sọrọ, ni Lai Muhammed kede pe eto aabo munadoko labẹ isejọba Muhammadu Buhari ju tawọn ijba to ti kọja lọ. Lai sọ pe ka fi ẹgan kun, ka tun yọ tẹgan kuro, eto aabo ni Naijiria munadoko labẹ aarẹ Buhari ju igba ti ijọba ti tẹlẹ, PDP, wa lori oye lọ. Ayodele Fayose, to jẹ eekan ninu ẹgbẹ PDP wa lara awọn to faraya lori ọrọ yii, ti ọpọ ọmọ Naijiria si kin lẹyin lati gboju agan si Lai Muhammed. Ko yẹ kawọn ọmọ Naijiria faraya lori ọrọ alekun owo epo Lasiko to n ba awọn akọroyin sọrọ, naa tun ni Minisita feto iroyin ati asa sọ pe ko yẹ kawọn ọmọ Naijiria bara ajẹ nitori alekun owo eroja epo rọbi. Lai Mohammed ni ifaraya awọn ọmọ Naijiria lori alekun owo epo kii ṣe oun to yẹ nitori bi owo epo ṣe n lọ soke, naa lo tun n wa silẹ, ko si yẹ ki wọn binu. Muhammed ni ti owo epo rọbi ba walẹ, o di dandan kawọn araalu san owo kekere lowo epo nitori naa ko yẹ ki wọn maa fa ibinu yọ lori rẹ. Bed Wetting: Tolulope Joseph ní ò lé ní ogún ọdún tí òun fi tọ̀ sílé kí ìwòsàn tó dé Ero wa ko yipada lori abadofin iṣakoso ẹrọ ayelujara ""Ko si ijọba kankan to ni ifẹ ara ilu lọkan ti yoo faaye gba ki awọn eeyan maa sọrọ ikorira, ki wọn si tun maa pin iroyin eke lori itakun agbaye."" Diẹ ree lara ọrọ ti Minisita sọ nipa abadofin iṣakoso ẹrọ ayelujara tawọn ọmọ Naijiria fi yari mọ lọwọ. Loṣu Kọkanla ọdun 2019 lo fi ọrọ yii lede, to si tun fi akawe awọn orileede mii lagbaye to n sakoso bi awọn eeyan wọn ṣe n lo ẹrọ ayelujara. Ninu awọn orileede to darukọ ni Singapore, China, South Korea, ati bẹẹ bẹẹ lọ. Ẹ̀yin tẹ̀ ń ta Nàíjíríà lọ́pọ́, ojú yín ti ja lórí iléeṣẹ́ Twitter tó lọ Ghana - Lai Muhammed Minisita feto iroyin ni Naijiria, Alhaji Lai Mohammed ti da si awuyewuye lori bi ileesẹ Twitter ṣe gbe ọọfisi rẹ ni Afrika lọ si Ghana dipo Naijiria. Lọjọ Aje ni ọga ileeṣẹ Twitter, Jack Dorsey kede pe awọn ti ṣetan lati si ọfisi si ilẹ Afrika, ti olu ileeṣẹ naa yoo si tẹdo si orileede Ghana. Kete ti o fi ikede yii sita lawọn ọmọ Naijriia ti n sọ ariwisi nipa igbesẹ yii, tawọn kan si ni Naijiria lo yẹ ko gbe ileesẹ naa wa dipo Ghana. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Alaye tawọn ọmọ Naijiria fi kin ọrọ wọn lẹyin ni pe, Naijiria tobi ju Ghana lọ pẹlu awọn idi miran. Lai Mohammed naa wa salaye idi ti ọrọ naa fi ri bẹẹ nigba to n ba awọn akọroyin sọrọ l‘Ọjọbọ. O ni ohun to yẹ ni pe ki Twitter gbe olu ileeṣẹ rẹ ni Afrika wa si Naijiria ''nitori nkan bi eeyan miliọnu marundinlọgbọn lo n lo Twitter ni Naijiria, ti wọn ko si ju miliọnu mẹjọ lọ ni Ghana'' ''Lai si iye meji, kii ṣe nitori ọrọ aje lo fi tori rẹ gbe igbesẹ yi'' Lai Muhammed ni Twitter lẹtọ lati gbe olu ileeṣẹ rẹ lọ si ibikibi to ba wu u. Minisita wa fi ọrọ kun eleyi ti o sọ pe ""Mo lero pe eleyi yoo jẹ ẹkọ fawọn ọmọ Naijiria.'' Lai ni ''Nkan ti oju eeyan maa n ri ree, ti o ba ta orileede rẹ lọpọ nitori ọpọlọpọ igba lawọn eeyan ma n sọ asọdun lori ipenija to n koju Naijiria.'' O tẹsiwaju pe ''ko si igba teleyi foju han bi asiko iwọde ENDSARS nibi tawọn akọroyin ti n jijadu laarin ara wọn lori ẹni ti yoo ṣapejuwe Naijiria gẹgẹ bi ọrun apaadi ti awọn eeyan ko gbọdọ wa sibẹ.'' Slain Ekiti Police woman: Ìyá rẹ̀ ní àìrìṣẹ́ṣe ló mú kí Bukola Olawoye gba iṣẹ́ ọlọ́pàá O ni oun dupẹ lọdọ Ọlọrun pe orileede Amẹrika fọ Naijiria mọ pe ko si eeyan kankan to ku ninu iṣẹlẹ Lekki Toll Gate. Minisita naa pari ọrọ rẹ pẹlu amọran sawọn ọmọ Naijiria lati nifẹ ilẹ wọn lọkan. O ni ''bi o ba ba ile ara rẹ jẹ, nibo lo ku ti wa a gbe?'' Twitter gbé olú ilé iṣẹ́ rẹ̀ àkọ́kọ́ ní Áfíríkà lọ Ghana, ọmọ Nàíjíríà yarí Ilé iṣẹ́ Twitter tó fi ilẹ̀ ilẹ̀ Amerika ṣe ibùdó ti yàn orílẹ̀ -èdè Ghana gẹ́gẹ́ ofíisì rẹ̀ túntun ni afirika, sùgbọ́n ọpọ ọmọ Naijiria lo n beere pe kí ló mú wọn yan Ghana láàyò gan? Lọ́jọ́ Ajé òṣẹ̀ yìí ní Jack Dorsey fi léde lórí twitter pé, ""Twitter ti balẹ̀ bàgẹ sí ilẹ̀ adúláwọ̀. Ghana ẹ seun o àti @NAkufoAddo"". Eyi si lo dabi ni pe ileesẹ Twiitter fi n kéde agbekalẹ ọọfisi rẹ akọkọ ni Afirika. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kí ọ̀gà àgbà pátápátá fun ileesẹ Twitter tó le kọ èyí sí ojú òpó twitter rẹ̀, tó sì tún ṣe àbẹ̀wò sí orílẹ̀èdè Ghana ni ọdún 2019, eyi fi han pé ìjọba Ghana wà lẹ́yìn ilé iṣẹ́ náà gbáágbágbá. Àsìkò yìí bákan náà tó sàbẹ̀wò sí Ghana ni Dorsey ń ṣe àbẹ̀wò káàkiri awọn orílẹ̀-èdè to wa nilẹ̀ Afrika, bákan náà ló sì sọ pé, òun fẹ wá gbé ilẹ̀ adúiláwọ̀ fún oṣù mẹ́ta sí mẹ́fà. Amọ o ni òun kò ti mọ ibi ti òun yóò gbé ni Afrika. Sùgbọ́n ó jọ bi ẹni pé gbogbo ètò ló ti tò lati tẹdo si Ghana, ni ọ̀gá àgbà twitter ṣe kọ sórí twitter fúnra rẹ̀. Ààfàní rèé fún Dorsey láti gbé, ki o sí kópa nínú si agbega ètò ìmọ̀ ẹ̀rọ ni ilẹ̀ adúláwọ̀, kó jẹ́ pé Ghana náà ló wà, eyi yóò jẹ́ ìwúrí fún ọ̀pọ̀ ọmọ aláwọ̀ dúdú nilẹ̀ Afíríkà. Abẹ̀wọ sojú òpó Twitter fi han pé ààyè mẹ́sàn ló ṣí sílẹ̀ fún ìṣẹ́ níbẹ̀ Sàbẹ̀wò sí ojú òpó wọ́n níbí Wayi o, ìdùnnú súbú lu ayọ ni ìròyìn náà fún àwọn olùgbé Ghana, tó fí mọ ààrẹ Ilẹ̀ Ghana, Nana Akufo-Addo, tó sàkàwé ìgbésẹ̀ náà bíi èyí tó dára, sùgbọ́n ọ̀rọ̀ ṣe ọ̀tọ̀ọ̀tọ lọ́dọ̀ àwọn ọmọ Nàìjíríà. Awọn ọmọ Naijiria fariga: Bí àwọn ọmọ Nàìjíríà kan ṣe n gbarata pé orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ni ọọ́fíísì túntun ileesẹ Twitter naa tọ́ sí, ni àwọn míràn gbà pé ijọbaNàìjíríà àti ètò ààbò tó mẹ́hẹ, kò lé jẹ́ kí irú ilé iṣẹ́ bẹ́ẹ̀ wá tẹ̀dó sí Nàìjíríà. Ó kọ́ pé, "" Ìfọkànbalẹ̀ tí a ni láti gbé ilé iṣẹ́ wa sí Ghana jẹ́ ìròyìn ayọ, ìjọba Ghana fi tayọ̀tayọ̀ gba ìkéde náà, ó sì ni ìbáṣepọ̀ wọn yóò dán mọ́rán. Kíní ìdí ti Twitter fi yan Ghana Láàyò? Ó lè jẹ́ pé nítórí Ghan a máa gbárùkù tí òwò Gẹ́gẹ́ bi ìwádìí Bánkì àgbáyé kan tó jáde ni ọdún 2019, ipò 118 ní Ghana wà lára àwọn orílẹ̀-èdè tí o rọrun láti ṣe òwò lẹ́gbẹ̀ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, tó wà nípò 131. Ìtùmọ̀ èyí ni pé, ẹni tó jẹ́ ipò àkọ́kọ́ ni òwò dùn ṣe jù níbẹ̀, ìpò tí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà wà túmọ̀ sí pé kò rọ̀rùn rárá lati se owo lorilẹede rẹ. Sùgbọ́n gẹ́gẹ́ bí ọ̀gá yìí ṣe sọ, òun yàn orílẹ̀-èdè Ghana nítori pé ètò ìjọba àwa arawa ń rú gọ̀gọ̀ níbẹ̀. Bákan náà lo ni wọ́n faramọ́ òmìnirà láti sọ èrò ọkàn ẹni lórí ayélujára, pàápàá jùlọ lórí ayélujára èyí tí twitter ń pè fún. Akomolede àti Asa: Kí ni Ìjálá láàrin àwọn ewì alohùn àti bí wọ́n ṣe ń sun-ún? Bákan náà ni twitter tún sọ àwọn ìdí míràn tí wọ́n fi yan Ghana láàyò bí i eto ajọsepọ okoowo lai ni owo ori ọja ninu, taa mọ si ""African Continental Free Trade Zone "" Ilé iṣẹ́ twitter ni ẹka ilé iṣẹ́ rẹ méjìlélọ́gbọ̀n ni orílẹ̀-èdè mọ́kàndínlógún.",0,yoruba Fayemi declares for presidency: Kayode Fayemi sọ pé ètò ààbò ni yóò jẹ́ kókó nínú ìjọba òun,0,yoruba àsà tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìwà: ti o dun.,0,yoruba "Ọkan tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..",0,yoruba àwẹ ọba. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó ṣe pàtàkì.,0,yoruba "Iba Gani Adams sọ ọrọ yii ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC News Yoruba lọjọbọ. O ni pẹlu bi ọrọ abo, eto ẹkọ, ilera ati igbayegbadun araalu ṣe ri ni Naijiria bayii, ilẹ Yoruba ko lee tẹsiwaju ati maa sinru nibi to yẹ ko ti lẹnu. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Gani Adams ni lootọ oun ko lee yọ ẹrẹkẹ ṣuti tabi eebu si ọba kankan ni ilẹ Yoruba, ṣugbọn o wa rọ awọn ọba Yoruba lati fi ara wọn sipo ọwọ, ki wọn si maa tẹ sibi tawọn ọmọ Yoruba ba tẹ si. ""Oluwo ṣẹṣẹ jẹ Ọba ni, ko mọ itan Yoruba lo fi n ṣe gbogbo ohun to n ṣe lori oye, ko mọ pe ọba ti ko ba se ifẹ araalu maa n kabamọ gbẹyin ni."" Oluwo, tí wọ́n bá rán ọmọ níṣẹ́ ẹrú, kó fi t'ọmọ jẹ - Gani Adams O ni awọn iroyin to n lọ kaakiri n fihan pe, awọn ọbalaye nilẹ Yoruba naa n lọwọ ninu wahala naa pẹlu bi ọpọlọpọ wọn ṣe n gba maluu ati ẹran ọsin miran lati dakẹ lori iwa ibajẹ awọn Fulani darandaran. Adams ni eyi gan n kun ara ohun to n fun awọn ọbayejẹ ọdaran darandaran naa lanfani ati tẹsiwaju ninu iwa aitọ wọn. Iba Gani Adams ṣalaye pe, lootọ awọn ọba alaye kan ti ngba ohun ti ko tọ bi abẹtẹlẹ, amọ kii ṣe gbogbo ọba lo jẹ ọbẹ, ja epo si aya , sugbọn igbesẹ ti n lọ lati mu atunṣe ba iha naa. Bí Oduduwa Republic bá bẹ̀rẹ̀, a ò ní ṣe aburú fún àwọn tó takò wá, ìlànà ààtẹ̀lé rèé - Banji Akintoye O tun ke sawọn eekanlu, ọbalaye ati ilumọọka ilẹ Yoruba ti ko ba nifẹ si idaduro ilẹ Yoruba lati dakẹ jẹjẹ titi ayeraye, ki wọn maa ba a foju wina ibinu awọn ọmọ Yoruba. Ẹwẹ, Iba Gani Adams ṣalaye pe, ihuwasi awọn agbofinro pẹlu ko ran ilakaka araalu lati dẹkun ipenija abo ni ilẹ Yoruba lọwọ. Nigba to n mẹnu ba bi ọlọpaa ṣe fi mẹta ninu awọn ọmọ ẹgbẹ OPC si ahamọ, lẹyin ti wọn fi panpẹ mu Wakili, afurasi Fulani ti wọn ni o n da awọn eeyan oke Ogun laamu, gẹgẹ bi apẹrẹ,. Iba Adams ni awọn agbofinro ko fẹ fi ọwọ sowọpọ pẹlu araalu lati dẹkun ipenija eto aabo naa. O ni bi awọn ọbalaye, agbofinro ati alaga ijọba ibilẹ ba le e fọwọsowọpọ pẹlu awọn araalu ati ẹgbẹ gbogbo to yẹ, ipenija abo yoo dẹkun ni kiakia. Kò sí ìyèméjì mọ́, Oduduwa Nation ni Yorùbá ń fẹ́ - Gani Adams Aarẹ Ọna Kakanfo tilẹ Yoruba, Iba Gani Adams tun ti sọrọ lori ipo ti eto aabo ilẹ Yoruba wa, to si ni arwo aabo to mẹhẹ ti dinku pupọ. O ni lootọ ni ewu si n waye lawọn agbegbe kan amọ aabo ti n gbopọn lawọn agbegbe kan yatọ si bo se n waye ni osu mẹta si mẹfa sẹyin. O ni pẹlu ajọsepọ awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ atawọn eeyan kan to n se ipade loore koore lori eto aabo yii, o ti n so eso rere. ""A ti kọ lẹta si gbogbo ọba nilẹ Yoruba, ti mo si fi ọwọ si lẹta naa eyi tawọn ọlọdẹ ati OPC fi ọwọ si pe ki wọn maa fi idunkooko to ba wa ni agbegbe wọn ransẹ. Atunto Naijiria la n fẹ - Aarẹ Onakakanfo, Gani Adams O ni ọrọ eto aabo kii se ọrọ ariwo, amọ o yẹ ka bi awọn agbofinro wa pe se wọn setan pe ki aabo wa ni Naijiria ""Awọn agbofinro wa to n se ijamba feto aabo lo mu ki awọn eeyan maa fun idasilẹ Oduduwa, sugbọn ti wọn ba fọwọsowọpọ pẹlu araalu, eto aabo to mẹhẹ yoo dohun itan. Lori idasilẹ orilẹede Yoruba, Gani Adams ni Íbi ti Yoruba ba ti n lọ ni mo n lọ, ohun ti wọn ba fẹ, ni mo fẹ. Amọ o yẹ ki a beere pe nibo lawọn ọba atawọn oloselu wa n lọ nitori emi gan fẹ orilẹede Oduduwa. Wakili tẹẹ rí yẹn kìí ṣe ẹran rírọ̀, ó ń díbọ́n ní o - Iba Gani Adams Awọn ọjọgbọn kaakiri agbaye ni Odududwa Republic ni awọn n fẹ. Laelae n ko ni jẹ ọta Yoruba, a si ti se ipade lori ayelujara, to si foju han pe Oduduwa Republic ni awọn eeyan wa n fẹ."" Anfaani Oduduwa Republic ree: Laarin ọdun mẹwa, ọrọ aje Yoruba yoo ru gọgọ, nitori Ọlọrun fun wa ni ọpọlọ pipe, ti idagbasoke nla gidi yoo si wa fun ilẹ Yoruba. Iwa ijiyin isẹ iriju ẹni yoo pada sinu ilana isejọba wa, ti eto aabo to gbopọn yoo si wa nigba ti iwa ajẹbanu yoo dinku Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Tẹlẹtẹlẹ, ko si ole jija nilẹ Yoruba amọ ọdun 1975 ni idigunjale bẹrẹ, eyi ti yoo dinku pupọ, ti orilẹede Yoruba ba wa. Nigba to n sọrọ lori awọn eeyan wa to wa loke ọya, Adams ni ka to gba orilẹede oodua, ko nilo kawọn eeyan wa loke ọya wa sile tabi kawọn ẹya miran kuro nilẹ Yoruba. O fikun pe ohun to le mu akude wọ agbekalẹ orilẹede Oodua ni aala ilẹ amọ o ni Ọlọrun ti se eyi funra rẹ nitori aala wa ti wa tipẹ. Kò sí ìgbà kankan tí Yorùbá jókòó pé ki Igboho lọ kéde ìyapa kúrò ní Nàíjíríà A le joko si tabili lati pin Naijiria Aarẹ ni dandan kọ ni ki ogun waye, ka to pin kuro ni Naijiria, a le joko sori tabili, ka si pin Naijiria si wẹwẹ O pe mi ki n jẹ ọrẹ iran mi ju ọrẹ awọn aninilara lọ Iba Gani Adams wa fọwọ jaya pe oun ko ni tako nnkan ti Yoruba ba n fẹ nitori ẹni to ba n se ọta ilu maa n ge ika jẹ gbẹyin ni. O wa rọ awọn ọba alaye nilẹ Yoruba lati fọwọsowọpọ pẹlu iran Yoruba lati ri daju pe ohun ti wọn n pohungbẹ tẹ wọn lọwọ. Bakan naa lo ni oun ko ni sọrọ abuku si ọba kankan amọ o yẹ kawọn ọba naa tete maa se ohun tawọn eeyan wọn ba n fẹ. Lori eto aabo, Adams ni inu ọgba ẹwọn ni onikaluku wa nitori eto aabo to mẹhẹ. O ni wọn ran Kọmisana ọlọpaa wa sipinlẹ Oyo ni, ki ọga ọlọpaa patapata tete gbe kuro Igbesẹ gbigbe awọn",0,yoruba RT @user: @user ninu telifisoni leti yaaa o. Eleyi ko bojumu to. Sewon ko fun yin laye lati wole ni?,0,yoruba ti Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba "Saraki ati Dogara ni awọn lọpaa ti n toju bọ ọrọ oṣelu Awọn aṣofin mẹjọ ninu ọgbọn aṣofin to wa nile igbimọ aṣofin ipinlẹ Benue bẹrẹ igbesẹ ati yọ gomina ipinlẹ, Samuel Ortom nipo lẹyin ti wọn se awọn aṣofin mejilelogun yoku mọ ode gbagede ile aṣofin ipinlẹ naa. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ninu atẹjade kan ti Saraki ati Dogara jumọ fọwọ si, wọn ke si aarẹ Mohammadu Buhari lati ke si ileeṣẹ ọlọpaa pe ko tọwọ ọmọ rẹ bọ aṣọ, ki wọn si yee sọ ara wọn di ohun elo fun dida ilana iṣejọba tiwantiwa ru. ""Olori ile naa tẹlẹ ti wọn ti rọ loye, Terkimbir Ikyange ko awọn aṣofin meje miran sodi lati fi iwe iyọninipo ranṣẹ si Gomina Samuel Ortom"" ""A ti boju wo ohun to n lọ nipinlẹ Benue daradara nibi ti olori ile naa tẹlẹ ti wọn ti rọ loye, Terkimbir Ikyange ko awọn aṣofin meje miran sodi lati fi iwe iyọninipo ranṣẹ si Gomina Samuel Ortom, nigba ti ti wọn ko faaye gba awọn aṣofin mejilelogun ti wọn pọ julọ ninu ile naa lanfani ati wọ gbagede ile aṣofin ipinlẹ ọhun. A gbagbọ pe iwa arufin patapata ni eyi ko si ba ilana ti ofin la kalẹ fun awọn aṣofin lati gunle fun yiyọ gomina mu."" ""Bakan naa ni o tun jẹ iyalẹnu pẹlu ipa ti awọn ọlọpaa n ko ninu ilana arufin yii. Igbagbọ wa ni pe, ẹka aṣofin ni wọn n ta ẹrẹ ba lori ọrọ yii. Eyi si tun ṣe akawe bi wọn ṣe n lo ọlọpaa lọna aitọ lati fun ọrọ oṣelu lorilẹede yii.""",0,yoruba ọdún ń kanlẹ̀kùn á bá wa láyé àti láàyè ara,0,yoruba Eḳọ tí a ní nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò.,0,yoruba we caught them young with ranging from ta ló wà nínú ọgbà náà to ẹyẹ mélòó tolongo wáyé believe me they didnt want anything more àwọn ọmọdé àti eré ṣíṣe,0,yoruba "Ileeṣẹ to n ri si eto ilera lorilẹede Naijiria ni pẹlu ajọṣepọ ajọ agbaye to n ri si eto ilera WHO, Naijiria ti ni ibudo to lee kapa ṣiṣe ayẹwo ẹni to ba ko aarun aṣekupani Coronavirus eyi to bẹrẹ lorilede China. Minisita wa lo oju opo itakun Twitter wọn lati fun pe si ẹnikẹni lorilede Naijira to ti lọ si China ni oṣu bii melo sẹyin lati ""ya ara wọn s'ọ́tọ̀ na fun ọjọ́ mẹ́rìnlá ki wọn si pe ajọ to nṣamojuto kikoju aarun NCDC lori nọmba 07032864444. Bakan naa wọn tẹnu mọ ọ pé ẹnikẹni to ba ti ri i pe oun ni iba, ikọ, ọna ọfun n dun un ati inira lati mí, ki o tete lọ si ileewosan to ba wa ni tosi rẹ. Ehanire gba gbogbo awọn oṣiṣẹ eleto ilera niyanju pe bi wọn ba ṣe n tọju awọn to ba wa, ki wọn maa fun wọn ni iboju, ki wọn si ya wọn sọtọ ki wọn to kan si ajọ NCDC. O ti le lọdunrun-un eeyan to ti dero ọrun bayii nipasẹ aarun coronavirus eyi ti ọpọ ninu wọn wa lati ẹkun Hubei ni Wuhan. Ọkunrin kan ti gbẹmi mi lorilẹede Philippines lẹyin to lugbadi aarun Coronavirus to n ran kaakiri agbaye bayii. Ọmọ orilẹede China ni ọkunrin naa, ẹni ọdun mẹrinlelogoji, ọmọ ilu Wuhan to wa lẹkun Hubei ti aarun Coronavirus ti bẹrẹ ni ọkunrin naa ti wa. Ajọ to n ri si eto ilera lagbaaye, WHO ṣalaye pe o dabi ẹni pe ọkunrin naa ti lugbadi aarun Coronavirus ko to rinrin ajo lọ si orilẹede Philippines. O ti le lọdunrun un eeyan to ti dero ọrun bayii nipasẹ aarun coronavirus eyi ti ọpọ ninu wọn wa lati ẹkun Hubei ni Wuhan ti aarun naa ti bẹrẹ. Eeyan to le lẹgbẹrun un mẹrinla lo ti ni aarun coronavirus bayii kaakiri agbaye. Ẹwẹ, ọrọ di bo o lọ, o ya a mi nile iwosan kan ni Wuse niluu Abuja lọjọ Abamẹta lẹyin tawọn eeyan marun un kan parọ pe awọn ti ko aarun coronavirus. Awọn eeyan naa ti orukọ wọn jẹ Peggy Shandi, Abayomi Adedoyin, David Enemigin, Priscilla Ajesola ati Jacob Oji ṣe idiwọ fun ilera nile iwosan naa. Agbẹnusọ fun ile iṣẹ ọlọpaa l'Abuja, DSP Anjuguri Manza ṣalaye pe awọn eeyan naa yoo foju ba ileẹjọ ẹjọ lẹyin tawọn agb ofinro ba pari iṣẹ iwadii wọn tan. Akọwe iroyin fun minisita olu ilu Naijiria, Ọgbẹni Anthony Ogunleye sọ ninu atẹjade kan pe oludari eto ilera niluu Abuja, Dokita Josephine Okechukwu ti fọkan awọn ara ilu Abuja balẹ pe ko si ohun to jọ aarun coronavirus l'Abuja.",0,yoruba "Ajani Godwin Babalola ẹni ọdun mẹtadinlọgọrin, to jẹ aluduru ninu ijọ African Church ti ṣalaye fun BBC Yoruba bi igbe aye rẹ ṣe yi pada lẹyin ọpọ ọdun to ti n ṣiṣẹ fun ọlọrun. Baba agba naa ti ijọ ọhun kọ ile fun ni ile tuntun naa jẹ iyalẹnu nla fun oun. O ni awọn elere aye kan loun n tẹ gita fun tẹlẹ ki oun to pẹyinda bẹrẹ si n lo ẹbun oun fun Oluwa. Ninu iriri rẹ, o ni igba ti oun bẹrẹ si n lo gbogbo akoko oun fun duru titẹ ninu ile Oluwa loun padanu owo ti oun n ṣe tẹlẹ, to fi mọ iyawo oun atawọn ọrẹ kan, amọ ni igbẹyingbẹyin, ayọ lo pada ja si fun oun. Nigba to n sọrọ, alufaa ijọba ti babalola ti n ṣiṣẹ sin Ọlọrun, Pasitọ Adebayo Olujimi sọ pe Ọlọrun lo fi si oun lọkan ki wọn da ọkunrin naa lọla. Olujimi sọ pe asiko ti baba naa n ṣe ọjọ ibi lawọn gbero lati ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ naa fun ki inu rẹ le dun amọ Ọlọrun ni eto rere miran fun baba oniduru ọhun ju ero ti awọn ni lọkan. Ọkan lara awọn to kọ gbero bi wọn ṣe kọ ile naa, Olusesan Akinpelu ni asiko ti wọn n gbero lati ṣe akara oyinbo nla kan fun baba ni ẹnikan ninu igbimọ ti wọn gbe kalẹ fun eto naa sọ pe o san ki wọn kọ ile fun baba ju ki wọn ṣe akara oyinbo fun lọ. Gẹgẹ bii ohun ti Olujimi sọ, ile oniyara kan ni awọn kọkọ fẹ kọ tẹlẹ, amọ wọn yi ero awọn pada, ti wọn si kọ ile oniyara meji fun baba, eyii ti wọn pe orukọ rẹ ni “Bethel House.” Lori bi inu rẹ ṣe dun to lori ile naa, Babalola sọ pe ayọ oun ko lohunka. O ni ile ọhun da bi igba ti eeyan ba kuro ninu ile eku si aafin ọba lo ri loju oun. Baba Babalola wa gba awọn eeyan to n ṣiṣẹ sin Ọlọrun lamọran pe ki wọn ni suuru nidi iṣẹ naa, ki wọn si maa fi ọkan kan ṣiṣẹ ọhun.",0,yoruba Lílé ► ṣákítí bọ̀bọ́. Egbè ► bọ̀bọ́. L ► Ìdí ò gba póò. E► gba póò. L► t'ó bá gba póò. E► gba póò. L ► póò á fàya. E► fàya. #OjoEwe #Yoruba,0,yoruba Damola Olatunji fojú balé ẹjọ́ lórí ẹ̀sùn pé ó dúnkookò mọ́ ọlọ́pàá àtàwọn ẹ̀sùn míì,0,yoruba "Goodluck: Ṣèbí ajagunfẹ̀yìntì ni Buhari, o yẹ kó mọ ohun tó yẹ láti kápá ìpèníjà ààbò",0,yoruba dé sí ìbàdandun láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa òkè: ti o ní wúlò.,0,yoruba Ó tẹ̀síwájú pé “ ọ̀nà tó dára jùlọ láti mọ rírì ipa ribi - ribi tí àwọn òsìsẹ́ ń kó láwùjọ ní láti mójútó ètò ìgbáye - gbádùn wọn .,0,yoruba "#Yoruba Yoruba people please help me find this song! @user Jumpe jumpe o jumpe Ebami pe omo yi, ko wa sumi re A pe omo, omo ko, omo ko sumire Jumpe Omi ko pa ina, Ina ko Ina ko Jo igi, igi ko Igi ko na aja, aja ko Aja ko ge omo, omo ko Omo ko sumi re https://t.co/56g7DgfGNR",0,yoruba lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó ṣe pàtàkì.,0,yoruba "Ọ̀jọ̀gbọ́n Jerome ré s'álákeji lójú ìbọn àwọn afurasí agbébọn Iroyin taa gbọ ni pe oloogbe naa n dari pada lọ sile lati ile iwe fasiti Ambrose Ali (AAU) nibi to ti lọ ṣamojuto idanwo awọn akẹkọọ ẹ̀ka iṣegun oyinbo to n ri si itọju awọn ọmọde. Fasiti Obafemi Awolowo kede ipapoda oloogbe Ọjọgbọn loju opo Twitter wọn pẹlu ọkan wuwo. Content is not available End of Twitter post, 1 Iroyin tun sọ pe awọn agbebọn da a lọna lopopona Benin si Auchi laarin ilu Iruekon ati Ekhor ti wọn si ṣina ibọn bolẹ si ọkọ rẹ ko tilẹ to lee sọ pe oun fẹ duro. Adetoun Ogunṣẹyẹ: ìrìnàjò ẹ̀kọ́ mi títí dé òkè kò rọrùn rárá Wọn ni loju ṣe ni oloogbe faye silẹ ti awakọ rẹ si fara pa yanayana latari awọn ọta ibọn ti wọn yin lu wọn. Ẹwẹ, ẹka ẹgbẹ awọn onimọ iṣegun oyinbo ti ipinlẹ Edo banujẹ gidi gan an si iṣẹlẹ ibanujẹ yii. Ninu ọrọ ti alaga ẹgbẹ naa ni ipinlẹ Edo, Dokita Valentine Omoife fọwọ si, wọn bu ẹnu atẹ lu iṣoro aabo atawọn iṣẹlẹ aidaa miiran tawọn oniṣẹ ibi n ṣe lorilẹ-ede Naijiria. Brain Squad: Àwọn ọmọdébìnrin Nàìjíríà ṣe ""App"" ìrànwọ́ owó iléèwè Ẹwẹ, ẹgbẹ awọn onimọ iṣegun oyinbo ni ipinlẹ naa ni awọn ti kọ́ lẹta ranṣẹ si Gomina ati Kọmiṣọnna Ọlọpaa ipinlẹ Edo ti kọ iwe ranṣẹ si ile iṣẹ Ọlọpaa ipinlẹ lati ri aridaju aabo fun ẹmi awọn ọmọ ẹgbẹ wọn to ku. Akure Kidnap: Àwọn abiyamọ fẹ̀hónúhàn lórí ọmọ tí wan jígbé nílé ìjọsìn Akurẹ",0,yoruba "Ijọba apapọ Naijiria ni o yẹ ki wọn tun iwe asẹ ẹgbẹ oselu PDP gbeyẹwo Eyi ko si sẹyin ọrọ ti minisita feto iroyin lorilẹede Naijiria, Lai Mohammed, sọ nilu Eko lasiko to n ba awọn akọroyin sọrọ lori igbesẹ to waye lati tu awọn akẹkọ Dapchi silẹ. Nibẹ ni Alhaji Lai Mohammed ti ni oun to buru jọjọ ni pe ẹgbẹ oselu PDP ti ọwọ oselu bọ wahala awọn ọmọ Dapchi naa, Muhammed ni "" Asiko ti to fun atungbeyẹwo ilana fun gbigba iwe asẹ iforukọsilẹ fun awọn ẹgbẹ oselu bii PDP, ti wọn ti fidirẹmi yala gẹgẹ bii ẹgbẹ oselu to n sejọba ni abi eyi to n se atako."" Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Lai Muhammed tun yannana ọrọ kan, ti aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari sọ, lasiko to fi n gbalejo awọn akẹkọ Dapchi nilu Abuja. O ni gẹgẹ bii aarẹ Buhari ti wi ""ijọba ko ni faye gba ẹnikẹni tabi ẹgbẹkẹgbẹ to fẹ maa fi oselu se ọrọ aabo lorilẹede yii. Nitorinaa, awọn ileesẹ alaabo ko ni tiju ati fi panpẹ ofin gbe awọn kọlọransi bẹẹ."" APC, PDP n tahun si ara wọn lori bi nkan se ri lori ijinigbe ati idapada awọn akẹkọ Dapchi Amọsa, ẹgbẹ oselu PDP ti fesi si ọrọ yi,i ti wọn si ni, ara ọgbọn ti ẹgbẹ oselu APC n da lo n farahan yii, lọna ati rii daju wi pe, ni dandan, Aarẹ Buhari dije gẹgẹbii oludije alailatako lọdun 2019. Ẹgbẹ oselu PDP ninu atẹjade kan salaye wi pe, ti a ba ni ka da-a silẹ ka tun un sa, ẹgbẹ oselu APC ti ko ni igbimọ majẹobajẹ, ni ibamu pẹlu ofin ẹgbẹ oselu naa, lẹyin ọdun marun gan an lo yẹ ki wọn gba iwe ẹri lọwọ rẹ. ""A fẹ mu u wa si eti igbọ awọn ọmọ orilẹede Naijiria wi pe, ọgbọn alumọkọrọyi ni ijọba apapọ, ti ẹgbẹ oselu APC n sakoso rẹ n gbimọran rẹ, lati gbogun ti awọn ẹgbẹ oselu alatako ki wọn si lee yẹna fun oludije wọn, Mohammadu Buhari, lati dije gẹgẹbii oludije ti ko latako.""",0,yoruba jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ẹkọ́: ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba Ìlú tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "Nígbà tó kún jú, àwọn ènìyàn ni ó pa Alàji lo fi.",0,yoruba lo joko. A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn yì í tún ṣe àwọn iṣẹ́ tí ó ṣe pàtàkì.,0,yoruba owó money owó hand òwò business ówo boil ówō he looked owò broom òwò a town in ondo state ó wó it fell,0,yoruba "Igbimọ alaṣẹ fun eto ọrọ aje Naijiria ti fẹnuko lẹyin ipade wọn pe ki awọn olori awọn oṣiṣẹ alaabo lorilẹede Naijiria rii daju pe wọn n ṣe ayẹwo ọpọlọ ati ti oogun oloro fun awọn oṣiṣẹ wọn. Eyi wa lara abajade ipade wọn to waye lọjọ Ẹti eyi ti igbakeji aarẹ, Ọjọgbọn Yemi Osinbajo dari. Ninu ọrọ kan ti agbẹnusọ igbakeji aarẹ, Laolu Akande fi sita, o ni wọn gbudọ rii daju pe ilera ọpọlọ awọn eeyan wọn duro deede lati gbe ibọ̀n ati nkan ijagun. Ipade yii n waye ni ibamu pẹlu bi igbimọ naa ṣe rii pe awọn ọmọ Naijiria n gbero lati ṣe ayajọ iwọde ifẹhonuhan #EndSARS. Gẹgẹ bi ọkan lara awọn afẹhonuhan ṣe bere lọdun to kọja, igbimọ naa ni ki ijọba boju to alaafia awọn oṣiṣẹ eleto aabo. ""Igbimọ NEC n pe gbogbo awọn adari oṣiṣẹ eleto aabo Naijiria lati rii pe awọn ti wọn ba n gba si iṣẹ eyi ti wọn yoo ti maa gbe ibọn lati ṣe ayẹwo ọpọlọ ati ti oogun oloro"". Lẹyin ti wọn ba gba wọn wọle tan, igbimọ naa tun ni ki wọn maa ṣe ayẹwo ọhun loorekoore lẹnu iṣẹ. Igbimọ naa rọ ijọba Naijiria lati faaye silẹ fun igbeaye alafia awọn ọlọoaa atawọn oṣiṣẹ alaabo Naijiria. Ni pato, wọn pe fun ṣiṣe ayẹwo owo oṣu awọn oṣiṣẹfẹyinti to jẹ ọlọpaa ati riri owo awọn to wa lẹnu iṣẹ gba lasiko to yẹ. Bakan naa ni igbimọ yii tun gba awọn oṣiṣẹ alaabo ni imọran pe ki wọn maa tẹle ofin ti wọn fi gba wọn siṣẹ lasiko ti wọn ba wa lẹnu iṣẹ lagbegbe ibi ti wọn pin wọn si tabi nita. Nigba to n fun 'pe si awọn oṣiṣẹ alaabo lori ọgbọn amulo lati gbogun ti iwa ọdaran, igbimọ naa ni ki awọn ọlọpaa wa ni ibamu pẹlu ohun ti wọn pese latara ikọni abala ofin ileeṣẹ ọlpaa fun dun 2020. O ni ṣiṣe ikọni ati idanilẹkọ fun awọn ọlọpaa ṣe pataki fun iṣẹ wọn. Lafikun, igbimọ NEC ni awọn eeyan ti wọn timọle nitori iwọde EndSARS wa ni ibamu pẹlu ofin to de gbigbọra ẹni ye. O fi kun un pe wọn ni lati rii pe ilana ti wọn fi lelẹ laarin ileeṣẹ Ọlọpaa Naijiria lati maa fi yanju ẹsun ti awọn araalu ba mu wa kun oju osuwọn ki awọn ọlọpaa to ba ti wa lẹnu iṣẹ si maa wọ aṣọ. wọn pẹlu lilẹ orukọ wọn mọ aya.",0,yoruba "ìwájú. Alàji lo ni ìgbà mi owó àkokò, Ọmọ lo ni iwa rere lojiji.",0,yoruba bí ẹ̀dá bá fẹ́ gba àwìn ẹ̀bà ni wọ́n máa ńṣe ojú àánú tí wọ́n bá yó tán wọ́n á di ọkọ olúwa wọn,0,yoruba mú yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó wáyé..,0,yoruba "Arábìnrin Oluremi Adeleye Adeleye ẹni ọdún mẹ́tàléláàdọ́rin bú sẹkún nilé ẹjọ pé oun tọrọ aforiji nítori pe àṣìṣe ni kìí ṣe pé oun mọ̀ọ́mọ́ pa ọmọ náà. Wọn fẹbi ẹ̀sùn ìpàniyan kan an ní inú oṣù keji ọdún pe ó fi tipatipa fún ọmọ oṣù mẹ́jọ̀, Enitan Salubi ni mílììkì mú ní tulàsì lágbegbe Glenarden ní inu oṣù kẹwàá ọdún 2016 ti ọmọ náà si gba ibẹ̀ lọ. Ẹri láti ara àwọn ayàwòràn kọ̀rọ̀ ti wọn ń lẹ mọle fi han pe Adeleye jẹ alágbàtọ ọmọ tó n ba wọn gbéle, O gbiyanju láti fún ọmọ náà lóunjẹ, sùgbọ́n ti ó kọ láti gba ounjẹ náà ti obinrin yii si da ọmọ náà dubulẹ láti fún un lóunjẹ. Oluwo: Mo lè jẹ Ọba ní Ile Ife Adajọ to gbẹ́jọ náà Karen Mason sọ pe bó tilẹ̀ jẹ pe oun ni igbagbọ pé Adeleye kìí ṣe ènìyàn burukú tí ó fẹ pa ọmọ sùgbọ́n ó yẹ ki ó mọ pé igbésẹ̀ náà le gba ẹmi ọmọ. Ọmọ Yoruba ni Oluremi Adeleye, dídá ọmọ kilẹ̀ sì jẹ aṣà láàrin awọn abiyamọ láti rii dáju pe ebi ò pa ọmọ.",0,yoruba "Arsenal vs man United: Láì tíì pé ọ̀sẹ̀ kan tó kéde akọ́nimọ̀ọ́gbá tuntun, Arsenal j'ojú Man U pẹ̀lú góòlù Mẹ́ta sí ẹyọkan ní Emirate",0,yoruba lòdì Àbẹ́òkúta. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba "20, 000 likes. E se gan o. Apapo omo Yoruba.🍉🥰🍉🥰🥰🔥👉 Yorùbátv ẸGBẸ ỌMỌ OLÚWA BÍ GBOGBO ÀGBÁYÉ Ojú òpó ìkànsíraẹni 🇳🇬🇹🇬🇧🇯🇧🇷🇨🇴🇨🇺🇬🇭🇨🇮______________________________□ Yoruba TV 🥰😘🔥 #yoruba #yorubatv #yorubaweddings #ebi… https://t.co/wfEqy7zT8j",0,yoruba "Nígbà tó kún jú, àwọn ènìyàn ni ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ài: ti o ní wúlò.",0,yoruba "Ẹ rò ó. Àgbẹ̀ ló ma yọ wá nílúu wa yìí. Kọ́mọ kàwé má rí'ṣẹ́ ṣe, àwé nǹkan jíjẹ sì ń tà wàràwàrà. #Ise #Agbe #Yoruba #Nigeria",0,yoruba "RT @user: Amin Ase Eledumare!!! """"""""""""""""@user: Ẹ ká alẹ́ o. A ò ní ráburú lọ́dún tuntun o.""""""""""""""""",0,yoruba "Ẹnu lẹbọ, ahọ́n ẹnu ń mú ni í là, òun náà ní í kó bá ni. Ẹ wòreré ayé kí ẹ ríi b'ẹ́nu ti í pa ni. #Enulebo #Yoruba",0,yoruba dídì yìí ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ẹkọ́: ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó ṣe pàtàkì.,0,yoruba ìyẹ̀ alẹ́. Èyí ni òun tí a ní nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Alàji lo joko.,0,yoruba "Ìkéde Shebuyeva àkọ́kọ́ nípa ètò náà fa ẹgbẹlẹmùkù èébú ìkórìíra - ìbálòpọ̀ - láàárín - akọ́ - àti - akọ nínú àwọn èsì , tí èsì sì wá láti ọ̀dọ̀ àwọn òṣìṣẹ́ ọba kan bákan náà , ṣùgbọ́n ìyẹn ò mú ọkàn - an rẹ̀ kúrò , ó sọ fún Novaya Gazeta .",0,yoruba "@user ... olè gbé e, olè gbà á. Ló bá tán!",0,yoruba "Orin naa ni: ""Awọn ẹda kan lo wa, ti wọn n fẹ ki ẹnikeji jẹ, iru wọn ni ti Fajemirokun, To fi owo mọ Oluwa, to tun fi mọ eniyan, ile isẹ rẹ, aimọye eniyan ni wọn n jẹ, ti wọn n mu."" Ti a ba n sọrọ okoowo ati isẹ aje, bi kanhun se jẹ ọga ni awujọ okuta, naa ni Henry Fajemirokun jẹ ọga lawujọ ọrọ aje lorilẹede Naijiria. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: A si lee se apejuwe Henry Fajemirokun bii atapata dide, to de ibi giga, lati ipasẹ okoowo eyi to yẹ kawọn ọdọ fi se awokọse rere. Gẹgẹ bi a se ka itan igbe aye akọni olokoowo naa loju opo Wikipedia lori itakun agbaye, Fajemirokun ko ipa ribiribi si agbega ọrọ aje lẹkun Iwọ Oorun ilẹ Afirika. Bi itan igbe aye rẹ si se lọ ree: Ibẹrẹ aye, eto ẹkọ ati isẹ oojọ ti Henry Fajemirokun se: Oladapo Adu: Nàíjíríà já mi kulẹ̀ torí wọn kò wá gbé mi 'Báyìí la ṣe rìn ín láti pápákọ̀ òfurufú Abuja sí Eko bí ìrìnà òfurufú abẹ́lé ṣe bẹ̀rẹ̀' Bí àrùn Coronavirus ṣe dá gbogbo àgbáyé gúnlẹ̀ sójú kan náà nìyí Fọwọ́ kan obìnrin lọ́nà àìtọ́, kí o rẹ́wọ̀n ọdún mẹ́rìnlá he- Àwọn aṣòfin yarí Kò ní sí ayẹyẹ ọdún Ojúde Oba lọ́dún yìí- Awujale ilẹ̀ Ijebu Awọn okoowo nlanla ti Henry Fajemirokun dawọle: Mama Arsenal: Màmá àgbà yìí máa ń lọ sí ìbùdó tí wọ́n ti ń wo bọ́ọ́lù láti wòran Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ Bi ileesẹ Fajemirokun se gbọrẹgẹ-jigẹ: Itan Omi Erin Kemi Dairo: Iṣẹ́ abẹ nínú ọpọlọ àti ẹ̀rọ ni mo fi ń gbọ́ ọ̀rọ̀ báyìí Awọn ipa manigbagbe ti Henry Fajemirokun ko si iranwọ ọmọniyan: Ẹ̀mí kan náà ló n darí ìrìnàjò wa táa fi jọ kọ́lé papọ̀- Ìbejì Awọn oye ati ami ẹyẹ ti wọn fi da Henry Fajemiloku lọla: Idile Henry Fajemirokun: Baba ọlọla yii fẹ iyawo, oloogbe Comfort Oseboade Fajemirokun, ẹni to papoda lọdun 2019. Ọlọrun fi awọn ọmọ si aarin awọn mejeeji, lara awọn ọmọ rẹ ni ilumọọka olokoowo kan to kalẹ silu Eko, Dele Fajemirokun. Dele naa lowo bii baba rẹ, o lọla, to si jogun ileesẹ baba rẹ nilu Eko. Wo itan omi gbigbona ati tutu ni Ikọgosi Ekiti Iku Henry Oloyede Fajemirokun: Ẹni ọdun mọkanlelaadọta pere ni Henry Oloyede Fajemirokun nigba to lọ sọrun ọsan gangan. Yoruba ni ka ku ni ọmọde ko yẹ ni san ju ka dagba lai ni adiẹ irana lọ. Osu Keje, ọdun 2020 yii si ni oloogbe naa ko ba pe ẹni ọdun mẹrinlelaadọrun. BBC Yoruba wa gbadura pe Ọba oke yoo dẹ ilẹ fun oloore to lọ. Pẹlu imọran pe ki onikaluku tete ja itanna rẹ to n tan nitori a ko mọ igba ti ọlọjọ maa de. Awọn Obinrin Dahomey: Awọn obinrin ilẹ Afirika ti wọn yii itan pada re e",0,yoruba Pánẹ́ẹ̀lì Ìléfòó Òkè,0,yoruba owo ṣẹlẹ ni Eko ti gbogbo eniyan sọ o ṣe pataki. (1999),0,yoruba "A gbọ pe ikọlu naa bẹrẹ lagbegbe Odo-Osun lọjọbọ, ti o si tan de agọ ọlọpaa to wa ni Mapo. Eeyan meji ku ninu iṣẹlẹ naa gẹgẹ bi iroyin to tẹ wa lọwọ ti wi. Lọjọbọ ni awọn ọlọpaa mu awọn janduku meji kan ladugbo Odo-Osun nitosi Mapo. Bi awọn akẹgbẹ wọn ṣe ri pe ọwọ ti tẹ wọn, ni wọn gbiyanju lati fipa tu wọn silẹ lọwọ awọn ọlọpaa. Amọ ṣa, ọlọpaa ṣina bolẹ fun wọn ni agbegbe Odo-Osun ti eeyan kan si ku nibẹ. Lẹyin ikọlu ti Odo-Osun yii, awọn janduku taa n wi yi tun ṣigun lọ si agọ ọlọpaa to wa ni Mapo, lati fẹhonu han lori eeyan wọn kan ti o ku. Ninu wọdu-wọdu to waye nibẹ, awọn ọlọpaa tun yinbọn lati daabo bo agọ wọn, eeyan kan tun fara gbọta to si gba ibẹ ku. Ilorin Conjoined Twins: Àwọn òbí ìbejì tó lẹ̀pọ̀ ní ọ̀kàn àwọn bàjẹ́ láti rí ibèjì wọn tó Alukoro ọlọpaa ni ipinlẹ Oyo, Olugbenga Fadeyi fidi iṣẹlẹ yii mulẹ fawọn akọroyin ninu atẹjade kan to fi sita. O ni ''lẹyin tawọn ọlọpaa mu awọn janduku meji kan, arakunrin kan ti wọn n pe orukọ rẹ ni ''Packaging'' lewaju awọn janduku mii to to ọgbọn, lati ṣigun bo agọ ọlọpaa, ki wọn le tu akẹẹgbẹ wọn silẹ''",0,yoruba "Lara ipenija ipinlẹ Kaduna ni ikọlu darandaran.Okunrin yi'n nawo si ọkọ ti wọn so ina si labule Barkin Kogi lọjọ kẹrinlẹlogun osu keji ọdun 2017. Alukoro fun isẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Kaduna, Muktar Aliyu salaye fun BBC wi pe, ileesẹ ọẹọpaa si wa lẹnu iwadi lati mọ ohun to sokunfa wahala naa. Eniyan meje lo padanu ẹmi wọn ti awọn mẹẹdogun miran si tun fara gb'ọgbẹ nigba ti ija kan bẹ silẹ lagbegbe Kasuwan Magani ni ijọba ibilẹ Kajuru ni ipinlẹ Kaduna. Alukoro fun isẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Kaduna, Muktar Aliyu salaye wi pe, 'A o mo ohun to fa ija naa sugbọn a ti dẹkun rẹ. ""A si ti gbe igbesẹ ki wahala naa maa baa tan ka de awọn agbegbe miran ni ipinle yi."" Ọlọpa ni ko si ẹni lee sọ boya ọrọ ẹsin lo sokunfa wahala naa Biotilẹ jẹ wi pe awọn kan ti ọrọ naa soju wọn sọ fun BBC pe wahala bẹ silẹ nigba ti ọmọbirin ẹya Gwari kan yi ẹsin pada lati Kristẹni si Musulumi nitori ọrekunrin rẹ. Amọsa, ileesẹ ọlọpaa salaye wipe, ""A ko le fidi ọrọ yii mulẹ wi pe ayipada ẹsin eeyan kan lati Kristẹni si Musulmi tabi ẹsin miran lo da ija naa silẹ. ""Olukuluku lo ni ẹtọ lati se ẹsin to ba wu u. Eleyi ko yẹ ko fa ija rara"". Irin Kasuwan Magani si aarin gbungbun Kaduna to kilomita mẹrindinlọgbọn o si jẹ oju ọna ti eeyan le gba lọsi apa guusu Kaduna, Plateau, Nasarawa ati ipinlẹ Benue. Awọn iroyin miran ti ẹ le nifẹ si:",0,yoruba pa Ọba lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò.,0,yoruba "Awọn orilẹede bi i Turkey ati Malaysia n lo iru ilana ti Atiku Abubakar fẹ ẹ gba gbogun ti iwa ibajẹ. Ọjọru ni Abubakar sọ ọrọ naa nibi ipade itagbangba kan ti ajọ MAcArthur Foundation, ileeṣẹ amohunmaworan NTA ati Daria media pawọpọ ṣe nilu Abuja fun awọn oludije fun ipo aarẹ ati igbakeji wọn. Atiku: Màá foríji àwọn tó kówó ìlú jẹ́ tí mo bá di àárẹ ‘Ìjọba kò tẹ̀lẹ́ ìlànà òfin lòrí ọ̀rọ̀ Onnoghen’ Ṣugbọn ṣa, kini ilana ti Atiku fẹ lo lati gbogun ti iwa ibajẹ tumọ si? Onwoye nipa bi nkan ṣe n lọ ni agbo oṣelu Naijiria, to tun jẹ olupolongo tako iwa ibajẹ ninu ajọ Children Anti-corruption Initiative, Akinwande Ọmọlolu ṣe atupalẹ rẹ. ""O dara ti Atiku Abubakar ba le se bẹẹ."" O ṣalaye pe oun ti o tumọ si ni pe awọn to ti kowo ilu jẹ tẹlẹ yoo da a pada fun ijọba, ti ijọba yoo si na owo naa sori eto ọrọ aje Naijiria. Eyi dara ju ki ijọba o maa gbe wọn lọ sile ẹjọ lọ. Gẹgẹ bi ẹni to n polongo tako iwa ibajẹ, bi eto idajọ wa ṣe ri ko jẹ ki igbogun ti iwa ibajẹ o ṣaṣeyọri. ""O san ki ijọba ba iru ẹni bẹẹ duna-dura lati da owo naa pada, niwọn igba ti awọn miiran ko ni ko owo jẹ mọ, de bi ti iru eto bẹ yoo tẹsiwaju. Ọna ti ijọba le gba yanju eyi ni lati ṣe ofin pe ki gbogbo awọn osisẹ ijọba to fi mọ awọn to di ipo oṣelu mu lati maa kede dukia wọn, ki wọn to de ipo. Ayẹwo si gbọdọ maa waye lọdun maarun maarun lori awọn dukia bẹ ẹ"". O tẹsiwaju wi pe ""Mo gbagbọ pe a ko fi bẹẹ tẹle ofin to de awọn to di ipo iṣakoso mu ni Naijiria. Ijọba si le ṣe idasilẹ oju opo ti wọn o maa fi iru awọn nkan bẹẹ to araalu leti. Yoo mu ko soro fun wọn lati maa ko dukia jọ. Awọn ọmọ Naijiria yoo si le jẹ oye oju lalakan fi n sọri. Aarẹ Buhari ko ṣe to ninu igbogun ti iwa ibajẹ. Amọ o ṣeni laanu pe afojusun rẹ ti yẹ."" Ko buru ti a ba dan ilana ti Atiku fẹ ẹ gba gbogun ti iwajẹ wo, ka wo esi ti yoo fun wa. Ṣiṣe bẹ yoo ran ijọba lọwọ lati mọ iwọn dukia ti owo oṣu oṣiṣẹ kọọkan le ko jọ fun un. Ni Akinwande Ọmọlolu wi. ""Igbesẹ ti Atiku fẹ gbe yii lo dara fun Naijiria."" Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari gbe iru igbesẹ pe ki awọn to di ipo iṣakoso mu o maa kede dukia wọn, nigba to kọkọ de ipo. Kini awọn ọmọ Naijria n sọ lori ipinnu Atiku? Awọn ọmọ Naijiria loju opo Facebook BBC Yoruba kan gbagbọ pe ki Atiku kọkọ ko owo ilu to wa lọwọ rẹ silẹ naa, ko to gbe igbesẹ naa. Bakan naa ni awọn kan ni ọna to dara ni Atiku fẹ tọ̀ lati gbogun ti iwa ibajẹ. Awọn orilẹede bi i Turkey ati Malaysia n lo iru ilana ti Atiku Abubakar fẹ gba gbogun ti iwa ibajẹ.",0,yoruba Ìyá mú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba ọlọ́run fẹ. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìṣẹ̀: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn olórogun...,0,yoruba "Pásítọ̀ gún ìyàwó rẹ̀ lọ́bẹ nínú ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá tì í bọ ara rẹ̀ náà níkùn",0,yoruba "lọ, Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Nitori eyi, ara eni lo ni ẹ̀ká àwẹ eyti o gbe lori iwa rere.",0,yoruba emi na lowo si ati ma gba awon eeyan wa ni iyanju nipa ati ni itelorun pelu nkan tiwa awon agba bo won fiyewa wipe teni nte,0,yoruba "ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba o nuni ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo.,0,yoruba @user Team A lo mu igba oroke ni nu ere basketball ti gbogbo irawo ni Zenith Bank League fun awon obinrin. 🏀😁👍 #TweetinYoruba #ZenithWBL,0,yoruba "Iriri akọkọ arakunrin ẹlẹsin musulumi kan nigba ọdun keresi to fi soju opo Twitter ti di ohun tawọn eeyan n pin kaakiri. Mohammad Hussain, to n gbe ni ilẹ Canada pinu lati ṣe ọdun Keresi pẹlu awọn akẹgbẹ rẹ meji kan nitori isede to de wọn mọle. Ohun toju rẹ ri nigba Keresi akọkọ rẹ yi, paapa nipa gbigbin igi keresi ati didana ounjẹ Keresi fjẹ iyalẹnu fun un. Nitori naa lo fi ni ohun bẹrẹ si ni kọ nipa iriri yi soju opo Twitter-ibẹ lawọn eeyan ti bo bi igba ti eera bo ṣuga ti wọn si n pin kaakiri. Ni bayi ẹni ọdun marundinlọgbọn naa sọ pe oun n foju sọna de owurọ ọjọ Keresi akọkọ ti oun yoo ba wọn ṣe. O sọ fun BBC pe''Niṣe o n ṣe mi igba pe Harry Porter ni mi'' Ọgbẹni Hussain to ba wọn ṣe gbogbo pọpọsinṣin ọdun keresi- bi ka ba wọn ṣe apejẹ Keresi ni ọfisi tabi lilọ si ile ọrẹ rẹ laisun Keresi- ko lanfaani ati ṣe iru rẹ ri nitori idile musulumilo ti wa. Ajakalẹ Corona virus to de ju onikaluku mọle lo mu ki oun ati awọn alajijọgbe rẹ gbimọran lori ọna ti wọn yoo fi ṣe ọdun Keresi. Nigba ti eeyan kan s pe ki wọn da ina ounjẹ orisi mejila ni arakunrin Husdsain ni ko sa'buru nibẹ. ""Mo kan fẹ ran wọn lọwọ nipa ipalẹmọ ọdun Keresi ni'' Bi mo ti ṣe n wo wọn, mo ri pe wọn mọ iṣẹ yi ṣe ju mi lọ.Apẹrẹ iṣẹlẹ yi kan ni igba ti wọn n fi ohun ẹṣọ sara akaba ile, mi o ribi ṣe daada ṣugbọn ẹnikeji mi yara ṣe tiẹ'' Gbogbo awọn nkan to ri nipa ipalẹmọ Keresi yi lo fi soju opo rẹ ni Twitter, kia lawọn eeyan ti ṣalabapin rẹ niye igba to le ni 100,000 Lẹyin ti awọn eeyan bẹrẹ si ni pin ọrọ to kọ yi ni ọrẹ rẹ kan mu imọran wa pe ki o fi oju opo awọn ajọ ẹlẹyinju aanu sibẹ ki awọn eeyan baa le da owo fun wọn. O gba imọran yi ti wọn si ko owo jọ fun awọn ẹlẹyinju aanu meji to n pese ounjẹ, Milton Halal Foodbank ati Parkdale Food Centre. ''Iyalẹnu lo jẹ si mi'' ati pe ''eeyan pupọ lo ti n ta awọn alaini lọrẹ, awọn eeyan n sọrọ daada nipa igbiyanju wa'' Mohammad sọ pe oun n foju sọna di igba ti oun yoo ba awọn akẹgbẹ rẹ sọju Musulumi to si ni o ṣeese ki oun wa baba keresi ti yoo fun wọn lẹbun ni igba naa. Lara ohun ti wn la kalẹ lati ṣe ni ọjọ Keresi ni pe wọn yoo dana orisisi ounjẹ mejila ti wọn yoo si jijọ ṣere kaadi tita nitori iṣede to wa nita Kini kan ti Mohammad ni o n jẹ iyalẹnu fun oun ni bi awọn eeyan ṣe n duro lati tu ẹbun wọn ti wn ko kalẹ ''Diduro de asiko ti a o tu ẹbun wa n ṣemi bakan.Sẹbi awọn ẹbun naa lo wa niwaju wa yi?'' Awọn alabagbe rẹ sọ pe awọn yoo ṣi awọn ẹbun kan laisun ọjọ Keresi tawọn yoo si ṣi eyi toku lowurọ ọjọ Keresi.",0,yoruba "#sundayseries The Yorùbá word """"""""""""""""Àlàáfíà"""""""""""""""" has 5 syllables and 5 tonal sounds (do-do-mi-mi-do) cc alamoja.yoruba #sọ́ndèàmì #sọ́ndèsílébù #ojọ́àìkú #learnyoruba #tonalsound… https://t.co/GaefXiy176",0,yoruba "Kọmiṣọnna fun ọrọ abo abẹle nipinlẹ Kaduna, Samuel Aruwan ṣalaye pe awọn agbebọn ọhun di oju ọna lẹba abule Kadanye lagbegbe Kajuru. Ọgbẹni Aruwan sọ pe nibẹ ni wọn ti dabọn bo ọkọ bọọsi akero kan ati ọkọ akẹru to ko igi idanam wọn si yinbọn pa eeyan marun un lẹsẹ kẹsẹ. Awọn kan tiẹ sọ pe wọn tun ji ọpọ eeyan gbe ninu iṣẹlẹ naa. Bakan naa ni Kọmiṣọnna fun ọrọ abo abẹle nipinlẹ Kaduna ṣalaye pe ni abule Akilbu ati Inlowo lagbegbe Kachia lawọn agbebọn ti yinbọn pa awọn eeyan mii. Bakan naa lo sọ pe ọgọsan maalu ni wọn tun jigbe lọ ni gaa awọn darandaran to wa lagbegbe naa. Ọgbẹni Aruwan tun fidi rẹ mulẹ pe awọn ọlọpaa dena ikọlu mii ti ko ba tun waye loju ọna Kaduna si Birni Gwari lagbegbe Buruku. Awọn ọlọpaa yabo ibi tawọn agbebọn ọhun ti fẹ ṣọṣẹ nibi ti wọn ti doju ija kọ ara wọn ti awọn janduku naa si fẹsẹ fẹ. Eeyan meji, Fahad Lawal ati Usman Shehu ni wọn doola nibẹ, awọn mejeeji si n gba itọju nile iwosan bayii. 'Bí ojú ọ̀nà agbàrá òjò tí ijọba ṣe n'IIorin ṣe ń pa àwọn ọmọ iléèwé wa rèé! Ẹ sàánú wa'",0,yoruba "Aarẹ orile-ede Naijiria, Muhammadu Buhari lọ sọ ọrọ yi di mimọ nibi ipade apero eto ọrọ aje l'agbaye ni ẹkun Middle East ati North Africa to n waye ni Amman lorileede Jordan. O ni awọn ọmọ ogun orileede Naijiria ti gba gbogbo agbegbe ti Boko Haram gba lọdun 2014 pada lọwọ wọn. O ṣafikun pe ijọba ohun ti doola ẹmi awọn ti Boko Harm ko ni panpẹ mọra. Ọrọ rẹ yi n waye lasiko ti ipenija aabo ti ṣe n koju awọn ipinlẹ kọọkan lariwa Naijiria bi Zamfara ati Kaduna. Bo tilẹ jẹ wi pe Boko Haram ko lagbara to titẹlẹ mọ, ko ti si aridaju wi pe ijọba ti ribi yọ ọwọ wọn lawo patapata. Aarẹ Buhari ninu ọrọ rẹ tubọ salaye pe aisi anfaani eto igbayegbadun ati aikari mudunmudun eto ọrọ aje lo mu ki ipenija aabo ma peleke si lagbaye . O ni lorile-ede Naijiria, ijọba sapa lati mu irọrun ba awọn eeyan pẹlu ipese awọn eto kan eleyi to mu ki Naijiria ṣi sii fun karakata pẹlu awọn orile-ede miran.",0,yoruba ọ̀gbọ́n. Ọmọ lo ni ẹ̀ká àwẹ eyti o gbe lori iwa rere.,0,yoruba Oloye Bode Akindele lasiko aye rẹ jẹ ilumọọka oniṣowo ti o si tun jẹ Parakoyi ti ilu Ibadan. Sun re o 💓❤️🙏🙏 ibadanslayers #ibadan #yorubamovies #yorùbáculture #ibadanentrepreneurs #yoruba #oduduwa #oyo #religionyoruba https://t.co/MYxG4B8xnD,0,yoruba "fè fi, Nitori eyi, ara eni lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..",0,yoruba "Aarẹ Buhari ati Atiku Abubakar Atiku sọ eyi lasiko to n fesi ọrọ ti ẹgbẹ oselu APC sọ wi pe ko tọ ọ si lati dije dupo aarẹ lorilẹede Naijiria nitori ilẹ Cameroon lo ti wa, ti kii si i se ọmọ Naijiria. Oludije lẹgbe oselu PDP wa ni ara lo n ta ẹgbẹ oselu APC ati wi pe agbẹjọrọ oun ni ẹlẹjọ wọn ni ile ẹjọ. Ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress (APC) lo fi ọrọ lede wi pe oludije fun ẹgbẹ oṣeluPeoples Democratic Party (PDP), Atiku Abubakar kii ṣe ọmọ bibi orilẹede Naijiria. Eyi lo n fa ibeere ati ọpọlọpọ esi ti awọn ọmọ Naijiria n fi sita lori ẹrọ ayelujara lati igba ti ọrọ yii ti ti ẹnu ẹgbẹ oṣelu APC jade si Atiku Abubakar. APC ni aridaju akọsilẹ wa pe ni ọjọ kẹrindinlọgbọn oṣu kọkanla ọdun 1946 ni wọn bi Atiku Abubakar ni ilu Jada ni Adamawa, iha ariwa Cameroon. Bí o ṣe lè fí òǹkà, ọ̀mọ̀ ìka tàbí ìkúùkù wọn oúnjẹ́ APC ni nitori eleyii, ipẹjọ ti Atiku Abubakar fi sọwọ si ile ẹjọ to n gbọ ẹsun awọn to di ipo nla mu ko lẹ nilẹ ati pe ko tilẹ tọ si Atiku lati du ipo ninu idibo orilẹede Naijiria nitori ọmọ orilẹede Cameroon ni. Ajọ INEC kede aarẹ Buhari gẹg bi ajawe olubori plu ibo 15,191,847 eyi to fi fi ẹyin alatako rẹ, Atiku janlẹ to ni ibo 11,262,978 ṣugbọn ṣe ni Atiku kọjalẹ to si pe ẹjọ lori pe oun lo yẹ ko jawe olubori. Ọ̀dọ́kùnrin tó kọ́kọ́ ṣe ẹ̀rọ tó ń tu ìyẹ́ lára adìyẹ Wọn ni igba awọn oyinbo amunisin, orilẹede Germany lo n dari orilẹede Cameroon nigba naa ko to di ẹyin ogun ti orilẹede naa yapa. Ilẹ Faranse n dari apa kan nigba ti ilẹ Gẹẹsi n dari apa keji labẹ akoso Naijiria. Wọn ni eyi ja si wi pe ọdun 1961 ni apa ibi ti Atiku Abubakar ti wa dara pọ mọ orilẹede Naijiria. ""Nitori naa a duro lori pe gbogbo ibo ti Atiku ni lasiko idibo, ofo lasan ni"". Ṣugbọn ibo ti oludije wa daju ko si si eru ninu idibo naa"" gẹgẹ bi APC ṣe sọ ọ ninu esi wọn.",0,yoruba "Orúkọ tí a ma ń pe ọba Òsogbo ni, ÀTAỌJÀ ÌLÚ ÒSOGBO. The title of the king of Òsogbo is, ÀTAỌJÀ of Òsogbo (Ọ̀SUN STATE).",0,yoruba Parí òwe yìí ► etí kan ò yẹ orí; ... #Ibeere #Yoruba,0,yoruba """"""""" Ẹ̀rọ ìgbéròyìnjáde ń yí bí a ti ṣe ń ṣe nǹkan padà , síbẹ̀síbẹ̀ ẹ̀rọ - ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ ṣì ni ó ṣì wúlò jù lọ fún ọ̀gọ̀rọ̀ ènìyàn láti gbọ́ ìròyìn ohun tí ó ń lọ lọ́wọ́ , òhun ṣì ni ohun èlò tí ó máa ń lapa tí ó pọ̀ jù nínúu gbogbo ọ̀nà tí àwọn oníròyìn máa ń lò nítorí ó",0,yoruba "ni ara eni lo ni ìgbà mi owó àkokò, Alàji lo lọ.",0,yoruba "Àwọn ìpín kejì Super Eagles tí wọ́n ń gbá bọ́ọ̀lù jẹun lórílẹ̀èdè Nàìjíríà ni wọ́n kópa nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà Ami ayo meji pere si ni Super Eagles ti orilẹede Naijiria ni. Ifẹsẹwọnsẹ naa jẹ idije ife ẹyẹ Gotv cup, eyi ti wọn fi n ṣe igbaradi fun ikọ keji Super Eagles ti wọn jẹ agbabọọlu ti wọn n gba bọọlu jẹun lorilẹede naijiria. Ọmi alayo kọọkan ni wọn fi pari abala akọkọ ifẹsẹwọnsẹ naa, lẹyin ti Kelechi Nwakali ti kọkọ gba ayo wọle fun orilẹede Naijiria, ti Angel Correa si daa pada fun ikọ Athletico nigbati ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju mejilelọgbọn. Fernando Torres to wole ni abala keji ifẹwọnsẹ naa, lo yi oju ayo pada fun Athletico lẹyin to fi ori gbe ayo kan wọle, eleyi ti ipa aṣọle orilẹede naijiria ko si ka. Iṣẹju marun pere lo ku ki ifẹsẹwọnsẹ naa o pari, ti agbabọlu Athletico, Borja fi gba goolu kẹta wọle Amọ ṣa, ki a to ṣẹju pẹ ni Usman Mohammed tun daa pada fun ikọ Super Eagles. Iṣẹju marun pere lo ku ki ifẹsẹwọnsẹ naa o pari, ti agbabọlu Athletico, Borja fi gba goolu kẹta wọle. Awọn agbabọọlu Naijiria to kopa ninu ifẹsẹwọnsẹ naa ni Thomas, Musa Muhammed, Ebube Duru, Olamilekan Adeleye, Chinedu Ajanah, Emem Eduok, Alhassan Ibrahim, Chidiebere Nwakali, Kelechi Nwakali, Ekundayo Ojo, Kadiri Samad. Oblak, Juanfran, Rafa Muñoz, Montero, Sergi, Thomas, Toni Moya, Olabe, Mikel, Correa ati Gameiro lo kopa fun ikọ Athletico.",0,yoruba what do you understand by àgbé as in àgbéníyì àgbédánà etc its also found in oríkìs like àgbé olólà tí ń ṣá kẹ́kẹ́,0,yoruba "Idán baba idán, èdè baba èdè, àṣà baba àṣà #Yoruba",0,yoruba kàbàkàbà = roughly ọmọ ìta sáré kàbàkàbà nígbà tí ọlọ́pàá dé the area boy ran roughly when the police came,0,yoruba kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba Kí ní dé tí àwọn ìyá mi ò ki ń fẹ́ sọ èdè #Yoruba? Èéṣe tí a fi ma ń díbọ́n bí kò gbédè? :(,0,yoruba Àkójú ọ̀rọ̀ yi kún fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba ti ibile. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "kan. Nitori eyi, ara eni lo ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Bẹẹ ni ọrọ Ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi kẹta rí,ẹni ti ori gbe de ipo awọn baba rẹ leyin ọpọ ifigagbaga laarin awọn ọmọ oye to le ni mẹwa, ti wọn dìjọ du ipo. Ọjọ nla si ni ọjọ Kẹrinla osu Kinni ọdun 1971 ti atọbatẹlẹ ko to jọba, Lamidi Atanda Olayiwola Adeyemi gori itẹ awọn baba nla rẹ. Gomina ologun nigba naa to ti di oloogbe, Ajagunfẹyinti Robert Adeyinka Adebayo si lo gbe ọpa asẹ le lọwọ gẹgẹ bii Alaafin Ọyọ. Ọmọ ọba ni Lamidi Atanda, baba rẹ si ni Alaafin Adeniran Adeyemi, koda, ọmọ ọmọ ọba tun ni pẹlu nitori baba to bi baba rẹ, Alaafin Alowolodu Adeyemi naa jẹ Alaafin. Amọ sibẹsibẹ, eyi ko ni ki o ma figa gbaga pẹlu awọn ọmọ oye yoku to fẹ jọba nikete ti Alaafin Gbadegesin Ladigbolu keji waja lọdun 1970. Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Iru ẹda wo ni Alaafin Adeyemi jẹ? Yoruba ni ajise bi Ọyọ laa ri, Ọyọ kii se bi baba ẹni kọọkan, a si lee ni asamọ yii faramọ ninu ilana igbe aye Oba Lamidi Olayiwola Adeyemi Kẹta ba ba wo isesi rẹ lori oye. Oba Adeyemi ko to jọba jẹ osisẹ adojutofo ati akansẹ to dantọ, to si ni iriri ba se n se akoso eyi to wulo pupọ fun lasiko to di ọba alaye. Tẹ ba si fẹ mọ siwaju si nipa itan igbe aye Ọba Adeyemi, ẹ ka itan igbe aye rẹ nibi lati mọ bo se lo aye rẹ ko to jọba ati bo se dori oye. Gẹgẹ ba se mọ pe ipo pataki ni ipo Alaafin ninu itan Yoruba, to si se asaaju ninu odiwọn ipo awọn oriade nilẹ kaarọ Oojire. Ko si si ọba alaye ti yoo ni bawo ni ti Alaafin se jẹ nitori odu nla ni, kii se aimọ fun oloko, ko si si ẹni ti yoo kọ iyan rẹ, ti ko ni fi ewe boo. Ta ba si n sọrọ nipa ọla, iyi ati ẹyẹ, a le sapejuwe Alaafin Adeyemi bi ọba alade to n fi ọla wu ni, ẹni to jẹ atọbatẹlẹ, ko to jọba. Oba Adeyemi bii Alaafin akọkọ ti yoo lo aadọta ọdun lori itẹ: Ko si yẹ ko ya ẹnikẹni lẹnu pe ọba to lọla, niyi ati ẹyẹ yii lo aadọta ọdun lori oye eyi to mu agbega nla ba agbegbe rẹ. O si yẹ ko ye wa pe ohun aseyọri gbaa ni ki ọba alade kan lo aadọta ọdun lori oye, bẹẹ si ni ko si ni akọsilẹ pe Alaafin kankan lati ẹyin wa lo aadọta ọdun nipo. Amọ ka ba le mọ bi ẹyẹ yii se pọ to fun Ọba Adeyemi gẹgẹ bi Alaafin akọkọ ti yoo lo aadọta ọdun nipo, o yẹ ka woju wẹyin wo iye ọdun ti diẹ lara awọn baba nla rẹ to jẹ Alaafin lo, to fẹ ẹ sun mọ adota ọdun. Awọn Alaafin to lo ọdun to pọ diẹ nipo yatọ si Ọba Adeyemi: Akọsilẹ fi ye wa pe Alaafin to fẹ sunmọ aadọta ọdun lori oye lẹyin Ọba Adeyemi ni Alaafin Siyanbola Ladigbolu to jọba laarin ọdun 1911 si 1944, ẹni to lo ọdun mẹtalelọgbọn nipo. Bakan naa ni Oba Alowolodu Adeyemi Kinni, tii se baba fun baba Oba Adeyemi naa jọba laarin ọdun 1876 si 1905, to si lo ọdun mọkandinlọgbọn lori oye. Oba Atobatele Arugba naa jọba laarin ọdun 1837 si 1859, to si lo ọdun mejilelogun nipo. Bakan naa ni Alaafin Adeniran Adeyemi keji, tii se baba ọba Lamidi Adeyemi, ẹni to jọba laarin ọdun 1945 si 1955, to si lo ọdun mẹwa pere lori oye, ki wọn to yọ nipo. O si daju pe aye ti ẹsin Oba Adeniran Adeyemi ko jẹ, ti wọn fi yọwọ rẹ ninu awo, ni iru idi rẹ, tii se ọmọ rẹ n jẹ lori aleefa. A si le se apejuwe Ọba Lamidi Adeyemi bii oloriire, ti Ọlọrun gba fun, to si ri aanu pupọ gba. Awọn idagbasoke to ba ilu Oyo ati ipa manigbagbe ti Ọba Adeyemi ko ni Naijiria: Kii se pe a sọ asọdun ta ba ni idagbasoke alailẹgbẹ ba ilu Ọyọ lati aadọta ọdun ti Lamidi Adeyemi ti wa lori itẹ bii Alaafin Ọyọ. Awọn ileesẹ nla nla, ileesẹ alabọde atawọn ileesẹ kereje kereje lo ti lalẹ hu nilu Ọyọ lẹyin ti Ọba Adeyemi di Alaafin. Bakan naa ni eto igbayegbadun buyaari si nilu naa, to jẹ ilu to dakẹ jẹjẹ tẹlẹ ki Alaafin yii to debẹ. Fun awọn onwoye ohun to n lọ lawujọ, alaafin kii fi ọrọ asa sere, ta si le ni o kogiri mọ ojuse rẹ bi ọba alaye lati ri daju pe awọn asa, ise ati ede wa ko lọ sokun igbagbe. Ẹni ti itan ko ba si ye, to ba tọ Alaafin lọ, oye yoo ye kedere nipa ohun to ba fẹ mọ, ti ọba alaye naa si jẹ iwuri fun ọpọ ọmọ Yoruba, paapaa lasiko to ba n hu awọn itan manigbagbe jade. Yatọ si eyi, ipa kekere kọ ni Adeyemi n ko si idagbasoke orilẹede Naijiria, to si maa n kopa ti kii se keremi si awọn ohun to n lọ lorilẹede yii. Bẹẹ ba si gbagbe, ọpọ lẹta ni Alaafin maa n kọ si awọn adari to ba wa nipo boya labẹ ijọba apapọ ni abi lawọn ipinlẹ. O yẹ kẹ ranti lẹta to kọ si aarẹ Muhammadu Buhari lati jẹ ko mọ bi ori se n ta araalu si nipa ọrọ aje to dagun ati eto aabo to mẹhẹ, eyi to lapa rere. Bakan naa ni Alaafin tun da si ọrọ aawọ ija agba to n waye nipinlẹ Ekiti, to si kọ lẹta si gomina ipinlẹ naa, Kayode Fayemi, lati pe akiyesi rẹ si ọrọ naa ati ọna atunse nipa rẹ. Tun wẹ, ọpọ awọn gomina oloselu ati ti ologun to ti jẹ nipinlẹ Ọyọ lo mọ ipa ribi ribi ti Alaafin ko lati jẹ ki isejọba wọn se aseyọri. A si le sọ pe Ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi ti sisẹ pọ pẹlu awọn gomina to to mọkanlelogun lati ri si idagbasoke ipinlẹ Ọyọ. Awọn gomina ti Alaafin Adeyemiri ibẹrẹ ati opin saa wọn nipo: A le sọ pe Ọba Adeyẹmi ri aye wa ni gbogbo ọna nitori gbogbo ohun ti eeyan maa n gbe ile aye se, ni Alaafin ti se ni aseyọri. O ni ẹmi gigun, o ni alaafin, Ọ́ba Adeyemi tun lowo, o lọla, o ni gbajumọ, bakan naa lo n sọla ni agbala rẹ pẹlu awọn orekelẹwa obinrin, to si tun jẹ alayelugba ti awọn ọba ẹgbẹ rẹ n wari fun. BBC Yoruba wa n ba Ọba Lamidi Olayiwola Atanda Adeyemi Alowolodu yọ ayọ aadọta ọdun rẹ lori itẹ, ta si n gbadura pe ade yoo pẹ lori, bata yoo pẹ lẹsẹ, ẹsin ọba yoo si jẹ oko pẹ. Asẹ.",0,yoruba "Adarí àpapọ̀ fún ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress (APC), Bola Tinubu ti ní òun ni ẹni tó tọ́ láti jẹ Ààrẹ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà ní kété tí Ààrẹ Muhammadu Buhari bá ti gbésẹ̀. Tinubu ní òun ní gbogbo ìgboyà àti àmúyẹ tí Ààrẹ tó le mí àyípadà ọ̀tun àti ìdàgbàsókè tó lòòrìn bá orílẹ̀ èdè Nàìjíríà. Níbi ìpàdé àti ìjíròrò ọlọ́jọ́ kan èyí tí Tinibu ṣe pẹ̀lú àwọn Abẹnugan àti àwọn ìgbákejì Abẹnugan ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ẹgbẹ́ òṣèlú APC tó wáyé ní ìpínlẹ̀ Eko ló ti ṣíṣọ lójú ọ̀rọ̀ yìí. Ó sọ wí pé ìlọsíwájú àti ìdàgbàsókè orílẹ̀ èdè Nàìjíríà wà lọ́wọ́ bí àwọn adarí bá ṣe lè ronú àti bí wọ́n bá le ṣe jí gìrì sí ojúṣe wọ́n sí. ""Orílẹ̀ èdè Nàìjíríà nílò mi gẹ́gẹ́ bí èmi náà ṣe nílò Nàìjíríà nítorí mo jẹ́ ẹni tó le ronú tó sì ní ìgboyà láti mú àyípadà ọ̀tun bá a."" ""Ẹni tó ní ìgboyà ní Ọlọ́run dá mi tó sì ń ṣe iṣẹ́ fún mi, mo sì fẹ́ lò ó fún orílẹ̀ èdè Nàìjíríà náà.""",0,yoruba "Agbófinro mú ọkùnrin to n gun baalu to fẹ́ gbera Awọn elétò ààbò to wà nibẹ̀ ni awakọ ofurufu aladani kan to ń bọ lẹ́yìn lo sáré ké gbajari ki wọ́n tó mú ọkùnrin náà. Bótilẹ̀ jẹ́ pé àwọn òṣìṣẹ́ pápákọ ofurufu náà ko le fi ìdí ti ọkunrin òhun ṣe gbe irú igbésẹ̀ bẹ́ẹ̀ ni kété ti ọ̀rọ̀ naáà ṣẹlẹ̀, ṣùgbọ́n ọwọ́ ti tẹ̀ẹ́. 'Mí ò ya wèrè, mí ò burú, ọ̀nà àtijẹ là ń wá' Ẹ̀wẹ̀, ilé iṣẹ́ Airpeace ni ọkùnrin náà jẹ́ ọkàn lára àwọn ti wọ́n máa ń tèlé ọkọ ofurufu sálọ si ilẹ̀ òkèrè. Ilé iṣẹ́ náà ni àfurasi náà ti wà ni àhámọ àwọn bàyìí fun ìfọrọ̀wánilẹnuwò. Bayii ni àtẹjáde Airpeace ṣe lọ ""Ní òwúrọ òni, ní dédé ààgo mẹsàn kọja iṣẹ́jú mẹwaà ni MMA1 nílù Eko ni bàà'lú Airpeace to n lọ Owerri n gbìyànju láti gbéra nigbati ọkunrin kan ti ko ti to ọmọ ogun ọdun bẹ jáde lati inu igbó lójú ọ̀nà ti bààlu yòó gbà láti sá tèlé bàálú náà.""",0,yoruba da ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Bàbá lo tun se lọ.,0,yoruba wúlò. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ìyá lo aye àìlẹ̀.,0,yoruba orisirisi. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.,0,yoruba rò papa re yóò ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba Ọba ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa aráyé: ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo.,0,yoruba "Orí igi tó wọ́, làá wà, táà rí èyí tó tọ́. / It's while on the crooked tree that one will find the proper one. [Keep hope alive: don't despair; where you are is still good enough as a stepping stone.] #Yoruba #proverb",0,yoruba RT @user: @user Ti Oluwa ni a wa se o,0,yoruba "ni ìgbà mi owó àkokò, Baàlè ri A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..",0,yoruba toò a jẹ́ pé ìpáyà kan ò sí fún yín nìyẹn o kẹ nà gbalaja nínú ọkọ̀ lókù báyìí,0,yoruba Baàlè fi. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "Ninu agbejade iwadi iṣiro rẹ lori bi owo ori awọn ohun jijẹ ati mimu ṣe lọ si loṣu kẹjọ si ikẹsan ọdun yii. Ajọ NBS ni, ida mọkanla o le diẹ ninu ọgọrun (11.24%) ni ohun jijẹ tun fi gbowo lori sii laarin oṣu kẹjọ si ikẹsan. Lati oṣu kẹjọ, ti ijọba apapọ ti ti awọn ẹnu ibode orilẹede Naijiria pa, ni awọn owo ori ohun jijẹ lorilẹede Naijiria ti gbe ẹnu soke, lẹyin to ti wa silẹ fun awọn saa diẹ. Gẹgẹ bi ohun ti ajọ NBS gbe jade, ipinlẹ Kogi ni ounjẹ ti wọn julọ, lẹyin naa ni ipinlẹ Delta pẹlu Kwara. Bakan naa lo ni ipinlẹ Kano ati Zamfara ni owo ori ohun jijẹ ti fara rọ julọ fun oṣu kẹsan.",0,yoruba "àlùfáà ni iwa rere lojiji. Bàbá lo tun se joko. Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Olùwo fi. Nitori eyi, ara eni lo ni àṣà yorubá eyti o gbe lori ọ̀run dídì.",0,yoruba "ìṣẹ́ ni ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Nitori eyi, ara eni lo ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba RT @user: @user ejowo kini yoruba n pe ni (1) afurugbin (re mi mi do) (2) komookun (do mi do re)?,0,yoruba "Àkànnàmọ̀gbò kì í pa ọdún jẹ, pẹ́pẹ́yẹ kì í kú sómi, ṣóm f'omi ṣeré. O kò ní kú sómi ayé, wà á wẹ omi ayé já láṣẹ Olódùmarè. Kú ewu ọdún o! https://t.co/vo62hYPesq",0,yoruba "Èso yìí le kú, ó ṣòro í fọ́. Méjì àti mẹ́ta nígbà mìíràn la ń bá nínú ẹ̀pa so ọmọ ayò. https://t.co/kP4MAkXTeo",0,yoruba Ìlú yorubá lo ni ìgbà mi owó àkokò eyti o gbe lori àìmọ́ kọ. Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba fẹ. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa òkè: ti o nuni ti o dara.,0,yoruba "ijọba kò ṣetan lati wọn ọn kun, ASUU naa ko fẹ gbaa ni aabọ lori ọrọ iyanṣelodi olukọ fasiti Lọjọ Aje nilu Abuja la ti gbọ wi pe awọn ọmọ ẹgbẹ ASUU binu jade kuro ninu ipade ti o yẹ ki wọn ṣe pẹlu awọn aṣoju ijọba ti Minisita fun ọrọ iṣẹ ni Naijiria Chris Ngige le waju wọn. Ọrọ n bá ọrọ bọ Chris Ngige to jẹ minista fun ọrọ iṣẹ ni Naijiria ni tootọ ni ijọba ṣe ipade pẹlu ASUU ni eyi ti wọn ti jọ n sọ asọyepọ lori awọn nkan ti ASUU n fẹ. O ni ki awọn le jọ wa ọna abayọ naa loun ṣe pe ipade naa ati pé abọ iṣẹ ti a fun ẹnikọọkan nile iṣẹ ijọba ni a ṣẹṣẹ n to pọ ki a le mọ ọna abayọ. Yorùbá gbà pé òrìṣà bí ìyá kò sí! Ni ipari o ni idi ti awọn ko ṣe yanju ọrọ naa ni pe oun ki onikaluku ri ọjọ diẹ lati wo awọn akọsilẹ naa wò ṣaaju keresimesi. O fi idaniloju han pe awọn olukọ a fopin si iyanṣẹlodi na laipẹ ati pe awọn akẹkọọ a wọle nibẹrẹ oṣu kinni ọdun 2019. O ni oun yoo ṣe ipade pẹlu minista fun eto inawo lati yanju ohun gbogbo ti ASUU n beere nitowo. Gbogbo ènìyàn ló wọ agbádá ikú, ẹni tó kàn lẹnìkan kò mọ̀ Gbogbo igbiyanju lati ba alaga ASUU sọrọ lo jasi pabo nitori o ni oun ko ni ohunkohun lati sọ ki Ngige jabọ ohun to ṣẹlẹ. Alápinni: Kò sí ẹni to fẹ́ kọ́kọ́ kọ́ iṣẹ́ òṣèré bíi ti àtẹ̀yìnwá Ko ti daju oun to mu ki awọn olukọni naa binu jade ninu ipade ohun ṣugbọn saaju ipade naa la gbo wi pe ọgbẹni Ngige ti sọ wi pe ohun ni ireti wi pe ọrọ yoo ni iyanju. ASUU Strike: Bí àwọn kan se dunnú, làwọn kan fajúro Awọn olukọni ile ẹkọ fasiti Naijiria ti dẹgun le iyansẹlodi ọlọjọgbọrọ lati ọjọ kẹrin osu kakanla ọdun yi yi. Ohun to mu wọn gun le iyansẹlodi naa ni awọn nnkian koko mẹta ta ti ri owo osu wọn ti wọn ni ko munadoko to,atunto ati atunṣe awọn ile ẹkọ to fi mọ ajẹmunu awọn olukọni naa. 'Tayọ̀tayọ̀ ni mó fẹ́ ṣiṣẹ́ pẹ̀lú INEC ki ìdìbò 2019 lé dára'",0,yoruba í tún ṣe àwọn iṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa iṣẹ́: ti o lẹ.,0,yoruba Ijoba apapo ngbero lati se eto isuna N7.9tn fun odun 2018. #tweetinyoruba https://t.co/rjTE21hSRL,0,yoruba ìrèní ọjọ́ mẹ́ta òní ìfàní ìdúnta ọdún mẹ́ta sẹ́yìn ìdúnsànán,0,yoruba "Ọba fè lọ, Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba pataki lojiji. Alàji lo ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba Baàlè lọ. A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà.,0,yoruba Ìyá joko. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "Gẹgẹ bii ohun ti a gbọ, awọn eeyan da owo naa si ikawọ arabinrin kan ti orukọ rẹ n jẹ Maureen Badejọ, to si yẹ ki Maureen fi owo ọhun ṣowọ si Oloye Igboho. Wahala bẹ silẹ lẹyin ti Maureen sọ pe oun fi owo naa ṣọwọ si Olayomi Koiki, ti ọpọ mọ si Koiki Media, to jẹ agbẹnusọ ajijagbara naa. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Iroyin naa ni lẹyin ti Koiki gba owo naa tan, ko fidi rẹ mulẹ fun Maureen pe owo naa ti de ikawọ oun fun nnkan bi ọsẹ meji. Ko pẹ si asiko yii ti awuyewuye bẹrẹ si n waye lori owo naa, ti wọn pe ni owo ounjẹ. Idi ree ti Muareen fi ṣe fidio kan, nibi to ti kesi Koiki lati wa sọ boya o ti gba owo naa tabi ko tii gba. Bo tilẹ jẹ pe ibeere ọhun ati gbagede eto ti Muareen ti beere nipa owo naa ko dun mọ Koiki ninu, o fesi pe lootọ ni oun gba owo ọhun gẹgẹ bii owo ounjẹ. Gẹgẹ bii ohun ti Maureen sọ, o ni oun n reti ki Koiki kede pe oun ti gba owo naa, ki awọn eeyan to da owo ọhun le mọ bo ṣe n lọ. Nigba ti Maureen n beere lọwọ rẹ, idi ti ko ṣe fi ohun ransẹ pe oun ti gba owo naa lẹyin ọsẹ meji, ni Koiki ba dahun pe owo ounjẹ lasan ni N2.5 miliọnu, ati pe kii ṣe nnkan babara nitori awọn eeyan ti da owo to ju bẹẹ lọ fun ijagbara ọhun. Akomolede àti Asa: Mọ̀ si nípa àṣà ìsọmọlórúkọ́ nílẹ̀ Yorùbá àti ìtumọ̀ orúkọ̀ fún ìkókó Ọrọ ti Koiki sọ yii, pe owo na ko jẹ tuntun ati nnkan babara lobi Muareen ninu, to bẹẹ ti awọn mejeji fi n ta ohun sira wọn. Lẹyin naa ni Maureen ni ki Koiki fi ori eto oun silẹ. Gbas gbos to waye laarin Maureen ati Koiki ti wa mu ki obinrin naa ke si ileeṣẹ GoFundMe lati da gbogbo owo to gba lọwọ ara ilu to nifẹ lati ṣagbatẹru ijijagbara ti Sunday Igboho n ṣe, pada fun wọn. Ti ẹ ko ba gbagbe, oṣu diẹ sẹyin ni Ololye Sunday Igboho kede Koiki Media gẹgẹ bii ojulowo agbẹnusọ oun, lẹyin ti awọn kan bẹrẹ si ni ṣi oriṣiri oju opo lorukọ rẹ. Adebunmi Adeyeye: Mo jẹ gbèsè gbọ́múléláńtà, ìdí iṣẹ́ kabúkabú ni mo ti ri san Níbo ní £46,933 owó ìrànwọ́ tí wọn dá fún Sunday Igboho wa? Awuye wuye ti n waye lori owo iranwọ fun isẹ ijijagbara ti wọn da fun Oloye Sunday Igboho, tii se ajijagbara kan fun iran Yoruba. Idi ni pe Igboho ti kede fun araye pe oun ko gba owo kankan to to ogoji miliọnu naira tawọn eeyan kan n pariwo pe wọn ko fun oun. Igboho, ninu fidio kan to ti bawọn araalu atawọn ọmọlẹyin rẹ sọrọ lọjọ Aiku ni ọrọ yii ti jẹyọ. O ni ""Owo ti wọn ni wọn da fun mi, pe wọn gbe ogoji miliọnu naira fun mi, n ko gba owo kankan lọwọ ẹnikẹni. Sunday Igboho: Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọ̀n bàbá wa Miliọnu mẹfa ati aabọ naira (N6.5m) pere lo tẹ mi lọwọ. Awọn ti mo sọrọ wọn jade ninu fidio ti mo se nikan lo fun mi lowo naa, mo si kede rẹ nigba naa."" Ajijagbara ọmọ Yoruba naa fikun pe ""owo rẹpẹtẹ ti wọn da fun Maureen, a ko ri gba, gbogbo ẹnu ni mo fi sọ. Awọn eeyan kan fọkan si pe mo gba ogoji miliọnu naira, amọ n ko ri gba. Madam Maureen naa ni oun ko ri owo naa gba. O ni GoFundme ko gbe owo naa kalẹ, n ko si sọ ohunkohun, tori owo naa kọ la n na."" Sunday Igboho: Ẹ fi Ògún búra fún wa láti jà fún ilẹ̀ Yorùbá láì gbé Amotekun sábẹ́ ìjọba Sunday Igboho ni ojoojumọ ni awọn n dana pẹlu awọn ọmọlẹyin oun, tawọn n jẹun, da epo sinu ọkọ tawọn n gbe kiri. Amọ o fikun pe yiyọ ẹkun oun lori ọrọ naa, ti ojo kọ rara. Ibeere to wa n gba ẹnu ọpọ eeyan ni pe nibo ni owo tuulu yii wa nigba ti ko de ọdọ Sunday Igboho? Adebunmi Adeyeye: Mo jẹ gbèsè gbọ́múléláńtà, ìdí iṣẹ́ kabúkabú ni mo ti ri san Ogundamisi sọrọ lori owo iranwọ ti wọn kojọ fun Igboho Sugbọn lẹyin ọjọ kan ti Sunday Igboho sọrọ yii lori ayelujara, ni gbajumọ kan nipa ohun to n lọ lawujọ, Kayode Ogundamisi fi ikede kan soju opo Twitter rẹ nipa owo naa ni aarọ ọjọ Aje oni. Ninu ikede naa ni Ogundamisi ti salaye pe obinrin kan, Maureen Badejo, ti wọn fi ẹsun ikowojẹ kan, ti kọwe si ajọ GoFundMe pe ko da owo to din diẹ ni miliọnu mẹtadinlaadọta pọun (£46,933) pada. Owo iranwọ yii, to ni wọn ko jọ fun Sunday Igboho lo ni ki ajọ naa da pada fun awọn eeyan to da owo naa. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Nibayii, BBC Yoruba ti n gbe igbesẹ lati ba Maureen Badejo sọrọ lori isẹlẹ yii lati mọ ibi ti ọrọ owo owo iranwọ naa de duro ati bi owo naa se rin. Bo ba se lọ si, a maa mu iroyin ọhun wa fun yin.",0,yoruba ìgbà kan. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìṣẹ̀: ti o ní wúlò.,0,yoruba Yorùbá àwọn èrò àti àsà tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba opo la pe di e lao fi fun ni oro messi ooo rt ẹ̀dá ọmọ ènìyàn ni ọ̀gbẹ́ni messi yí àb,0,yoruba "Bo tilẹ jẹ pẹ ileeṣẹ to ma n ṣafihan awọn ohun to lamilaaka lagbaye, Guinness World Records, ko fi ontẹ lu ọjọ ori rẹ, wọn bi Fredie Blom ni agbegbe Ila Oorun Cape, lọdun 1904. Ko to pe ogun ọdun lo ti padanu gbogbo ẹbi rẹ lọwọ ajakalẹ arun ""Spanish flu"" to kọlu agbaye lọdun 1918, lẹyin naa lo la ogun agbaye meji ọtọọtọ kọja. Nigba to ba BBC sọrọ lọdun 2018, ọgbẹni Blom sọ pe ko si aṣiri kan gboogi si ẹmi gigun oun. O ni ""Ko si aṣiri kankan, Ọlọrun lo da mi si, igbakugba ni mo le ku ṣugbọn Ọlọrun lo gbemiro."" Iṣẹ alagbaṣẹ ni Blom fi pupọ ninu igbesi aye rẹ ṣe ko to fẹyinti lẹyin to le ni ọgọrin ọdun. Blom maa n mu siga daadaa nigba aye rẹ, ṣugbọn o fi ọti silẹ lọpọ ọdun ko to jade laye. Awọn ẹbi oloogbe ọhun sọ fun awọn akọroyin pe aisan kọ lo pa Blom. Ọkan lara wọn, Andre Naidoo sọ fun ileeṣẹ iroyin AFP pe ""Ọsẹ meji ṣeyin, baba wa ṣi n la igi, ṣaka lara rẹ da, ko si si nkan kan to ṣelẹ si i."" Ṣugbọn o fi kun un pe o yọ jo laarin ọjọ diẹ sira wọn lai ṣaisan ṣaaju. Naidoo pari ọrọ rẹ pe awọn ẹbi oloogbe naa ko gbagbọ pe arun Covid-19 lo mu ẹmi rẹ lọ. Ǹjẹ́ o leè fẹ́ ẹni tó bá ń jẹ ẹran Ajá?",0,yoruba dara. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó wáyé..,0,yoruba """Nilẹ Arab bi a ba n di ẹru lati rinrinajo, ohun mẹta ni a gbudọ rii daju pe a ni: iwe irina, owo ati ibi ti a le fọ idi si ni'rinajo"". Eyi ni adẹrinpoṣonu ara ill Egypti Bassem Youssef sọ nibi ere itage akọkọ rẹ ni Uk gẹgẹ bi alawada. (Ẹ̀rín kèékèé)! Ṣe lo bẹrẹ si nii ju ọpa kan ti wọn n pe lede wọn ni shattaf (tabi bum gun) iyẹn ẹrọ kan to lee fọn omi jade to maa n wa lẹba ile igbọnsẹ igbalode fun idi fifọ. O ni ""ẹ wa, ko ye mi o, ẹ jẹ ọkan lara ilu to laju ju lagbaye, ṣugbọn to ba di ọrọ ti ẹyin wa yii, ẹyin lẹwa o."" (Ha ha ha)! Bẹẹ si ni ọpọ eeyan gba pẹlu Youssef pe ootọ lo sọ. Shokoleeti to ri bii pẹ̀tẹ̀ -""Chocolate pudding"" Ni ilu oyinbo, ọpọ wọn ti fẹran ki wọn maa fi nkankan nu idi ju bi wọn ba lo ile igbọnsẹ tan ju ki wọn maa bu omi ṣan idi lọ - eyi si jẹ oun to ya awọn eeyan lẹnu lagbaye. Kẹẹ si maa wo o, omi a maa fọ idi mọ ju béébà lọ. Awọn to ti mọ lara ki wọn maa fi omi fọ idi wa beere tọkan tọkan wi pe "" ẹ wa, ṣe lootọ o tẹẹ yin lọrun lati fi tiiṣu nikan nu shokoleeti pẹ̀tẹ̀ kuro lara yin? (Ínyànmà)! Ati pe nigba ti tiiṣu ti wọ́n n lo lode oni ko le lara bii àwo sẹ̀rámííkì tawọn Greek igbaani maa n lo tabi shùkù àgbàdo tawọn Amẹrika igbaani maa n lo (Hè hè hè hè - ẹ̀rín), gbogbo wa yoo gba pe omi ko tilẹ ki n ha ni lara to iwe to fẹlẹ ju. Ọpọ ara ilu awọn orilẹede agbaye lo ti wa n pari abẹwo wọn sile igbọnsẹ bayii pẹlu omi. Sibẹ, ni ọpọ awọ n orilede ti ẹlẹsin musulumi pọ si, omi lilo lo wọpọ nib gẹ́gẹ́ bi ẹkọ Islam ṣe kọ nipa lilo omi fun imọtoto. Onimọ kan to ṣewadii nipa iha ti awọn eeyan n kọ si awọn nkan eelo ile igbọnsẹ, Othman fi han pe awọn musulumi ara orilẹede Australia kan ti dara pọ mọ iwa igbe aye lilo ile igbọnsẹ igbalode ati lilo tiiṣu pọ mọ age omi to kun tabi ki wọn ṣe ẹrọ to n fọn omi sẹgbẹẹ ẹrọ igbọnsẹ wọn. Amọṣa o, ọ̀rọ̀ imọtoto yii ko duro lọdọ awọn musulumi nikan o. ""O ti mọ awọn ara orilẹede India kan lara lati maa lo tiiṣu, ṣugbọn ọpọ wa la ṣi fara mọ lilo omi nigba to ba yẹ"". Othman ni ""nigba ti o ba fẹ ṣebẹwo si ọrẹ rẹ to jẹ ara Indian nilẹ Amẹrika, mo lee fwọ sọya pe wọn gbe ike omi tabi ife si ẹba ile igbọnsẹ wọn"". Ẹwẹ, Othman sọ iha ti awọn eeyan kọ si lilo oriṣiriṣi beeba, o ni fun apẹrẹ akẹgbẹ oun kan ni Sheffield, UK ti lo tiiṣu rẹ tan, lo ba pada fi £20 nu idi. (Hà hà hàhà hà!) Idile kan, Kuo gan ti n jiroro lori ọrọ mejeji yii - ninu keeyan jokoo ya igbẹ tabi loṣoo. Iru ile igbọnsẹ fun mejeji lo wa laye Han Dynasty (206BC-220AD) bi o tilẹ jẹ pe bibẹrẹ yẹn lo wọpọ lawọn ile igbọnsẹ itagbangba. Koda lonii, iwadii fihan pe ida mẹta eeyan lagbaye lo maa n loṣoo ṣe 'ga. Ka si ma parọ, fun ẹya agọ ara liloṣoo naa lo dara ju gẹgẹ bi iru ibẹrẹ yẹn ṣe maa n jẹ ko jade wọọrọwọ. (Hmmmmmn!)",0,yoruba "Awọn ẹbi oloogbe Dokita Stellah Adadevoh ti ni, inu awọn dun si igbesẹ ti ijọ́ba apapọ gbe lati fi opopona kan sọ ori dokita naa, lẹyin ọdun marun to doola orilẹede yii lọwọ ajakalẹ nla, to ṣeeṣe ki apa rẹ o maa ka. Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ, Arabinrin Niniọla Williams ṣalaye pe, bi o tilẹ jẹ wi pe Dokita Adadevoh ko fi ẹmi rẹ lelẹ nitori ati gba ami ẹyẹ kankan, bikoṣe ifẹ nla to ni si orilẹede Naijiria, sibẹ inu awọn mọlẹbi ko ṣai dun si igbesẹ naa. ""Ọmọ orilẹede to nifẹ Naijiria tọkantọkan ni oloogbe Adadevoh, idi si niyi to fi ṣe ohun to ṣe"" Fun ọpọlọpọ ọmọ Naijiria to ranti ohun to ṣẹlẹ ni ọdun marun un sẹyin, wọn ko lee gbagbe orukọ Dokita Ameyo Stellah Adadevoh. Ohun ti yoo si wa si iranti wọn ni ipa takuntakun ti arabinrin naa ko, lati rii daju pe aisan gbẹmigbẹmi nni, Ebola ko raye ṣọṣẹ lorilẹede Naijiria. Bi kii ba ṣe ti Dokita yii ni, to fi tipa tikuuku de ọmọ orilẹede Liberia kan, Patrick Sawyer to ko arun naa wọ orilẹede Naijiria mọlẹ ni ileewosan rẹ, First Consultant Hospital, to wa nilu Eko, afaimọ ki ẹmi ti ko ba ba arun naa lọ nigba naa ma di ẹgbẹlẹgbẹ. Lọna ati sọ orukọ akọni obinrin naa di manigbagbe, lọjọru ni ijọba apapọ fi orukọ Dokita Adadevoh sọ opopona kan ni olu ilu Naijiria, Abuja. Opopona naa, lo wa lagbegbe opopona Ahmadu Bello nitosi gbọngan ipade nla ti ileeṣẹ ọmọogun ofurufu ilẹ Naijiria, Nigeria Airforce Conference center. Ni ọjọ kọkandinlogun oṣu kẹjọ ọdun 2014 ni Dokita Adadevoh jade laye, lẹyin to ti ko arun Ebola naa lara Ọgbẹni Sawyer to wa sorilẹede Naijiria lati Liberia. Awọn kan n woye pe ohun to loorin ju eyi lọ, bii ileewosan to ti ṣiṣẹ nigba aye rẹ, papakọ ofurufu, ibudokọ oju omi, tabi papa iṣere ati ileewosan apapọ orilẹede Naijiria, lo yẹ ki ijọba fi sọ ori dokita Adadevoh. Bẹẹni awọn miran kan sara si ijọba fun igbesẹ naa ti wọn si tun n woye pe, o ku ni ibọn n ro, ki ijọba o ranti awọn oniṣẹ eto ilera miran to ku lasiko arun naa.",0,yoruba Báwo ni a ṣe ń yan ẹran? #Ebola,0,yoruba "Àṣìṣé ni pé òún lọ, àmọ́ ó tún wá kó ènìà mẹ́rìndínlọ́gọ́fà lọ. Ìwà olórí burúkú kọ́ rèé? #GEJ #brazil",0,yoruba "Akeredolu ati Abraham ni wọn jọ figagbaga fun asia ẹgbẹ oselu APC fun ipo gomina ipinlẹ Ondo lọdun 2016 Olusẹgun Abraham, to baa du ipo asia gomina ninu ẹgbẹ oselu APC nipinlẹ Ondo, lo n pee lẹjọ. Rotimi Akeredolu tọ ileẹjọ to ga julọ lorilẹede Naijiria lọ, lati lodi si idajọ ti ileẹjọ giga ilu Abuja gbe kalẹ, ti ileẹjọ kotẹmilọrun nilu Abuja kannaa si faramọ, ninu idajọ to gbe kalẹ losu keje ọdun 2017 lati gba Olusẹgun Abraham laaye, lati fun Akeredolu ni iwe ipẹjọ lori ẹjọ to pe gomina ipinlẹ Ondo naa. Akeredolu ati Abraham ni wọn jọ figagbaga fun asia ẹgbẹ oselu APC fun ipo gomina ipinlẹ Ondo lọdun 2016 Ọgbẹni Abraham npẹ ẹjọ lori idibo abẹle ninu ẹgbẹ oselu APC, eleyi to fa Rotimi Akeredolu kalẹ gẹgẹbii oludije fun ipo gomina, lasiko idibo gomina nipinlẹ naa to waye kẹyin. Gbogbo awọn adajọ maraarun lo panupọ gbe idajọ naa kalẹ Ninu idajọ gbogbo wa lo fọwọsi, ti wọn gbe kalẹ, igbimọ onidajọ ẹlẹni marun ileẹjọ naa gbe idajọ kalẹ wipe, ẹjọ kotẹmilọrun ti Gomina Akeredolu pe ko lẹsẹ nlẹ. Bakannaa ni ileẹjọ to ga julọ lorilẹede Naijiria, tun pasẹ pe ki Akeredolu san ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta naira (N500, 000) gẹgẹbii owo 'gba maa binu' fun Abraham. Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si:",0,yoruba RT @user: Èèmọ̀ wọ̀lú o! Èèyàn mẹ́rìnlá ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ tún ni àjọ @user sọ pé wọ́n ti kó ààrùn kòrónà. Èèyàn méjì ní ìlú Àbùjá.Èèyàn…,0,yoruba rere. Ìyá lo ni ẹ̀ká àwẹ eyti o gbe lori àìmọ́ kọ.,0,yoruba "A óò ké pe Olódùmarè, a ó bá a wí ire, fọ ire, sọ ire kí ti wá ba a lè dára. #AsaIwure",0,yoruba "Ikú má pawo mọ́ o, Ikú ti yẹ̀ lórí awo; Ọ̀tọ̀ ni à á ya oofúà obìí sí. Ikú mọ́ pawo mọ́ o, Ikú yẹ̀ lórí awo.",0,yoruba "Gẹgẹ bi Daniel ti wi ninu atẹjade kan to fi sita, ika to ba tọ simu, la fi n re imu, Obi ti jẹ gomina ri, to si tun jẹ́ alaga tẹlẹ fun banki fidelity. Koda, ọdọ to jẹ ọlọpọlọ pipe ni, to si tun ni imọ pipe nipa eto ọrọ aje labẹle ati lagbaye. O fikun pe, awọn iriri Peter Obi yii ko se fi owo ra, iriri si se agba ohunkohun, irufẹ ọlọpọlọ pipe bayii si ni orilẹ-ede Naijiria nilo niru asiko taa wa yii. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìyá àkàndá ẹ̀dá: Àwọn ẹbí mi fẹ́ kí n pa ọmọ mi torí ó jẹ́ àkàndá ẹ̀dá Atẹjade naa fi kun pe, iyansipo Peter Obi ati ajọsepọ rẹ Atiku Abubakar ti wọn ba de ipo aarẹ, yoo seranwọ lati mu agbega ba eto ọrọ aje wa, irẹpọ ati agbega ba Naijiria lapapọ. Atiku yan peter Obi gẹgẹ bii igbakeji rẹ Olùdíje fún ipò aarẹ l'ábẹ́ àsìá ẹgbẹ́ òṣèlú Peoples Democratic Party, PDP, ti yan Peter Obi gẹ̀gẹ̀ bi igbakejì rẹ̀ tí wọn yóò jọ síje dú ipò l'ọ́dún 2019. Igbákejì alukoro ẹgbẹ́ PDP, Diran Ọdẹyẹmi sọ fun BBC Yoruba pé wọ́n yan Obi tó ti jẹ́ gómìnà rí ní ìpínlẹ̀ Anambra, nítorí pé ọmọ Nàìjíríà tòótọ́ ni, tí kò sí tún dàgbà tàbí kéré jù. ""Bákan nàá ni ẹgbẹ́ wo àwọn àṣeyọrí tó ṣe nígbà tó wa ní ipò gómínà, àti láti ìgbà tó ti fi ipò sílẹ̀."" Yíyàn tí a yan Obi kíì ṣe láti fa ojú ẹ̀yà ìgbò mọ́ra, ṣùgbọ́n nítorí pé ẹgbẹ́ wa gbà pé ẹ̀yà kan kò ju òmíràn lọ ní Nàìjíríà.'' Ìyànsípò Peter Obi ti n fa àríyànjiyàn lórí ẹ̀rọ̀ ayélujára. Bí àwọn kan ṣe n gbóríyìn fún ìgbésẹ̀ tí ẹgbẹ́ òṣèlú PDP gbe, ní àwọn kan ti sọ ọ̀rọ̀ nàá di ẹní bá láyà láàrin ìgbákejì aarẹ Nàìjíríà, Yemi Ọṣinbajo àti Peter Obi, ti olùdíjé fún ipò aarẹ nínú ẹgbẹ́ PDP, Atiku Abubakar, ṣẹ̀ṣẹ̀ yàn. Ohun tó yẹ kí Atiku Abubakar ó rò kí o tó yan igbákejì Àáyáa Atiku Abubakar oludije fún ipò Ààrẹ labẹ àsìá ẹgbẹ́ òṣèlú PDP tí bẹ́ sílẹ̀ ó bẹ́ ááré báyìí. Lẹyìn ìkéde rẹ gẹ́gẹ́ bí ẹni tí yóò sójú ẹgbẹ́ náà, n'isẹ ní àwọn ọmọ orílèèdè Nàìjíríà n dá aba oríṣi lórí ẹni tí yóò kọwọrin pẹlu rẹ gẹ́gẹ́ bí igbákejì. Ọrọ náà gbà ìṣirò diẹ nítorípé o lè ṣe atọna tàbí kó jẹ ijakulẹ fún. Ẹgbẹ́ òsèlú onígbaàálẹ̀, APC ti kí Igbákejì Ààrẹ Tẹ́lẹ̀rí, Atiku Abubakar kú oríire pẹ̀lú bí ó se jáwé olùborí nínù ìdìbò sípò Ààrẹ lẹ́gbẹ́ PDP. Àwọn orúkọ kọọkan ti n jẹ yọ lójú òpó ayelujara ṣùgbọ́n kò tí sí ìkéde kánkan pàtó lórí ìgbésẹ yí. Ṣáájú kí a tó mọ irú ẹni tí Atiku yóò yan, a ni kí a jijọ ṣe àgbéyẹ̀wò àwọn kókó pàtàkì tí o gbọdọ fi sọkan ki o to le yan ẹ́nikẹni ni igbákejì rẹ. Ẹsìn Òṣèlú Nàìjíríà ní àwọn ohun tó ya sọto pẹlú tí ibòmíràn. Nínú àwọn nnkán ti o sí le se atọna tàbí àkóbá fún Atiku Abubakar nípasẹ igbákejì to bá yan ni ẹsin ti ẹni náà bá n tẹlé. Ipa ti ko se fọwọ rọ sẹyin ni ẹsin nko ninu oselu Naijiria Kò fẹ sí oludije ààrẹ tabi ipo miran ti kí yan igbákejì to bá n ṣẹsin to yàtọ sí ti rẹ ki o ba ma da bí wipe o n gbé lẹyìn ẹsìn kàn. Fún ìdí èyí,o ṣeéṣe kí atiku mu ẹlẹsin Kristẹni ní igbákejì ààrẹ. Ọjọ́ orí Ọmọ ọdún méjìlelaadọrin ní Atiku Abubakar . Tí a bá sì wò bí ìpolongo fífún àwọn ọdọ ni ààyè nínú òṣèlú ti ṣe n lọ, òhun tó fẹ dájú ni wí pé,Atiku yóò yan ọdọ gẹgẹ bí igbákejì. Owó fọ́ọ̀mù APC fún ipò Ààrẹ gọbọi- olùdíje Pẹlú bí òun náà ti ṣe tẹnu mọ wí pé òun yóò faye gba awon odo ninu ìṣèjọba rẹ, kí ba da ti ọ bá bẹrẹ lórí yíyan igbákejì ọdọ Ẹyà Nínú ìwé òfin orílèèdè Nàìjíríà, kò sí àkọsílẹ wí pé èèyàn gbọdọ yan igbákejì láti ẹyà kan tabi òmíràn ṣugbọn kò sí olóṣèlú ti yóò yan igbákejì lalai woye ẹyà ti ẹni náà ti wa. Lọwọlọwọ lorílè-èdè Nàìjíríà, ẹyà Igbo kò fi taratara gba ti ìjọba Buhari pàápàá jùlọ lórí ọrọ atunto ti ọ bi ẹgbẹ bi Massob àti ipe fún ìdásílẹ̀ orílèèdè Biafra. Idibo ko ni waye ti wọn ko ba mu ọkọ mi jade Afọjusun òpó èèyàn ni pé Atiku yóò yan igbákejì láti ẹyà Igbo kí o bá lè rí ìyọnu wọn ati ìbò wọn lọdun 2019. Nínú àwọn tí orúko wọn ti n lédè bayi, o adabi ẹ́ni wi pe púpọ jẹ ẹyà Igbo. Ọkùnrin tàbí Obìnrin. Kí ọkùnrin rí ejò kì obinrin rí ejò... òwe yí gbà ọgbọn láti tù nípa yíyan ẹni tí yóò jẹ igbákejì Atiku. Tí o bá yan obìnrin gẹgẹ bí igbákejì oun ni yóò jẹ oludije akọkọ to lórúkọ ti yóò ṣe bẹ lagbo òṣèlú Nàìjíríà. Tí kò bá ṣe bẹ àwọn tó n já fún fífún àwọn obìnrin àti ọdọ ní ayé láti kópa nínú òṣèlú Nàìjíríà yóò bẹnu àtẹ lù. Ọrọ ba di ọba ran ni niṣẹ,odo ọba ya, iṣẹ ọba ko ṣe kọ, bẹẹ si ni odo ko ṣe kan lu. Botilewukori, ohun kan tó ṣe kókó ni pé tí yóò bá yan obìnrin,o gbọdọ jẹ obinrin tó jẹ ògúnná gbòngbò nínú òṣèlú tí òun náà sí le wọ èro fún Atiku. Òhun tí ẹgbẹ bá sọ Ẹgbẹ òṣèlú Atiku Abubakar ní ipá nlá láti kó nínú ìgbésẹ yiyan igbákejì fún un. Ní ọpọ ìgbà,ẹgbẹ a má yan igbákejì lẹyìn àgbéyẹ̀wò àwọn ìṣirò kọọkan gẹgẹ bí ẹni tí ẹgbẹ bá fẹ àti irú anfààní ti ẹni náà yóò mú bá àṣeyọrí nínú ìdìbò. Nígbà tí ìkọ BBC Yorùbá n ba akọwe ìpolongo fún ẹgbẹ PDP Ọgbẹni Kola Ologbondiyan lori boya ẹgbẹ yóò yan igbákejì fún Atiku,o ni ''àwọn yóò jọ pa imọran pọ ni ti àsìkò ba to.'' Aarẹ ana Olusegun Obasanjọ ti sọ tẹlẹ pe oun ko ni ṣatilẹyin fun Atiku Abubakar Nígbà tí Atiku náà du ipò Ààrẹ pẹlu Ààrẹ Olusegun Obasanjo lọdun 1999, ẹgbẹ òṣèlú PDP lo yan fún Obasanjo láti tẹ apá kan orílèèdè Nàìjíríà lọrùn. Lori ọrọ Aarẹ Obasanjo, ti a ba fi bi o ti ṣe n bẹnu atẹ lu Atiku,ko daju wi pe Atiku yoo yan ni igbakeji rẹ tabi ki Obasanjo tilẹ gbaruku ti Atiku ninu idijẹ fun ipo Aarẹ ni 2019. APC: Atiku fi owó ra ìbò tó gbé e wọlé ní PDP Ẹgbẹ Oselu APC ti ni Igbakeji Aarẹ tẹlẹri, Abubakar Atiku ko ni akọsilẹ rere lati le tukọ orilẹede Naijiria. APC fi eyi lede ninu atẹjade ti wọn fi sọwọ si awọn oniroyin lati fi ki Atiku ku orire bi o se jawe olubori ninu idibo abẹle ẹgbẹ oselu PDP lati fi yan oludije sipo aarẹ lọdun 2019. Ninu atẹjade naa, APC sọ wi pe iwa ibajẹ ti Atiku hu lọ jẹ ki oun ati Aarẹ orilẹede Naijiria tẹlẹri, Olusegun Obasanjo tako ara won. Wọn tun fi kun un wi pe orilẹede Amerika di eewọ fun igbakeji aarẹ tẹlẹri naa nitori iwa jẹgudujẹra ti o hu, eyi to fa a ti ilẹ Amerika fi n wadii rẹ lati fi jofin ijọba. Ẹgbẹ oselu APC wa fi kun un wi pe, gbogbo igba ti Atiku ba pinnu lati dije dupo ni o ma n ra ibo awọn eniyan ki o baa le bori. Saraki kí Atiku kú oríire, ó ṣèlérí àtìlẹ́yìn rẹ̀ ní 2019 Aarẹ Ile Igbimọ Aṣofin Agba, Bukola Saraki ti ki Atiku ku oriirẹ, o si tun fi atilẹyin rẹ han fun un lati jẹ ko ṣe aṣeyọri ni 2019. Saraki ni aṣeyọri naa yẹ Atiku ati wipe awọn ọmọ ẹgbẹ PDP ṣe daradara. Ninu ọrọ idupe rẹ, Saraki ni o jọ bi ẹni pe Naijiria ko ti i ṣetan fun oun o. Saraki dúpẹ́ lọ́wọ́ àwọn alátìlẹ́yìn rẹ̀ Bẹẹ naa ni Ibrahim Dankwambo to jẹ Gomina Ipinlẹ Gombe ṣe ileri wipe oun yoo ba Atiku ṣiṣẹ lati jẹ ko ṣe aṣeyọri. Lẹyin ti ẹgbẹ oṣelu PDP kede igbakeji aarẹ nigba kan ri, Atiku gẹgẹ bii ẹni to jawe olubori ninu idibo abẹle ẹgbẹ naa ni Port Harcourt, Atiku gboṣuba fun Aarẹ nigba kan ri, Oluṣẹgun Obasanjọ gẹgẹ bii ẹni to jẹ ki oun de ibi to de lonii. Atiku ni ti kii ba ṣe pe Obasanjọ yan oun gẹgẹ bii igbakeji rẹ laarin 1999 si 2007, oun ko ni wa nipo ti oun wa lonii. Aarẹ ana Olusegun Obasanjọ ti sọ tẹlẹ pe oun ko ni ṣatilẹyin fun Atiku Abubakar Eyi ni ọkan lara awọn oun ti Atiku sọ nigba ti oun dupẹ lọwọ awọn aṣoju ẹgbẹ naa to yan gẹgẹbii oludije. O tun sọ wipe lati igba ti oun ti n dije, oun ti kopa ninu idibo abẹle marun ọtọtọ. Atiku ni oludije fun PDP ni idibo 2019 Ọsan ọjọ Aiku ni ẹgbẹ́ oṣelu PDP kéde pé Atiku ló tó gbangba sùn lọ́yẹ́ láti kojú Buhari ni 2019. Atiku Abubakar ni PDP fa kalẹ̀ pé oun ati Buhari a jọ na an tan dupo aarẹ ni 2019 Awọn aṣoju 3, 274 ni wọn dibo ninu awọn ẹgbẹrun mẹrin (4, 000) to forukọsilẹ nigba ti wọn fagile ìbò 68. Eto idibo naa pari ni aago mẹfa kọja iṣẹju mẹrindinlogun. Ibo 1, 532 ni Atiku fi jawe olubori di oludije fun ẹgbẹ PDP lati dije dupo aarẹ Naijiria ni 2019. Ero awọn eniyan lori esi idibo to gbe Atiku wọle Awọn eniyan ti bẹrẹ si ni fesi si idibo to gbe Igbakeji aarẹ tẹlẹri, Abubakar Atiku lẹyin ti idibo abẹle ẹgbẹ PDP gbe wọle pẹlu ibo 1, 532 ni ipade gbogboogbo wọn. Lara awọn to fesi si idibo naa ni oju opo Twitter ba Atiku yọ pe owó ṣe pàtàkì pẹlu adura pé ko lè bori ninu idibo to n bọ. Awọn ọmọ Naijiria gbàá nimọran pe ki o fi gbogbo ipa rẹ sin orilẹ-ede Naijiria nitori awọn setan lati se atilẹyin si. Amọ, awọn ẹlomiran sọ pe magomago ko ni jẹ ki Atiku bori ni idibo to n bọ lọdun 2019, ti wọn si fi idibo ọdun 2019 we idibo Ọṣun to waye ni oṣu to kọja. Awọn elomiran bi Femi Fani-Kayode ti inu wọn dun si esi idibo abẹle PDP naa ni ki APC mura silẹ fun ogun. Esi idibo ni kikun Jonah Jang ni ìbò 19.; Datti Babà Ahmed ni ibo 05; David Mark ni ibo 35; Kabiru Turaki ni ibo 65; Sule Lamido ni ibo 96; Bafarawa Attahiru 48; Ibrahim Dankwanbo ni ibo 111; Makarfi Ahmed ni ibo 74; Kwakwanso Rabiu ni ibo 158; Bukọla Saraki ni ibo 317; Aminu Tambuwal ni ibo 693 àti Atiku Abubakar ni ibo 1,532. Àwọn oludibo Abia 106; Adamawa 76; Akwa Ibom 153 ṣugbọn 151 lo dibo; Anambra 54; Bauchi 76; Bayelsa 74; Benue 121; Borno 57; Cross River 95; Delta 150; Ebonyi 101; Edo 79; Enugu 126; Ekiti 109; Gombe 89; Kaduna 103; Kano 129; Imo 117; Jigawa 84; Katsina 102 ṣugbọn 101 lo dìbò; Kebbi 68 ṣugbọn 66 lo dìbò; Kogi 94 ṣugbọn 93 lo dibo; Kwara 102; Lagos 62; Nasarawa 52; Niger 83; Ogun 21; Ondo 64; Osun 89; Oyo 88; Plateau 76; Rivers 131; Sokoto 95; Taraba 93; Yobe 59; Zamfara 48 àti FCT 36. Bi ètò ìdìbò naa ṣe lọ Odiwọn iye awọn aṣoju to dibo lati ipinlẹ kọọkan ni yii: Awọn aṣoju ti bẹrẹ idibo lati yan ẹni ti yoo koju Buhari (APC) lọdun 2019. Awọn aṣoju 3274 ni yoo dibo naa lati ipinlẹ mẹrindinlogoji ati FCT Abuja. Awọn oludije mejila lo dije dupo ẹni ti ẹgbẹ PDP yoo fa kalẹ láti kojú Buhari ti ẹgbẹ AOC ti fa kalẹ bayii ni nu idibo sipo aarẹ Naijiria lọdun 2019. Awọn aṣoju ti n dibo yan ẹni ti wọn fẹ bi aarẹ ni PDP Ayẹwo awọn oludije ti pari Gbogbo àwọn oludije náà niroyin ni wọ́n kọ̀ láti yẹ̀ba fún ara wọ́n nítorí kálukú gbà pé òun lè ṣe é dáadáa Awọn mejila to n dije dupo asoju ẹgbẹ oselu APC ati awọn asoju wọn ti pari ayẹwo ki idibo to bẹrẹ si ipo oludije aarẹ ni abẹ ẹgbẹ oselu PDP. Lẹsẹẹsẹ ni awọn asoju naa joko lati bẹrẹ si ni di ibo yan ẹni ti wọn fẹ ko koju Aarẹ Muhammadu Buhari ninu idibo gbogbooogbo ti yoo waye ni ọdun to n bọ. Bakanaa, olorin takasufe ti igbalode to tun jẹ aburo oludije sipo gomina labẹ egbẹ oselu PDP ni ipinlẹ Ọsun, David Adeleke ti gbogbo eniyan mọ si ‘Davido’ naa ko gbẹyin nibi ipade gbogboogbo to n lọ lọwọ naa. PDP Convention 2018: Wọ́n ti parí àyẹ̀wò àwọn olùdíje fún ààrẹ ní PDP Papa isere Amaesimaka nilu Port Harcourt ni ipade gbogboogbo naa ti n waye ti n waye Eto ti to nibi ibudo ìdibo abẹle PDP ni Port Harcourt Oun gbogbo ti wa ni sẹpẹ fun ipade apapọ ẹgbẹ oselu PDP ni papa isere Amaesimaka nilu Port Harcourt. Oniroyin wa to jabọ lati ibi ti ipade naa yoo ti waye so pe nise ni awọn agbofinro duro digbi lati ri wi pe ohun gbogbo lọ leto leto. Awọn to n wọ agbegbe idibo naa ni a gbo wi pe awọn ọlọpaa n se ayẹwo finifini fun pẹlu irinsẹ ayẹwo igbalode. Ejò Sebe, Ọká, òjòlá àti àkeèké jẹ́ alábagbé Phillipe Oludije mejila ni yoo kopa ninu ibo abẹnu ẹgbẹ lati yan ẹni ti yoo koju Aarẹ Muhammadu Buhari ninu idibo Aarẹ ọdun 2019. Awọn onisọwo naa ko gbehin nibẹ Karakata naa si nlọ ni agbegbe naa paapa julọ fun awọn to ba fẹ ra asia ẹgbẹ tabi awọn ohun isaraloge miran lati fi se afihan pe ọmọ ẹgbẹ ni wọn. Jakejado Naijiria ni awọn asoju ẹgbẹ ti wa lati kopa ninu idpade apapọ yi Bi wakati naa ti se n sunmọ bọ ni awọn amoye ati ara ilu ti n bere ibeere pé: Tani yoo koju Buhari lati PDP? Awa naa ko le dahun ibere yi bi ki ba se wi pe a gbo abajade ibo abẹnu naa sugbọn oun ti a le se ni ki a se agbeyewo awọn oludije to lewaju larin awọn to n du ipo yi. Die ninu wọn re ati ohun to yẹ ki ẹ mọ nipa wọn. Bukola Saraki Bukola Saraki ni Aarẹ ile asofin agba Ninu akoso iṣejọba lorile-ede Naijiria, Sẹnatọ Bukọla Saraki lo wa ni ipo kẹta. Ọmọ bibi Ilorin to ti figba kan jẹ gomina ni ipinlẹ Kwara ni pẹlu iriri pupọ gẹgẹ bi aṣofin. Ọpọ lo ti n foju sii lara pe o ṣeeṣe ki o du ipo aarẹ, ko si jẹ iyalẹnu nigba ti o kede erongba rẹ lati du ipo Aarẹ nibi ipade ẹgbẹ awọn ọdọ ni Abuja. Awọn amoye n fi oju sii lara gẹgẹ bi ọkan lara awọn to le ri tikẹti ẹgbẹ gba ti ireti si wa wi pe ó le koju Buhari ninu idibo ọdun 2019. Atiku Abubakar ko fi igba kan sinmi nina ọwọ ife si awọn olori kakiri orilẹẹde Naijiria. Atiku Abubakar Atiku ni ti wọn ba yan oun sipo Aarẹ Naijiria, atunto isejọba ni oun yoo gbajumọ. APC Primaries: A ṣi n lọ sílé ẹjọ́ lóṣù tó m bọ̀ lórí ọ̀rọ̀ yìí Aminu Waziri Tambuwal Tambuwal fi igba kan sa kuro ninu ẹgbẹ PDP lo si APC Aminu Waziri Tambuwal jẹ olori ile asojusofin nigba kan ri. Lẹyin to sipo kuro ninu ẹgbẹ oselu PDP lo si APC, o du ipo Gomina nipinlẹ Sokoto ti o si wole gẹgẹ bi Gomina. Lẹyinwa igba naa ni o tun fi ẹgbẹ APC silẹ pada si PDP nibi ti o ti ferongba silẹ lati du ipo Aarẹ. APC Primaries: 'Kò sí 'Faction' ni Kwara APC rárá, NWC ti sọ̀rọ̀' Tambuwal ni ọpọlọpọ iriri gẹgẹ bi asofin ti awọn kan si ri gẹgẹ bi irawo ọjọ iwaju ẹgbẹ PDP. Nàíjíríà pé ọmọ ọdún 58 lónìí, ǹjẹ́ o mọ ìtàn ìbẹ̀rẹ̀ oílẹ̀-èdè rẹ? Rabiu Kwankwanso Lọdun 2015, Kwankwaso dije nibo abele APC sugbọn o fidiremi lọwo Buhari. O pe die ki Rabiu Musa Kwankwanso to sọ boya ohun yoo du ipo aarẹ labe asia ẹgbẹ PDP tabi ẹgbẹ miran. Sugbọn pẹlu atimaaṣebọ rẹ tẹlẹ ati awọn ipolongo ti awọn ololufe re n se lori ẹro ayelujara, ko ru ẹnikẹni loju pe o fẹ du ipo Aarẹ pẹlu Muhammadu Buhari. Ọmọ bibi ipinlẹ Kano ni Kwankwanso, o si jẹ ilumọọka oloṣelu ti o ti fi igba kan jẹ Minista ati Gomina ipinlẹ Kano ri. Kwankwaso kii se ajoji si ka ma du ipo Aarẹ sugbọn idije ọtẹ yi yoo fẹ le die fun un pẹlu bi ọrọ ko ti se wọ laarin oun ati Gomina ipinlẹ rẹ lọwọlọwọ, Abdullahi Ganduje. Ti Kwankwaso ba ribi ja tikẹti ẹgbẹ PDP gba fun ipo Aarẹ, o seese ki o ba Buhari fa ibo pupo to ma n saba wa lati ipinlẹ Kano. David Mark. Ko daju wi pe Mark yoo fẹ jọwọ ipo Aarẹ fun Saraki lọtẹ yi Ajagunfẹyinti ni David Mark sugbọn iriri rẹ ninu oselu Naijiria jẹ oun to lami laka. O ti saaju jẹ Aarẹ ile asofin agba Naijiria laarin ọdun 2007-2015. Mark wa lara awọn ogunna gbongbo ẹgbẹ oselu PDP lati ibere pẹpẹ ti ko si sipo kuro ninu ẹgbẹ titi di bi a ti se n sọrọ yi. Mark ni ti wọn ba yan oun gẹgẹ bi Aarẹ, ọdun meji loun yoo fi se atunto orile-ede Naijiria. Isoro rẹ bayi ni ki o ri tikẹti ẹgbẹ gba. Ọmọ àádọ́rin ọdun nii se. Sule Lamido Sule Lamido ati Aminu Waziri Tambuwal Sule Lamido ni o fẹ da bi wi pe ipolongo rẹ fun ipo Aarẹ ko gbode sugbọn kii se ẹni a a foju di. Ipinlẹ Jigawa lo ti wa nibi ti o ti jẹ gomina labẹ asia ẹgbẹ oselu PDP lọdun 2007. Ninu awọn to duro ti ẹgbẹ PDP nigba isoro lo jẹ ti awọn to mọ nipa oselu ko si ko iyan rẹ kere rara. Aarẹ orile-ede Naijiria nigba kan ri, Olusegun Obasanjo, nigba ti o n gba a ni alejo ni Ota so pe ''Lamido kun oju osunwọn lati dari Naijiria.'' Ti awọn ọmọ ẹgbẹ ba wo ti wi pe o duro gbagba ti awọn, o yẹ ki wọn dibo yan an gẹgẹ bi oludijẹ ẹgbẹ fun ipo Aarẹ. Àwọn tó n bọ Ṣàngó n jẹ iná níni ọdún Ọlọ́jọ́ Àwa obìnrin tó ń lépa afòjúsùn máa n ba ọkùnrin lẹ́rù ni -Toyin Lawani",0,yoruba tìkẹ́ gbfi yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa aráyé: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa aráyé: ti o nuni ti o ní wúlò fún àwọn.,0,yoruba Muhammadu Buhari London travel: Ìdí tí àwọn ọmọ Naijiria ṣe fẹ̀hónúhàn lòdì sí ìrìnàjò Buhari sí London,0,yoruba a ó pàdé o olúṣẹ́gun kòkúmọ́ àgàgú kí o kí wọn lọ́run alákeji ó tún dojú àlá olúṣẹ́gun ọkọ olúfúnkẹ́ sùn re o,0,yoruba "@user Yorùbá ní, ọmọ tí ó bá ṣípá ni ìyá ẹ̀ ń gbé. Níwọ̀n ìgbà tí ẹ bá ti pinu pé ẹ fẹ́ kọ́ ọ, kò s'éwu lóko àfi gìrì àparò. Mo ṣe tán.",0,yoruba RT @user: @user amin oh. Mo se amin Adura mo gbe ito adura mi! A kaaro oh. A ji bi? @user,0,yoruba "ìbàdandun àtọ́wọ́dá, àwọn oníṣẹ́ ìṣẹ́ ni a ní láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba "Abadofin yii, pẹlu aba ofin mẹrin miran nile igbimọ aṣofin ipinlẹ naa gbe kalẹ ni ọjọ Isẹgun lasiko ti ile joko. Wọn ni ofin naa yoo mu idagbasoke ba eto ẹkọ ni ipinlẹ naa ati igbelarugẹ isakoso ijọba ibilẹ ni ipinlẹ naa. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ninu atẹjade ile asofin naa, wọn ni awọn ti buwọlu aba ofin ọdun 2020 to sọ wi pe, ki wọn yii orukọ fasiti ipinlẹ Kwara kuro ni Abubakar Olusola Saraki University si Kwara State University. Ile igbimọ aṣofin naa fikun pe, awọn ti fi aba ofin naa ṣọwọ si gomina ipinlẹ Kwara, Abdulrahman Abdulrazaq lati buwọlu, ki o le di ofin. Abubakar Olusola Saraki, ti wọn fi orukọ rẹ pe fasiti ipinlẹ Kwara tẹlẹri naa, ni aarẹ ile asofin agba ni ọdun 1979 si 1983. Bakan naa lo jẹ oye Waziri ti ilu Ilorin, ki o to di wi pe o ku ni ọjọ Kẹrinla, ọdun 2012 ni ẹni ọdun mọkandinlọgọrin. Ìdílé Saraki láti ìran dé ìran, ló ti di ipò ńlá mú ní ìpínlẹ̀ Kwara láti ìgbà dé ìgba. Bakan naa ni ọmọ rẹ Bukọla Saraki jẹ gomina ipinlẹ Kwara, ki o to di wi pe o lọ si Ile Igbimọ Asofin Agba, ti o si di ipo aarẹ ile igbimọ asofin mu, titi di ọdun 2019 ti idibo gbogboogbo yọ ni ipo. Ìdílé Saraki láti ìran dé ìran ló ti di ipò ńlá mú ní ìpínlẹ̀ Kwara láti ìgbà dé ìgba. Ni ọpọ igba ni etò òṣèlú orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti salábàpàdé àwọn oríṣiríṣi ìdíle, tí wọn sábà ń dipò ńlá mú nínú ètò òṣèlú orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, látí ìran wọn kan sí ìran wọn míràn tó ń bọ̀.",0,yoruba ilẹ̀ agbègbè tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìwà: ti o ní wúlò.,0,yoruba "Ààrẹ Pierre Nkurunziza sọ níbi àpéjọ àwọn akọ̀ròyìn kan tí ó wá sáyé ní ọjọ́ 26 oṣù Kejìlá wí pé ohun ohun kò ní fẹ́ dídijú mọ́rí dájọ́ àmọ́ ó dìgbà tí a bá ti ṣánpá tí kò ṣe é ṣán mọ́ ni òun yóò tó ká a lérí , pẹ̀lú pé ó lè fi àṣẹ tí ó ń bẹ ní ìkáwọ́ rẹ da ẹjọ́ náà nù .",0,yoruba Títì tí àwọn ológun ti Abubacar mọ́lé jẹ́ ìpalára fún ẹ̀tọ́ rẹ pẹ̀lú mímú tí wọ́n mú un láìsí ìdí tí wọ́n fi ìdí ẹ múlẹ̀ .,0,yoruba ọsẹ àlùfáà. A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà.,0,yoruba "Eni to l'owo ti o n'iwa, asan l'oje"""""""" - #Yoruba adage https://t.co/K3Wsw0eRJe",0,yoruba / Aung Kyaw Htet / The Irrawaddy,0,yoruba Ta lo buru ju laarin Sango ati Ogun? (Audio) #Ogun #sango #yoruba https://t.co/8RcJG7dim3 https://t.co/H8pATm8Zmq,0,yoruba yìí ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba ó dàbí pé ẹni já sí kòtò níjọ̀ọ́sí ò kọ́ aráyókù lọ́gbọ́n kankan àbí báwo ni àwọn èyàn ṣe tún jóná mọ́kọ̀ agbépo,0,yoruba "yorubá tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba Ẹni ọdún bá ti bá láyé ó yẹ kó ṣ'ọpẹ́. #keresimasi #Yoruba,0,yoruba òní nípa ọ̀ṣun ìlú lo je ti ibile.,0,yoruba "mú, Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Nitori eyi, ara eni lo ni ọ̀gbọ́n.",0,yoruba "FRCN — tí a tún ń pè ní Radio Nigeria — ni ó léwájú nínúu iṣẹ́ẹ ẹ̀rọ - ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ ní orílẹ̀ - èdèe Nàìjíríà , pẹ̀lú ẹgbẹlẹmùkù àwọn olólùfẹ́ tí ó ń gbọ́ ọ jákèjádò Ìpínlẹ̀ Èkó th oríi ìkànnì mẹ́ta ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ , tí orúkọ wọ́n jẹ́ : Radio One 103 . 5 FM , Metro 97 . 7 FM àti aláràa gbàyídá inúu wọn",0,yoruba "tí Ọmọ fè lọ, Nitori eyi, ara eni lo ni ìgbà mi owó àkokò, Ọmọ lo fi.",0,yoruba "Pupọ ọmọ Naijiria lo ti pe fun gba ma binu latari isunsiwaju idibo Aarẹ Adinku ti wọn kede ọhun ni lati naira márùndínláàdọ́jọ (N145) lita kan si naira méjìlélógóje N142 tabi ogóje naira N140 Aarẹ ẹgbẹ naa Chindeu Okoronwo to ba ikọ BBC Pidgin sọrọ sọ pe onagba lati mu idagbasoke ba Naijiria ni awọn fi ṣe bẹẹ. ""Ohun ta gbero ni lati mu idẹkun ba awọn ọmọ Naijiria paapa jullasiko idibo yii. Ọna lati ṣe koriya fun awọn oludibo ni nitori pe ti eeyan ba jade lati dibo,ojuṣe rẹ pataki ni o ti ṣe yẹn.'' Janduku yinbọn nilu Iwara O ṣafikun pe adinku naa yoo bẹrẹ lati ọjọ Aje ti ṣe ọjọ kejidinlogun Oṣu keji titi di ọjọ kejila Oṣu kẹta ọdun 2019. Ọgbẹni Okoronkwo salaye pe kii ṣe ẹgbẹ oṣelu lo n gbe igbesẹ yi bi kii ṣe ẹgbẹ IPMAN. ""Ẹ ma jẹ ki a sọrọ nipa owo ti a o padanu.Alafia ti yoo mu ba ilu ni ki ẹ jẹ ki a sọ.A ko le ko iye owo kankan le nini alafia nilu'' Ko ti daju bi ikede yi yoo ti ṣe lapa lara owo irina amọ awọn eeyan n reti ki awọn awakọ din owo irina ọkọ ku nigba ti wọn ko nira epo to iye ti wọn n ra tẹlẹ. Ajọ eleto idibo Naijiria kede isunsiwajuiboAarẹ ati tawnile asofin orileede Naijiria lati ọjọ kẹrindinlogun Oṣu keji si ọjọ kẹtalelogun Oṣu keji ti idibo Gomina to yẹ ki o waye lọjọ keji Oṣu kẹta ti sun si ọjọ kẹsan Oṣu kẹta .",0,yoruba yoòbá ní gbàgbọ́ pé ẹ̀mí elédùmarè wà ńnú ẹni kẹ́ni tí í ba ṣe nǹkan àràmàndà tí wọn kò rí rí,0,yoruba "Akọwe ijọba ipinlẹ naa, Rafiu Ajakaye lo fi ọrọ naa lede ninu atẹjade kan to fi ṣowọ si BBC Yoruba. Atẹjade naa ni ""Logun jẹ ipe Eledumare lalẹ ọjọ Iṣẹgun lẹyin wakati diẹ ti esi ayẹwo fi han pe o ti ni arun Covid-19."" O tẹsiwaju pe ijọba atawọn eeyan ipinlẹ Kwara ti padanu ẹni iyi to sin ijọba ipinlẹ ọhun pẹlu gbogbo ọkan rẹ ki ọlọjọ to de. Iṣelẹ yii ti mu ki gomina ipinlẹ naa, AbdulRahman AbdulRazaq kede ọfọ ọjọ meje lati fi ṣedaro oloogbe ọhun. Lẹyin naa lo ni gomina ọhun ba ẹbi olori oṣiṣẹ ijọba tẹlẹri naa ati gbogbo awọn olugbe ilu Ilorin kẹdun iku rẹ. Akọwe ijọba pari atẹjade naa pe awọn ẹbi oloogbe naa atri ijọba yoo kede bi eto isinku rẹ yoo ṣe lọ laipẹ.",0,yoruba fi. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "Iroyin sọ pe ọgbọnjọ, oṣu Kejila, ọdun 2020 ni iṣẹlẹ naa waye. Botilẹjẹ pe ọmọdébìnrin naa si n gba itọju nileewosan, agbenusọ awọn ọlọpaa nipinlẹ Bauchi, DSP Muhammad Wakil sọ nkan ti awọn obi le ma a ṣe lati daabo bo awọn ọmọ wọn lọwọ irú awọn ọdaran bẹ ẹ. ""Nkan akọkọ ni pe ki awọn obi o ma a mojuto ìrìn ọmọ wọn; mọ ibi to wa, awọn to wa nibẹ pẹlu rẹ ati nkan to n ṣe."" Nkan keji ni pe da ẹnikẹni to ba n pe ọmọ rẹ ni ọkọ tabi iyawo mi, lẹ́kun. Idi ni pe nipasẹ iru nkan bẹ ẹ lo ti n bẹrẹ, titi ti nkan buruku yoo fi ṣẹlẹ. "" Ti o ba fi aaye gba ẹnikẹ́ni lati ma a pe ọmọ rẹ to jẹ ọmọde ni iyawo mi, o ma n mu ki iru ọmọ bẹ ẹ gba ki ẹni naa ṣe ohunkohun to wu si i."" Bi iṣẹlẹ naa ṣe waye Ọga ọlọpaa naa sọ pe iṣẹlẹ to ṣẹlẹ sì ọmọ ọdun mẹfa yii jẹ ọkan lara awọn nkan to buru ju ti oun riri gẹgẹ bi ọlọpaa. "" Eletutu ọlà kan lo ni ki awọn ọdọmọkunrin mejeeji lọ mu ojú ara ọmọdebinrin wa, ki wọn o le di olowo. Ohun lo mu ki wọn o fi ọgbọn tan ọmọ ọdun mẹfa naa pe awọn fẹ ẹ ran nisẹ. Nise ni wọn fi aṣọ penpe bo ẹnu rẹ, ti wọn si gbe lọ sinu ile kan ti wọn n kọ lọwọ. "" Ninu ile naa ni wọn ti fi nkan ge idọ 'clitoris' rẹ ti eletutu sọ pe yoo sọ wọn di olowo. Wọn fi ọmọ naa silẹ ninu agbára ẹjẹ, wọn si salọ. "" DSP Wakil tun sọ pe ọwọ ti tẹ ẹnikan lara awọn eeyan to ṣe iṣẹ ibi naa, sugbọn wọn ṣi n wa ẹnikan to ku ati ẹni to fẹ ẹ bá wọn ṣe etutu. Gomina ipinlẹ Bauchi, Bala Mohammed ti gbé miliọnu kan Naira silẹ fun itọju ọmọdebinrin naa, o si tun pasẹ fun awọn oṣiṣẹ alaabo lati se gbogbo nkan ti yoo mu ki ọwọ tẹ awọn meji to ku. Bakan naa ni dokita nileewosan ti ọmọ naa ti n gba itọju sọ pe owo ti gomina gbé kalẹ ti tẹ àwọn lọwọ, ati pe ara rẹ ti n ya diẹdiẹ. O ṣalaye pe awọn tun gbọ pe awọn eeyan kan n fi orukọ ọmọ naa tọrọ owo lori ayelujara. O ni ki awọn eeyan naa jawọ, nitori pe ijọba ti ṣèlérí lati san gbogbo owo itọju rẹ.",0,yoruba lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó wáyé.,0,yoruba eḳọ nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn aláìì wà ní ìṣẹ́ ọ̀pọ́lọ̀.,0,yoruba "Eto idibo ọhun to waye lalẹ tako aṣẹ ileẹjọ to sọ pe ki wọn si da etro idibo naa duro naa. Adajọ N. C. S. Ogbuanya ti ileẹjọ to n ri si ọrọ awọn oṣiṣẹ ọba niluu Eko lo fote le eto idibo awọn oloye ẹgbẹ tuntun. Ẹjọ to wa nile ẹjọ ọhun da le ẹjọ ti Ọgbẹni Hakeem Ojo Oyewo pe wi pe wọn yọ oun kuro gẹgẹ bi ọkan lara awọn oludije fun ipo aarẹ ẹgbẹ NULGE. Ofin yii si wa sibẹ, bẹẹ ni ko si le jẹ ki wọn ṣe eto idibo miiran titi ẹjọ naa yoo fi ni iyanju nile ẹjọ. Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lóri BBC Yoruba Amọ, ni idaji ni wọn dibo yan Kọmureedi Ayobami Olusegun Adeogun gẹgẹ bi alaga ẹgbẹ NULGE ipinlẹ Oyo. Nigba ti wọn kde rẹ tan gẹgẹ bi ẹni to jawe olubori ninu eto idibo naa, Kọmureedi Adeogun ṣeleri pe oun ko ni ja awọn ọmọ NULGE kulẹ. Alaga tuntun naa sọ pe oun ko ni ṣai maa tọ ipasẹ awọn to ti dipo olori mu ninu ajọ naa tẹlẹ. O gbadura wi pe ki Eleduwa jẹ ki oun ruure ki oun sọ ọ 're.",0,yoruba Àkójú ọ̀rọ̀ yi kún fún àwọn ìṣẹ́ tí ó wáyé..,0,yoruba nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọmọ lo lọ.,0,yoruba Ìṣàlàyé pánẹ́ẹ̀lì,0,yoruba "Lọjọ Aiku ni wọn bẹrẹ isẹ haji wọn nigba ti wọn pejọ silu Mina. bi oorun si ti yọ, lawọn omilẹgbẹ eeyan naa ti wọn da bii omi ninu asọ funfun, n gun oke Arafa yii, eyi to to kilomita mẹẹdogun si ila oorun ilu Mekkah, lẹyin ti wọn lo alẹ ọjọ kan lati sasaro ati ẹbẹ adura labẹ agọ ti wọn kọ fun wọn. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Obìnrin akunlé ìgbàlódé Lẹ́yin tawọn alarafa yii gbọ waasi tan ni mọsalasi Namira, ni wọn tun wa se adura Dhuhr ati Asr papọ ni ọna kukuru. Awọn alarafa naa yoo lo akoko wọn loke Arafa yii lati gbadura fun itẹwọgba isẹ haji wọn ati kika ẹsẹ iwe mimọ Alukurani titi ti oorun yoo fi wọ. Lẹyin ti oorun ba wọ, lawọn alarafa yii yoo morile Muzdalifah, to jẹ idaji irin laarin oke Arafa si ilu Mina, ti wọn yoo si duro di oru. Lẹyin ti wọn ba kirun Maghreb ati Isha papọ, ni wọn yoo wa bẹrẹ adura. Gbogbo awọn alarafa yii, ni ọkọ bọọsi ti fẹẹ ko de si inu agọ ti wọn se fun wọn naa, nigba tawọn miran fẹsẹ rin. Ijọba orilẹ-ede Saudi-Arabia ti wa pese awọn ohun eelo ati osisẹ to yẹ lati jẹki isẹ Haji naa lọ laisi wahala kan-kan, ko si tun yọri si rere. Koda, eto aabo to gbopọn, pẹlu osisẹ agbofinro to to ẹgbẹrun lọna ọgọrun ni wọn mu lati oniruuru ẹka to wa labẹ ileesẹ eto abẹle, ti wọn si pin wọn si awọn ibudo awn alalaji naa kaakirifun ipese eto aabo to peye Ìléyá ti dé, èran ọdún di jíjẹ! Ninu iroyin miran ẹwẹ, ijọba Ipinlẹ Eko ti fofin de iwa tita ẹran agbo l'awọn oju opopona kan nipinlẹ naa, nibayii ti bi ọdun ileya wọle de tan. Nigbati o n ba awọn akọroyin sọrọ, Kọmisọna fun ọrọ ayika nipinlẹ Eko, Babatunde Durosinmi- Etti sọ pe, o ṣe pataki fun awọn ara ilu Eko lati tọju ayika wọn, bi wọn ṣe n yọ ayọ ọdun. O fi kun ọrọ rẹ pe, ofin to de ọja tita loju popo naa lo de agbo tita loju popo nipinlẹ Eko. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Erelu Ọba Oṣunfunmike Ajike rèé tí wan tọrọ nídìí Ọṣun Kọmisọna naa tun gba awọn ara ilu Eko ni imọran, lati palẹ idọti wọn ninu ọdun, ki ayika wọn le mọ tonitoni, papaa julọ ki wọn o le dena ajakalẹ-arun. Ọjọ́ Iṣẹgun ati Ọjọru ni ìjọba Naijiria kéde fun ìsinmi. Ẹwẹ, Abdulrahman Dambazu to jẹ minista fun ọrọ abẹlẹ ni Naijiria kede pe ko ni si iṣẹ ni ójọ kókanlelogun ati ọjọ kejilelogun, oṣu kẹjọ, ọdun 2018 fun sisami ọdun Ileya. O rọ awọn ara ilu lati ṣe ọdun naa laisi wahala kankan ki wọn si lo asiko naa lati fifẹ han si ọmọnikeji wọn. Ọdun ileya jẹ ọdun nla fun àwọn musulumi ododo kaakiri agbaye. Ọ̀ṣun Oṣogbo 2018: Ulrich Salazar wálé ọdún láti New York Irun gígẹ̀ kọjá orí fífá lásán Ẹni ti ko riran to nlọ'ta ni Mushin Wùnmí Toríọlá: Toyin Abraham kìí se ọ̀gá mi nínú tíátà",0,yoruba "ti Nitori eyi, ara eni lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..",0,yoruba "Ẹ̀yin awo Brazil, ẹ mọ́ mọ̀ ba orò ilẹ̀ẹ wa yìí jẹ́ o! Nítorí owó àpèkánukò! #EseBoSeYe #Isese #Yoruba",0,yoruba ọgbọ́n díẹ̀ òmùgọ̀ díẹ̀ lọba fi ńto ìlú applying a little wisdom and a little stupidity is how a king administe,0,yoruba ibile. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò.,0,yoruba "Ọmọ fè lọ, Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé.",0,yoruba Sheffield United vs Arsenal: Evra ní Arsenal sì wà lọ́mọ ìkókó lẹ́yìn ọdún mẹ́wàá,0,yoruba 'Ilé ọba tójó ẹwà ló bùsi' So this Yoruba proverb about looking on the brighter side of life. Can you translate? ⠀ Gritinz | Celebrate your culture #yoruba #nigeria #africa #happybirthday #instaafrica #afrobeats #birthday #pulsenigeria #afroculture #davido #africa https://t.co/JjvpnoaEgy,0,yoruba rere. Ọba lo ni ìgbà àkerekere lo je ti ibile.,0,yoruba "Onírúurú ìròyìn ni ó ti rò ó wípé Ilẹ̀ - adúláwọ̀ ni àárín - ín gbùngùn òtòṣì àti ogun , síbẹ̀síbẹ̀ , Marie - Laurence Flahaux àti Hein De Haas , àwọn onímọ̀ láti Ifásitì ti Oxford àti Ifásitì ti Amsterdam , ní ṣísẹ̀ntèlé , kò gbà pé bẹ́ẹ̀ ní ó rí .",0,yoruba "Ọsẹ to kọja ni awọn ajinigbe naa kan lu aafin rẹ ni nnkan bii aago mẹjọ abọ aṣalẹ, ti wọn si ji i gbe lọ. Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ekiti, sọ fun BBC Yoruba pe ori ade naa ti bọ lọwọ awọn ajinigbe ọhun, o si ti pada sile lọdọ awọn ẹbi rẹ. Agbenusọ ọlọpaa naa ni: ""Mo fẹ sọ fun un yin pe awọn ajinigbe naa ti tu Kabiesi silẹ, o si ti pada silẹ lọdọ awọn mọlẹbi rẹ."" ""Wọn tu u silẹ lẹyin ti awọn akọṣẹmọṣẹ ọlọpaa kan lu inu igbo ti wọn gbe e lọ lati doola rẹ lọwọ awọn ajinigbe ọhun."" Ṣaaju ni iroyin kan ti kọkọ gbode pe awọn ajinigbe ọhun beere ogun miliọnu naira gẹgẹ bii owo itusilẹ lọwọ awọn ẹbi rẹ. Akomolede ati Aṣa lori BBC Yoruba: Ẹ̀yà Ara Ifọ̀ ní olùkọ́ Adedokun kọ́ wa Ṣugbọn Abutu sọ fun BBC pe ko si ohun to jọ bẹẹ, ati pe ileeṣẹ ọlọpaa ko le fidi rẹ mulẹ boya awọn ẹbi ọba alaye naa san owo itusilẹ kankan. Wọn ji ori ade naa gbe ninu aafin rẹ l'Ọjọbọ lẹyin ti awọn ajinigbe ọhun kọlu aafin rẹ, ti wọn si fo ogiri wọle. Iṣẹlẹ naa waye ni nnkan bii ọsẹ kan si asiko ti ọba Elewu ti Ewu-Ekiti, Ọba Adetutu Ajayi, ti kọkọ jajabọ lọwọ awọn kan ti wọn gbiyanju lati ji oun naa gbe. Ọpọ awọn ọmọ Yoruba kaakiri orilẹ-ede naijiria lo bu ẹnu ẹtẹ lu iṣẹlẹ naa pe o jẹ ohun itiju pe awọn ajinigbe gboju-gboya lati wọ inu aafin lọ lati ji odidi ọba gbe. aaaaaaaaaaaaaaa Èèmọ̀ wọ̀lú, Ajínigbé fo ògiri wọnú ààfin, wọ́n jí oríadé gbé l'Ekiti Yoruba ni iku to n pa ojugba ẹni, owe lo n pa fun ni, bi atẹgun ba si ti n gbe kẹtẹpẹ ogi, ayafi ki onilafun ma se afira. Ọba David Oyewumi, to jẹ Obadu ti Ilemeso-Ekiti, ni awọn ajijigbe ji gbe ninu aafin rẹ to wa ni ijọba ibilẹ Oye, nipinle Ekiti. Awọn ajinigbe naa fo iganna wọ inu aafin kabiesi, wọn si bẹrẹ si n yinbọ soke ki wọn to ji gbe lọ. Iṣẹlẹ yii lo n waye ni nnkan bii ọsẹ kan si asiko ti ọba Elewu ti Ewu-Ekiti, Ọba Adetutu Ajayi, bọ lọwọ awọn kan ti wọn gbiyanju lati ji oun naa gbe. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Oṣojumikoro kan sọ pe awọn ajinigbe naa lu ori ade ọhun atawọn ẹbi rẹ ninu aafin, ki wọn to gbe salọ. O ni ""inu aafin baba ni wọn ti gbe wọn lọ, awọn eeyan bii mẹrin fo ogiri wọle, ti wọn si n beere pe, baba da, baba da… eyi to n ṣafihan pe baba gan ni wọn wa wa. Sunday Igboho: Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọ̀n bàbá wa Ni kete ti wọn ri baba bayii ni wọn gbe wọn salọ."" Ọpọ awọn olugbe ilu naa to jẹ agbẹ, lo ti bẹrẹ si n sa kuro nibẹ nitori ibẹru awọn ajinigbe. Eti mi ko gbọ ri pe awọn ajinigbe wọ inu aafin lati gbe ọba lọ - Alawe ti Ilawe Ekiti Nigba to n fi idi isẹlẹ naa mulẹ fun BBC Yoruba, Alaga igbimọ lọbalọba nipinlẹ Ekiti, Ọba Adebanji Ajibade Alabi, tii ṣe Alawe ti ilu Ilawe-Ekiti ni iṣẹlẹ naa jẹ eyii to buru jai o si ba awọn lọkan jẹ gidi. O ni ""awa gẹgẹ bii ọba, ati gbe igbesẹ lori iṣẹlẹ naa, nitori ni kete ti a gbọ ni mo ke si ileeṣẹ ọlọpaa, awọn fijilante atawọn ikọ Amọtẹkun lati wọ inu igbo ti wọn gbe ọba naa lọ, lati wa a ri."" Ọba Ajibade Alabi sọ pe, o jẹ ohun ti eti ko gbọ ri ki awọn ajinigbe maa farapamọ sinu igbo ki wọn si gboju gboya lati wọ inu aafin lati ji odidi ori gbe. Gẹgẹ bo ṣe sọ, ""awọn Amọtekun n gbiyanju nitori awọn lo maa n wọnu igbo lọ lati lọ ṣọfintoto awọn ajinigbe, nitori naa, o yẹ ki ijọba ti wọn lẹyin, ki ijọba si pese irinṣẹ igbalode fun wọn lati ṣiṣẹ wọn."" Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik O rọ ileeṣẹ ọlọpaa lati fọwọsowọpọ pẹlu awọn ẹṣọ alabo miran bii ileeṣẹ ologun, awọn fijilante ati ọlọdẹ ilu lai yọ Amọtekun silẹ, lati wọ inu ogbo lọ lati le gbogbo awọn ajinigbeto wa nibẹ jade. Ọba Alabi ni itiju nla ni fun ilu pe awọn ajinigbe wọ inu aafin, ti wọn si ji ọba wọn gbe lọ lai si idiwọ kankan. Bo tilẹ jẹ pe o mẹnuba ikọlu ti awọn eeyan kan ṣe si ọba Ewu lọna ilu Ayetoro, alaga igbimọ awọn lọbalọba Ekiti naa ni iṣẹlẹ yii ni igba akọkọ ti wọn yoo ji ọba gbe ni ipinlẹ Ekiti. Ni ti awọn igbesẹ ti awọn lọbalọba n gbe nipinlẹ Ekiti lati dabo bo ara wọn atawọn eeyan ilu, Ọba Ajibade Alabi ni ipade ti n lọ lọwọ laarin awọn lọbalọba naa, ti oun ko fẹ mẹnuba. Female Car Painter: Èmi ní obìnrin àkọ́kọ́ tí yóò máa ṣiṣẹ́ akunmọ́tò ní Ibadan A ti ran awọn ọtẹlẹmuyẹ lati se awari Kabiyesi - Ileesẹ ọlọpaa Nigba ti BBC Yoruba kan si alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ekiti, ASP Sunday Abutu, o ni lootọ ni iṣẹlẹ naa waye, awọn si ti ran awọn akọṣẹmọṣẹ ọtẹlẹmuyẹ sinu igbo naa lati ṣawari kabiesi ọhun. Abutu ni iṣẹ ti n lọ lọwọ lati ṣawari oriade naa, awọn yoo si doola kabiesi ọhun laipẹ. O pari ọrọ rẹ pe, titi di akoko ti oun fi n ba BBC sọrọ, awọn ajijigbe naa ko tii beere owo itusilẹ kankan lọwọ awọn mọlẹbi ori ade ti wọn ji gbe ọhun. Oríadé míì nílẹ̀ Yorùbá tún kàgbákò ìkọlù agbébọn Awọn ikọlu to n waye nilẹ Naijiria lemọ lemọ yii ti di Egbirin ọtẹ, baa se npa ọkan ni omii n ru. Idi ni pe oriade kan nipinlẹ Ekiti, ẹni tii se ọkan lara awọn oriade pataki nipinlẹ naa, to tun jẹ Elewu tilu Ewu Ekiti, Ọba Adetutu Ajayi ni awọn gende agbebọn kan tun ti kọlu. Awọn gende agbebọn naa kọlu oriade yii lasiko to n ti ilu Ayetoro Ekiti to mule ti ilu rẹ bọ, se ni wọn si rọjo ọta ibọn si ara ọkọ ayọkẹlẹ rẹ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọba naa, to fi ara gba ọgbẹ ọta ibọn lori ko yọ lọwọ iku ojiji, to si ti n gba itọju nile iwosan aladani kan nilu Ado Ekiti. Torí àti ṣe Kòkò irin, bí mo ṣe máa ǹ fara yá iná nìyìí - Amokoko Saki A gbọ pe ẹsẹ, ọwọ ati ikun ni oriade naa ti fara gba ọgbẹ ọta ibọn, to si wa lẹsẹ kan aye, ẹsẹ kan ọrun bayii. Agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Ekiti, Sunday Abutu ti wa fidi isẹlẹ naa mulẹ, to si n fi ika hanu pe isẹlẹ naa waye lai naani pe awọn ọlọpaa n paraaro ipinlẹ naa lati de ikọlu awọn ọdaran. Àwọn ajínigbé bèèrè fún óúnjẹ àti suya kí wọ́n tó tú ọkọ, ìyàwó àtàwọn ọmọ sílẹ̀ l'Ondo Ara mee riri, mo rori ologbo latẹ. Awọn ẹbi Ọgbẹni Olisa Ibrahim iyawo atawọn ọmọ wọn mẹta ti sọ ohun ti oju wọn lakata awọn agbebọn to ji wọn gbe nipinlẹ Ondo. Ẹbi naa ti wọn jigbe lopopona Ajowa si Ayere kabba ṣalaye pe lara awọn nnkan tawọn ajinigbe ọhun beere fun ni ounjẹ to dun, ọti waini ati ẹran suya yatọ si owo. Ẹbi Ọgbẹni Ibrahim to n pada lọ si ibugbe wọn niluu Abuja lẹyin ọdun Ajinde lawọn ajinigbe ọhun kọkọ beere fun miliọnu mẹwaa owo itusilẹ lẹyin ti wọn gbe wọn lọ tan. Gbogbo wọn lo pada si ilu Ajowa-Akoko lẹyin ti wọn gba ominira tan lọwọ awọn agbebọn ajinigbe. Ohun ti a gbọ ni pe wọn san owo kan ki wọn to fi wọn silẹ, ṣugbọn ileeṣẹ ọlọpaa ko le fidi rẹ mulẹ. Niṣe lawọn eeyan n tu yaya lọ si ile wọn nibi ti wọn ti n ki wọn ku oriire pe aja to rele ẹkun to bọ, ki ki i ku ewu. Ipinlẹ Ondo yii naa wọn ti ji pasaitọ Fredrick Aramuwa gbe ti wọn si ṣekupa lẹyin ti a gbọ pe awọn ẹbi san owo gọbọi fawọn kọlọnbiti ẹda ọhun. Ariwo sọọ! Àwọn agbébọn jí ọkọ, ìyàwó àtàwọn ọmọ wọn gbé l'Ondo Awọn agbebọn kan ti ji idile ẹlẹni marun un gbe niluu Ajowa-Akoko, ni ijọba ibilẹ Ariwa-Iwọ-oorun Akoko ni ipinlẹ Ondo. Iroyin ni awọn eeyan naa n rinrinajo lọ si Abuja lati Ajowa-Akoko, nibi ti wọn ti lọ ṣe ọdun Ajinde ki awọn ajinigbe ọhun to ka wọn mọ abala kan ti ko dara loju ọna naa. Gẹgẹ bii ohun ti a gbọ, wọn ji olori ẹbi naa, Ibrahim Olusa plẹlu iyawo atawọn ọmọ rẹ gbe loju ibọn laarin Ajowa-Akoko si Ayere ni ipinlẹ Kogi, wọn si ko gbogbo wọn lọ sinu igbo kijikiji. Wọn ni awọn ajinigbe naa ti kan si ẹbi awọn ti wọn ti je gbe lati bere miliọnu mẹwaa naira owo itusilẹ wọn. Isẹlẹ naa si ti mu iporuru ba ọkan awọn eeyan ilu ọhun. 'Bí ojú ọ̀nà agbàrá òjò tí ijọba ṣe n'IIorin ṣe ń pa àwọn ọmọ iléèwé wa rèé! Ẹ sàánú wa' Ọkan lara awọn adari ilu naa, to tun jẹ alaga igbijmọ adari Ajowa-Akoko ana, Ajayi bakare to fidi iṣẹlẹ naa mulẹ sọ pe ijinigbe ati idigunjale n peleke sii lagbegbe nitori ọna ti ko dara ni iha ipinle Kogi. Bakare wa ke si ijọba lati tun ọna naa ṣe ni kiakia lati le ṣadinku iwa ọdaran lagbegbe ọhun. Àwọn èdè abẹ́ ahọ́n tóo lè fi sọ̀rọ̀ rèé láì tú àṣírí ọ̀rọ̀ rẹ áyé",0,yoruba "bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ opo àwọn ọmọ ẹgbẹ́ tó darapo sugbon ẹ máa gba pe nkan bíi ọdún mẹ́ta ààbò seyin kii se nkan tó rọrùn rárá, mo sì gbà pé kò derun rárá fáwọn èèyàn."""""""""""""""" @user",0,yoruba sí ìbàdandun láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó jẹ́ dára jù...,0,yoruba ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa aráyé: ti o ní wúlò.,0,yoruba Àmọ́ púpọ̀ nínú àwọn ilé wọ̀nyí ni ó ti wó láti ọjọ́ pípẹ́ .,0,yoruba @user Ara le koko bí ògún àgbẹ̀dẹ. Ẹ kú àmójúbà wa :) Òtútù ló kàn pọ̀ díẹ̀ o.,0,yoruba "Ọjọ kẹrindinlogun, oṣu kejila, ọdun 2010 ni Barrister dagbere faye ni ile iwosan kan nilu London. Ẹbi. ọrẹ ati awọn ololufẹ rẹ ni wọn n ṣeranti Barrister lonii. Ibẹrẹ igbe aye Sikiru Ayinde Barrister? Ogbeni Salawu Balogun, alapata ẹran lo jẹ baba to bi Sikiru Ayinde Barrister nigba ti iya rẹ jẹ oniṣowo pẹẹpẹẹpẹ. Wọ̀n bi Barrister ni ọjọ kẹsan-an, oṣu Keji, ọdun 1948 sinu ẹbi Salawu Balogun nilu Ibadan. Iṣẹ alapata ẹran ni baba rẹ n ṣe, iya rẹ si jẹ oniṣowo. Barister lo bi gbogbo oníṣẹ́ fújì -Oṣupa Sikiru Ayinde lọ si ile ẹkọ alakọbẹrẹ Muslim Mission School, ati Model School ni Mushin, nipinlẹ Eko. Lẹyin naa lo k nipa bi iwe titẹ ati awọn iṣẹ ọfiisi mii nile ẹkọ giga Yaba Polytechnic. Lati ọdọ ni Ayinde Barrister ti bẹrẹ orin kikọ pẹlu ẹka ori 'Were'. Asiko awẹ Ramadan ni wọn ma n kọ iru orin yii lati ile kan si ile mii. O siṣẹ atẹwe nileeṣẹ to n ṣe ọti, Nigeria Breweries. Lẹyin naa lo ṣiṣẹ akọwe nileeṣẹ ologun Naijiria lasiko ogun abẹle. O jẹ ọmọ ogun labẹ idari Ọgagun Adeniran, o si jagun nilu Akwa, Abagana ati Onitsha. Nigba to pada de lati oju ogun, wọn gbe e lọ si olu ileeṣẹ ologun to n ṣe ifimufinlẹ, ni Apapa nilu Eko, ko to o tun lọ si Army Resettlement Centre ni Oshodi. O kuro ninu iṣẹ ologun, lo fi di olorin Fuji patapata, to si da ẹgbẹ akọrin rẹ 'Supreme Fuji Commanders' silẹ. Irianajo rẹ gẹgẹ bi olorin Fuji Lọdun 1966, Sikiri ayinde Barrister gbe rẹkọọdu orin rẹ akọkọ jade. Lasiko naa, ibi ariya ni oun ati awọn ọmọ ẹgbẹ rẹ ti ma n kọrin ni awọn agbegbe Ebute Meta, ati fun awọn ololufẹ rẹ ni Mushin. Ayinde Barrister lasiko to n kọrin nibi ariya kan nilu Eko lọdun 1976. Ololufẹ rẹ kan si n na a lowo loju agbo. O pada gbe awọn rẹkọọdu mii jade labẹ ileeṣẹ African Songs Ltd, ko to o da ileeṣẹ ti ẹ, Silky-Oluyole Records, silẹ. Nigba ti yoo fi di ọdun 1980, Ayinde Barrister ati orin Fuji ti di itẹwọgba laarin gbogbo ẹsin to wa ni Naijiria. Lọdun 1982, ija nla waye laarin Kollington Ayinla, to jẹ ọrẹ rẹ, ati olorin Fuji mii. Ọrẹ ni Ayinde Barrister ati Ayinla Kollington nigba aye rẹ. Barrister gbe orin kikọ de ilẹ okeere, to si ṣe ariya ita gbangba ni awọn ilu bi London lọdun 1990 ati 1993. Eyi lo bi orin Fuji Garbage. Orin Fuji ti Sikiri Ayinde Barrister kọ nigba aye rẹ jẹ akojọpọ Apala, Sakara, Awurebe ati awọn mii. Aworan yii ṣafihan Ayinde Barrister nibi ayẹyẹ to ti gba ade gẹgẹ bi olorin Fuji to dara julọ lọdun 1977. Ẹni ọdun mọkandinlọgbọn ni lasiko naa. Orin rẹ si ma n da lori aṣa, ikilọ iwa, ibọwọ f'agba, oṣelu ati igbokegbodo eeyan laye. O si tun ma n fi orin ki awọn gbajumọ ni awujọ. Ọpọlọpọ ami idanilọla ni Ayinde Barrister gba fun iṣẹ orin kikọ. Lara wọn ni idanilọla pẹlu Member of the Order of the Federal Republic (MFR), ti Aarẹ Olusegun Obasanjo fun lọdun 2006. Awọn rẹkọọdun orin ti Sikiru Ayinde Barrister gbe jade nigba aye rẹ ni Sikiru Ayinde Barrister ṣiṣẹ ologun, ko to o di olorin Fuji patapata. Koda, o ja nibi ogun Biafra. Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsèjẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọ Africa Eye: Wo ìtàn ìyá kan ìyá kan àtàwọn olè ajọ́mọgbé tó n ta ọmọ ní Kenya Kollington ṣàlàyé bí orin Fuji ṣe bẹ̀rẹ̀ gan an ní Nàiìjíríà A ko le sọ daju pe gbogbo orin to kọ niyii. O ṣe e ṣe ki awọn mii wa ti a ko mọ.",0,yoruba "yi lo ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba oníṣẹ́ ìṣẹ́ ni a ní nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìwà: ti o nuni ti o dun.,0,yoruba "Ọ̀nà àrìn yè. Ẹyẹ kì í f'orí sọgi, bẹ́ẹ̀ sì ni ìkọ́ kì í kọ́ ọmọ ejò lẹ́sẹ̀, bí ọkọ̀ bá re òkun re ọ̀sà, dandan ni kí ó fi orí lé èbúté. Àlọ ire, àbọ̀ ire ni ìpín in wa láṣẹ Ọba Aláàbò. #iwure",0,yoruba Lateef Adedimeji àti Bimpe Oyebade sọ bi ìrìnàjò ìfẹ́ ṣe bẹ̀rẹ̀ láàrin wọn,0,yoruba ibile. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìṣẹ̀: ti o ní wúlò.,0,yoruba lòdì Ìbàdàn. Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.,0,yoruba "Ní ọdún díẹ̀ sẹ́yìn , ọ̀pọ̀lọpọ̀ iṣẹ́ ńláǹlà bíi kòtò ìdarí - omi ṣíṣàn fún Ìpèsè Iná Mànàmáná ti lé àwọn olùgbé jìnà ó sì ń ṣe àkóbá fún nnkan ìṣẹ̀dá odò náà .",0,yoruba "Kò sí bí ìgbẹ́ ṣe lè ta kókó tó, erin óò kọjá. #Owe #Yoruba",0,yoruba Àwọn Krìstẹ́ní Yoruba Nation kọ̀wé sí CAN láti pínyà!,0,yoruba "ní láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó ṣe pàtàkì.,0,yoruba O lòdì si òfin ki ènìkéni fi o si inú ìjìyà tàbí íróra nipa kpe o se e ni ìsekúse. #Law2go #HumanRightsinNigeria #Section34 #Yoruba,0,yoruba "RT @user: Ki eni sanwa o amin""""""""""""""""@user: Óyá mó ti dá'mi sí wájú, kí ng wá máa tẹ'lẹ̀ tútù.""""""""""""""""",0,yoruba "lo joko. Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.",0,yoruba "Ara ìjọba wa ni àléébù t'ó jù ú wà, ìjọba la óò fi ẹ̀sùn kàn kí a tó ó f'ẹ̀sùn kan alẹ́nulọ́rọ̀. @user #IjobaWaKala #Nigeria",0,yoruba "Ní ọjọ́ kejìdínlọ́gbọ̀n oṣù Belu ọdún 1990 , àwọn ẹgbẹ́ ológun yẹgi fún ọkùnrin méjìdínlọ́gbọ̀n tí a fi ìfarabalẹ̀ ṣà lọ́kọ̀ọ̀kan láti pa nínú ẹ̀wọ̀n láàárín òru , ní Inal ní orílẹ̀ - èdè Mauritania lẹ́yìn tí a fi ẹ̀sùn ìpète - lati - gba - ìjọba kàn wọ́n .",0,yoruba "Adìẹ funfun ò mọra rẹ̀ l'ágbà, a dífá fún #Carl #Lewis tó nsọ̀sọkúsọ nípa #Usain #Bolt #london2012",0,yoruba "ayẹwo wey ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "RT @user: Ẹni tó ńsáré tó ńwo ẹ̀hìn, ó di dandan, kó fi ẹsẹ̀ kọ. / Whoever keeps looking back while running, will certainly stum…",0,yoruba "Ọpọ awọn ọmọ orilẹ-ede India lo gbagbọ pe alawọ funfun dara ju alawọ dudu lọ Ajọ ọlọpaa Rajasthan sọ pe baba oloogbe naa fi ẹsun kan ọkọ obinrin ọhun pe, oun lo ṣokunfa bi oloogbe naa ṣe gba ẹmi ara rẹ. Baba obinrin naa sọ fun awọn ọlọpaa pe, ọkọ obinrin naa maa n fi ṣe ẹlẹya nitori pe aawọ ara rẹ dudu pupọ, idi ree ti obinrin ọhun naa ṣe pa ara rẹ. Awọn ọlọpaa Hindi sọ fun BBC pe, ọkọ obinrin ọhun ko tii ṣorọ lori ẹsun ti wọn fi kan an. Ọpọ awọn ọmọ orilẹ-ede India lo gbagbọ pe obinrin ti aawọ ara rẹ ba pupa tabi to funfun dara ju alawọ dudu lọ. Iṣẹlẹ yii kọ ni igba akọkọ ti obinrin India yoo gba ẹmi ara rẹ nitori ifiniṣẹsin ati idẹyẹsi to jọ mọ aawọ dudu lorilẹ-ede India. Gẹgẹ bi ọrọ ti ọlọpaa sọ, obinrin ẹni ọdun mọkandinlọgbọn kan pa ara rẹ lọdun 2014 lẹyin ti ọkọ rẹ fi ṣẹlẹya lataari pe o dudu pupọ. Bẹẹ naa ni lọdun 2018, ọmọ ọdun mẹrinla kan gba ẹmi ara rẹ, lẹyin ti wọn ni awọn akẹgbẹ rẹ nile iwe fi ṣẹ yẹyẹ, ti wọn si pe e ni oburẹwa, nitori pe o jẹ eeyan dudu. 'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan'",0,yoruba "pataki. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọmọ lo ni Nitori eyi, ara eni lo ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba RT @user: Edumare Oba ma pa IYA MI L'EKUN @user AKU ODUN º°˚˚°º http://t.co/tsTLD4Ld7y,0,yoruba "Nibi ayẹyẹ ajọdun aṣa ọdun yii ni ipinlẹ Ekiti, oniruuru ohun tẹ o tilẹ mọ pe o wa laye yii lẹ o ri nibẹ. Adari ileeṣẹ Aṣa ni ipinlẹ Ekiti, Wale Ojo sọ fun BBC Yoruba pe awọn n ko awọn aṣa awọn jade lati ṣe afihan rẹ faraye ni. ""A sọ ijó di owó, ohun t'ọ́kùnrin ń ṣe l'Ekiti, obìnrin lè ṣe é"". Ọgbni Wale sọ pe Ekiti Festival ti mú ọlá àti oríire wọ ìlú Ekiti, ""o n gbe ọgbọn inu ati imọ awọn ọdọ jade sita"". O tẹsiwaju pe gbogbo ìlú tó wà ní Africa ló kù tí Ekiti máa fìwé pè lọ́dún 2020 lati wa wo ọgbọ, imọ ati oye ti Ọlọrun fi sọlẹ si ilu Ekiti. Lóòtọ́ lóòtọ́, kò sí àṣàdànù nínú àwọ́n afihan ohun agbaṣa ga to waye nibi EKiti Festival 2019. Marlian, òfégè ìgbéyàwó Buhari, Fatoyinbo àtàwọn ìṣẹ̀lẹ̀ ńlá tó mi ìgboro tìtì ní 2019 Bukola Saraki fi 'Gbas Gbos' ọ̀rọ̀ ránṣẹ́ lórí 'ilẹ̀ bàbá rẹ̀' tí ìjọba Kwara gbà padà Oluwo àti Olorì àná, Chanel Chin tahùn síra Lórúkọ ìdílé Diya, a gbúdọ̀ ti ẹsẹ̀ òfin bọ ìkú tó mú ọkọ àti ọmọ méjì lọ - Agbẹjọ́rò Ṣé ẹ mọ̀ pé Ekiti ni ìlú tí Ògún Lákááyé wọlẹ̀ sí? Ilu Orunmila naa, Ekiti ni. Eṣu tó ma ń dá àbò bo àwọn èèyàn tirẹ̀, Eṣu Ẹlẹ́gbẹ̀rà to maa n gba awọn eeyan lọjọ ibi ba de, ilu Ekiti ni gbogbo wọn ti wa gẹg bi adari aṣa ipinlẹ naa ṣe sọ ọ. Iyawo gomina ipinlẹ Ekiti, Erelu Bisi Fayemi kadi eto ajdun naa pẹlu rọ̀ iwuri nipa Ekiti pe ""Orin Ekiti dá yàtọ̀, ijó wọn, oke nla nla atawọn nkan to jẹ pe owo lawọn eeyan fi lọ n wo wọn nibomiran"".",0,yoruba ayẹwo wey ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó wáyé..,0,yoruba Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ìyá lo tun se joko.,0,yoruba "Ijọba Osun ṣalaye loju opo Twitter rẹ pe ni bii ago mọkanla alẹ Ọjọru ti Oba Adedeji dagbere faye. Ko si ẹni to le sọ pato ohun to ṣekupa Akirun ilu Ikirun lẹni ọdun mejidinlọgọrin. Ohun ti a gbọ ni pe Akirun ṣe aisan diẹ ki Ẹlẹmi to gba a lalẹ Ọjọru. Bi ọgbọn ọdun sẹyin ni Oba Adedeji gori itẹ baba rẹ nilu Ikirun. World Cancer Day: Mo pàdánù ọkọ àti ọ̀rẹ́ bí mo ṣe ni 'Cancer'- Iwalade Adebimpe Adetunji Ọpọ eeyan lo ṣapejuwe Oba Adedeji to jẹ oṣiṣẹ banki tẹlẹ ki o to jọba pe musulumi ododo ni. Ogunna gbongbo ẹgbẹ musulumi nii ṣe nilu Ikirun ati ni ipinlẹ Osun lapapọ nigba aye rẹ. Ọdun 2002 ni Oba Adedeji lọ si ilẹ mimọ ni ilu Mecca. Oun ni baba iṣalẹ ẹgbẹ musulumi Ibadu-Rahman Society ati Anwar-Ul-Islam niluu Ibadan nigba aye rẹ. Oba Adedeji lo ọrọ rẹ Eledua yọnda fun un lati ṣe iranwọn fawọn ti ko rọwọ họri lawujọ. Big breast: Oluwatosin Adegboro, Oluwaseun Amoo, Remi Fatolu: Ẹlòmíì ń fi irú ọyàn wa tọrọ Ìròyìn Yàjóyàjó -'Akirun ti Ìlú Ìkìrun,Oba Abdul-Rauf Olayiwola Adedeji II ti wàjà Ọba Akirun ti Ikirun, Oba Abdul-Rauf Olayiwola Adedeji II ti jade laye. Eni ọdun mejidinlọgọrin ni ọba ni ipinlẹ Osun naa ki wọn to jade laye. Akomolede ati Asa Ondo: Wo ìdí tí Yorùbá ṣe ń lo Ìjàpá ni olú ẹ̀dá ìtàn Àlọ́ Àpagbé- Oyelo",0,yoruba "Edgal Imohimi lọ ṣaaju ikó to lọ ile ooṣa naa Ọga ọlọpaa ipinlẹ naa, Edgal Imohimi lọ ṣaaju ikó to lọ ilé òòṣà naa ni bi ti wọn ti ri ẹrọ agbowó (POS) mẹta. Awọn afunrasi mẹta ni ọlọpaa gbamu ni ile òòṣà naa. Edgal ni wọn yoo ṣ'alaye oun ti POS n ṣe ni ile ooṣa nitori iwadii fi han pe awọn adigunjale naa maa ń gbe ẹrọ agbowọ naa kaakiri ti wọn ba ti lọ ṣọṣẹ lati fi tipatipa gba owo lọwọ awọn to ba wọ panpẹ́ wọn. Ọga ọlọpaa naa ni oun ni igbagbọ pe awọn ọmọ ẹgbẹ OPC maa n fi tipatipa mu awọn ti wọn ba fa wa s'ile ooṣa naa mọlẹ̀. Edgal ni ṣe lo yẹ ki awọn ọmọ ẹgbe OPC maa fa ẹnikẹni ti wọn ba mú lé ọlọpaa lọwọ.",0,yoruba Ohun tí ó jẹ́ ìwúrí ní ti àwọn ọ̀rọ̀ àyálò nínú èdè Yorùbá ni bí àwọn ènìyàn ṣe ń lò wọ́n nínú ìtàkùrọ̀sọ lójoojúmọ́ bí wọ́n ṣe ń ṣàn wọ inú èdè náà .,0,yoruba "ìbàdandun àtọ́wọ́dá, àwọn oníṣẹ́ ìṣẹ́ ni ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Yorùbá wúre, a ò ní bá olóríburukú pàdé, olóṣì ò ní kóṣì bá wa. Ẹni àìjírí, ẹni àìjíkò ò ní kò wá. #IgbagboYorubaNipaAje",0,yoruba "Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn ló ti pàdánù ẹ̀mí wọn ní Zamfara l'ọ́dún 2018. Ọpọlọpọ lo ti fi ohun wọn sita loju opo Twitter lọjọ isinmi lati fi aidunnu wọn han si bi ""ọpọlọpọ eniyan ṣe ti padanu ẹmi wọn ni ipinlẹ Zamfara lati igba ti ọdun 2018 ti bẹrẹ."" Awọn kan ni ki ijọba apapọ ṣe iru akitiyan to ṣe si ipaniyan to n waye l'awọn ibomi i ni Zamfara naa. End of Twitter post, 1 Awọn kan bu ẹnu ẹtẹ lu Aarẹ Muhammadu Buhari pe 'ko ni ko awọn ọlọpa ati ọmọ ogun lọ si ipinlẹ Zamfara bo ṣe ko wọn lọ si Ekiti lasiko eto idibo gomina to waye nibẹ. Wahala eyi to waye kẹhin lọsẹ to kọja mu ki awọn eniyan kan padanu ẹmi wọn, t'ọpọlọpọ si di alainilelori nitori bi awọn onikupani naa ṣe dana sun awọn ile wọn l'awọn abule kan mejidinlogun nijọba ibilẹ Zurmi. Ẹwẹ, ìṣẹlẹ iṣekupani naa ti mu ki ogunlọgọ eniyan maa fi ibugbe wọn silẹ ki wọn o maa ba tun sẹ kongẹ iru iṣẹlẹ bẹ mọ.",0,yoruba """"""""" , àti """""""" bóyá àwọn ẹranko wọ̀nyí ti dínkù sí ti ìgbà kan , kí ni ìwọ rò wípé ó ti ṣẹlẹ̀ ?",0,yoruba "Ṣugbọn wọn o ba a mọ nibi awọn nkan to ṣee foju ri lawujọ nikan o, wọn tun n ṣe igbelarugẹ ọrọ ibalopọ laarin lakọ labo. Eyi fun awọn eeyan lanfani lati maa sọrọ bi wọn ṣe n ba ara wọn lo pọ tabi bo ṣe wu wọn lati ṣe e tabi bi bi wọn ṣe n ni imọlara rẹ lasiko ibalopọ. Sọrọ ori rẹdio yii ba kii fi para rara bẹẹ si ni kii ṣẹ ẹnu rẹ ku nipa ọrọ ibalopọ. O ba BBC sọrọ nipa bo ṣe maa n ran awọn obinrin lọwọ lori eto rẹ, koda bo ṣe maa n lọ kọ wọn ni ere idaraya to lee mu ara wọn dide fun ibalopọ.",0,yoruba "Aláké Òdí, ló ṣe ilé de baba rẹ̀ lórí ipò ọba. Asẹ̀ ni ó jọba lẹ́hìn tí Aláké Òdí wàjà. Asẹ̀ bí Ikin. Ikin bí ìbejì, tí orúkọ wọn ń jẹ́ Ọbátúapá àti Ọ̀pálápá. Ní àsìkò tí Ọbátúapá yóò jọba, ó ní wọ́n ní láti fi Kẹ́hìndé òhun náà jọba. Ọbátúapá jẹ Arẹ̀sà Adú",0,yoruba Orí ò! Jí wa 're lóòórọ̀,0,yoruba "Ọba fè se, Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.",0,yoruba "lọ yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "COVID-19: Ìjọba Nàìjíríà kéde ìlànà tuntun lórí COVID-19, Ó mú àdínkù bá ìye èèyàn tó lè wọ ṣọ́ọ̀ṣì, mọ́sáláṣí",0,yoruba "@user Èmi gan-an ti gbìyàjú ẹ̀. Mo ti pààrọ̀ ti ẹ̀yìn, ó ku ti'wájú tó ṣòro ṣe. Òun náà ni wọ́n fi ṣo ọ́ lórúkọ """"""""""""""""""""""""""""""""iPhone Fọ́"""""""""""""""""""""""""""""""" :)",0,yoruba odi arinako pa kasunmu yorùbátv ẹgbẹ ọmọ olúwa bí gbogbo àgbáyé ojú òpó ìkànsíraẹni yoruba tv,0,yoruba Àwọn kan gbèrò wọ́n fẹ́ gbé àjọyọ̀ Kérésìmesì fi ẹ̀gbẹ́ kan ẹ̀gbẹ́ pẹ̀lú ìrẹ̀sílẹ̀ ìlú tí ó wáyé ní 160 ọdún sẹ́yìn .,0,yoruba ifisipo pelu etan ti ko fara pamo ṣé ìdìbò ni tòní àbí ìfisípò,0,yoruba "Ní igba mi owó àkokò, Ọmọ lo ìgbà ọkọ.",0,yoruba "mú, Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba "À ń fi epo jẹ iṣu pẹ̀lú - òwé """"""""""""""""iṣu ẹni ní í ti ọwọ́ ẹni í bọ epo"""""""""""""""". #Epopupa #Owe #Yoruba #Proverb",0,yoruba Muslim prayers: Wàhálà n rúgbó bọ̀ ní ìlú kan ní India nítorí bí àwọn Musulumi ṣe n kírun,0,yoruba Ìlú yorubá lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó.,0,yoruba èèééoo ẹ kú orí ire o nígbà wo ni ìpàdé yín,0,yoruba "Ina jo ọja binukonu lọjọta nipinlẹ Eko Eyi ni ẹlẹẹkẹta ti ina yoo jo ọja yii laarin ọdun mẹta. Ọja Binukonu jamba ina ni ọdun 2015 ati ni oṣu kọkanla ni ọdun 2017. Awọn alẹnulọrọ sọ fun ileeṣẹ BBC wipe iṣẹlẹ ina yii ṣadeede bẹrẹ ni agogo kan abọ oru ti o si jo awọn ile itaja (ṣọọbu) ti o to aadọta patapata. Eyi ni ẹlẹẹkẹta ti ina yoo jo ọja Binukonu lẹyin ti ọdun 2015 ati 2017. Awọn onisowo gbìyànjú lati ṣaajo awọn ọja wọn lati ko wọn kuro ninu awọn ile itaja wọn ṣugbọn ẹpa ko boro mọ. Alhaja Rehanat Salami, Obinrin oludari ọja naa (Iyalọja) sọ pe ina mọnamọna ijọba lo ṣe okunfa ijamba ina naa. O sọ pe, ""Mi o wo agogo nigbati mo gba ipe wipe ọja wa n jona ti mo si yara jade wa si ọja. Ọpọlọpọ kudia ati ohun ini lo ti ṣegbe ninu ibugbamu ina to ṣẹlẹ ni ọja Binukonu ""Nigbati iṣẹlẹ ina yi waye lẹẹmeji sẹyin, a ṣe gbogbo ohun ti ijọba paṣẹ fun wa lati ṣe. ""Nigbati iṣẹlẹ ina yi waye ni igba akọkọ, ijọba ṣe iranlọwọ fun wa lati tun awọn ile itaja wa kọ fun wa laigbowo. Won so pe ina mọnamọna ijọba lo ṣe okunfa ijamba ina naa ""Mo gbọ pe ina mọnamọna lo fa ijamba yi, mo ti kìlọ fun gbogbo awọn ọlọja lati ma pa awọn ina ninu ṣọọbu wọn ti wọn ba ti taja tan ki wọn too lọ si ile wọn. ""A maa nrii daju pe a pa gbogbo awọn ina mọnamọna ni oja ki a too lọ."" Akọwe ọja naa, ọgbẹni Gbenga Fayemi sọ pe awọn oludari ọja naa ti ṣe ipese awsn ohun idaabo bo awọn ọja nibẹ lati igba ti iṣẹlẹ ina ti waye nigbakan ri. Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si:",0,yoruba "RT @user: Amin edumare """"""""""""""""@user: @user odun de,odun olowo,odun olomo, Edumare je ki asopo re oo.*singing in yoruba*",0,yoruba Àìṣòdodo. Ìmọtaraẹninìkan. Àìnífẹ̀ẹ́ ara ẹni t'ó ju ti tẹ́lẹ̀. Ọ̀gá ló kọ́ wa bẹ́ẹ̀,0,yoruba "Lagos/Ibadan Expressway: Ọpọ̀ èrò ló farapa tí mọ́tò ṣòfò Eeyan mejila si farapa. Ajọ ẹsọ alabo oju popo lo sọ eyi di mimọ fun BBC Yoruba ninu ifọrọwero pẹlu olori ẹka wọn ni ipinlẹ Ogun,Clement Oladele. Oladele salaye pe ere asapajude lo ṣokunfa iṣẹlẹ yi ti ọkọ meje si farakasa ijamba naa. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Saaju ni awọn ti ọrọ naa soju wọn kan ti ni o to eeyan mẹẹdogun ti o ku ninu iṣẹlẹ yi. Ijamba ọkọ naa la gbọ wi pe akọkọ rẹ ṣẹlẹ ni nnkan bi ago meje ọjọru ti awọn miran si tun ṣelẹ lowurọ ọjọbọ. Lagbegbe kan ti wọn n pe ni Danko saaju ki a to de Sagamu ni o ti waye. Isẹlẹ naa ti da sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ silẹ ti awọn ẹsọ ajọ oju popo si n gbiyanju lati dari lilọ bibọ ọkọ. Lagbegbe kan ti wọn n pe ni Danko saaju ki a to de Sagamu ni o ti waye. Akọroyin BBC Yoruba, Olu Alebiosu ti oun naa n rin loju ọna naa jabọ pe awọn ti ọrọ naa soju wọn sọ pe ọkọ nla kan to ya si ibi ti ko yẹ lo mu ki ijamba naa sẹlẹ. Gẹgẹ bi ohun ti o sọ, O ni awọn alafojuri nibi iṣẹlẹ naa bi ọkọ naa ṣe ya lojiji lo mu ki awọn miran to n bọ lẹyin rẹ fori sọ ara wọn. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ninu awọn ọkọ to farakasa la ti ri ọkọ akero kan to fi mọ awọn ọkọ ayọkẹlẹ miran. A ko ti ri aridaju lati ọdọ awọn ajọ to n risi iṣẹlẹ pajawiri lori iye eeyan to ku ṣugbọn awọn to wa nibẹ ni ko le kere ju mẹẹdogun lọ Ijamba ọkọ naa da sunkẹrẹ fakẹrẹ silẹ loju ọna naa Akọroyin wa jabọ pe nisoju oun, awọn ẹsọ abo oju popo n fi ọkọ alaarẹ gbe awọn eeyan kan to farapa lọ si ile iwosan. Ni kete ti a ba ti ni iroyin miran nipa iṣẹlẹ yi ni a o fi too yin leti. 9th Assembly: Aráàlú ní àwọn ń fẹ́ ìpèsè àwọn ohun èèlò amáyédẹrùn",0,yoruba "èrò àti àsà tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba Àyájọ́ ìfẹ́ ti tún ré kọjá l'ọ́dúnnìí. Àmọ́ má jẹ́ kí ìfẹ́ tán láàrin wa nígbà kankan Ọlọ́run wa.,0,yoruba Ǹjẹ́ ìwọ́ mọ̀ wípé orúkọ ìdílé eléégún ni Amúṣàn-án? Ìtúmọ̀ ni: ẹni t'ó mú ẹgba; àtòrì; ọrẹ́; pàṣán lọ́wọ́. #Yoruba #Egungun #Amusanan https://t.co/mktg4Cf6DO,0,yoruba "RT @user: Eledumare yio ko wa yo l'owo ekun omi o""""""""""""""""@user: Mó kí gbogbo yín o, ọmọ Oòduà gbogbo. Níbikíbi tí ẹ bá wà. Ẹkú b ...",0,yoruba "Australia lu D'Tigers ni 97-55 Ẹgbẹ D'Tigers fidi rẹmi ninu idije mẹta ti wọn ni ninu isọri kinni (Pool A) lai fakọyọ rara ninu wọn. Eyi tumọsi wipe wọn yoo ṣanwọ pada wale lati ibi idije Gold Coast ni ọdun 2018. Awọn ẹlẹgbẹ wọn lati orilẹede Australia san bantẹ iya fun wọn pẹlu ami ayo mẹ́tàdínlọ́gọ́rùn ún si márùndínlọ́gọ́ta (97-55) ninu idije naa lati fi opin si irinajo D'Tigers. Canada gbo ewuro si D'Tigers loju pẹlu 82-67 Bi o tilẹ jẹ wipe arakunrin ọmọ orilẹede Naijiria Ikechukwu Diogu gbiyanju ti o si jẹ ami ti o pọju lọ ninu idije naa pẹlu ami mọkandinlogun (19), ṣugbọn ẹpa ko boro mo fun ẹgbẹ D'Tigers. Wọn padanu idije akọkọ wọn pẹlu ami àádọ́fà si márùndínláàdọ́rin (110-65), lẹyin na ni orilẹede Canada gbo ewuro si wọn loju pẹlu ami méjílélọ́gọ́rin si mẹ́tàdínláàdọ́rin (82-67). Àwọn iròyin tì ẹ leè nífẹ̀ síí:",0,yoruba "Jìjìn ọ̀pọ́lọ̀ ni ìbàdandun àtọ́wọ́dá, àwọn oníṣẹ́ ìṣẹ́ ni ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa aráyé: ti o nuni ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ẹkọ́: ti o jare.",0,yoruba "Ki lo le mu ki agbabọọlu sọ fun akọnimọọgba pe ẹnu rẹ n run? Gbajugbaja agbabọọlu Barcelona to jẹ ọmọ Argentina lo sọ fun akọnimọọgba Brazil, Tite pe ko yee sọrọ mọ ninu ifẹsẹwọnsẹ ọlọrẹẹsọrẹẹ to waye laarin orilẹ-ede mejeeji lorilẹ-ede Saudi Arabia lọjọ Ẹti. Messi ati Tite tahun si ara wọn nigba ti ere bọọlu naa si n gbona girigiri, bo tilẹ jẹ pe Messi naa lo gba goolu kan ti ẹgbẹ agbabọọlu Argentina fi bori sawọn. End of Twitter post, 1 Messi kan ṣadeede lọ sẹgbẹ kan lori papa nibi ti Tite wa, nibẹ lo ti fi ika sẹnu to si ni ''fẹẹmu'' fun akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu Brazil. Tite fun ra rẹ ṣalaye pe lootọọ loun ti n ṣaroye fun rẹfiiri pe nipa bi ifẹsẹwọnsẹ ṣe n lọ, ati pe oun ati Messi jọ ni gbolohun asọ nigba ti ipele akọkọ ere bọọlu pari. Akọnimọọgba Brazil ni o yẹ ki Messi gba kaadi ikilọ yẹlo, lẹyin naa lọ sọ pe ki oun gbẹnu dakẹ, bayii loun sọ fun un pe ko dakẹ ẹnu rẹ. Ninu ọrọ tiẹ, balogun ẹgbẹ agbabọọlu Brazil, Thiago Silva bu ẹnu ẹtẹ lu ihuwasi Messi si Tite. O ni iwa ti ko boju mu ni lati sọ pe ki agbalagba gbẹnu dakẹ. Silva fikun ọrọ rẹ pe alaṣeju ni Messi, oun nikan lo fẹ fọn feere, o fẹ dari ere bọọlu naa, bakan naa lo n ṣe ariyanjiyan pẹlu rẹfiri.",0,yoruba "Àìmọ́ ni ó pa Alàji lo ìgbà ọkọ. ìgbà àkerekere. Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "Miliọnu kan abọ awọn akẹkọọ to pegede ninu idanwo naa Ajọ naa sọ eyi di mimọ nilu Eko. Ajọ naa ti wa rọ awọn akẹkọọ to joko ṣe idanwo naa lati bẹrẹ si nii lọ wo ori ayelujara fun esi wọn. Nnkan bii miliọnu kan abọ o le diẹ lawọn akẹkọọ to joko ṣe idanwo naa lọdun yii eyi to pọ ju ti esi lọ. Kayeefi: Facebook ni Wolii Arole Jesu fi tàn an wọ agbo, orí rẹ̀ ni wọ́n fi s'owó Gẹgẹ bi ajọ WAEC ṣe sọ ọ, ida mejilelọgọrin ni awọn akẹkọọ to gba ami o kare, iyẹn credit ni awọn iṣẹ ọpọlọ marun un tabi ju bẹẹ lọ. Eyi fẹrẹ to ilọpo meji awọn to ni iye ami yii ninu idanwo ọdun 2018, eleyi to jẹ ida aadọta o din diẹ, 49.98%. Ibadan Accident: Èèyàn méjì kú, ẹnìkan wà nílé ìwòsàn",0,yoruba "Ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress yoo ṣepade ni oni ọjọ Aiku lati jiroro lori ọjọ pato ti wọn yoo ṣe ipade apero gbogbo gbo eyi ti yoo ṣaaju idibo abẹle wọn. Eyi waye ni idahun si iru ikilọ ti aarẹ Naijiria, Muhammadu Buhari fi sita ninu ifọrọwerọ to ṣe pẹlu ileeṣẹ amohunmaworan NTA l'Ọjọbọ ọsẹ nibi to ti ni ki wọn tete wa wọrọkọ fi ṣe ada ki ituka ma baa ṣẹlẹ ninu ẹgbẹ wọn. Ninu ifọrọwerọ naa ni Aarẹ Buhari ti ni bi wọn ṣe da oni da ọla ti wọn n fi nkan falẹ, ẹgbẹ APC kan n fi ara wọn si eti bebe ijakulẹ ni lọwọ ẹgbẹ oṣelu alatako wọ, Peoples Democratic Party ninu idibo ọdun 2023. Kìí ṣe ohun tí ojú kò rí rí tí ìyàwó mi bá ní owó jù mí lọ - Kolawole Ajeyemi Wo obìnrin tó ṣe ìgbéyàwó pẹ̀lú àwọ̀ ""Pink"" Bobrisky tọrọ àforíjì lọ́wọ Ọba Benin lẹ́yìn tó ní kó wá fẹ̀ òun Nigba ti alaga ẹgbẹ awọn gomina iha Ariwa naa ṣepade pẹlu Aarẹ Buhari lọjọ Ẹti, Simon Lalong ni koko ohun ti awọn yoo maa ṣepade le lori lọjọ Aiku ni yiyan ọjọ ti ipade apero nla ẹgbẹ naa yoo waye. Ni bayii, gbogbo awọn gomina APC ti ṣetan fun ipade oni lati yan ọjọ ti wọn yoo ṣe e. Gẹgẹ bo ṣe sọ, Aarẹ Buhari ti ni onyẹ kankank ko ni yẹ wiwaye ipade apero wọn ninu oṣu keji ọdun yii. BAkan naa lo tọka sii pe ikilọ aarẹ Buhari pe ki wọn to ile wọn jẹ ohun to yẹ ki awọn ẹgbẹ mu lọkunkundun.",0,yoruba ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa òkè: ti o tẹ.,0,yoruba nítesíwájú ìwádìí fi hàn wípé ọsàn àgbálùmọ́ ní agbára láti wo àrùn ọkàn,0,yoruba Baàlè joko. A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba "Ọdẹ mú ìyàwó wọlé, wọ́n jọ ń gbé bíi t'ọkọ taya pẹ̀lú ìyálé ẹ̀. #EfonAtiOde",0,yoruba "o jare. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Bàbá lo ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba ẹ kú gbogbo ẹ̀ ṣé gbogbo nkan ń lọ déédé,0,yoruba nípa ìròyìn tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ài: ti o ní wúlò.,0,yoruba Ṣí fèrèsé ìtàn,0,yoruba òdégbódégbó òyijùyijù ni à ń ki ọdẹ àwọn wo ni a máa ń kì ní ọ̀sàlàǹsòlò òsòlòǹsala,0,yoruba "tó kún jú, àwọn ènìyàn ni ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò.",0,yoruba Iṣọ́ẹ̀ ìṣẹ́ ni a ní nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba "RT @user: Ogo ni fun Olorun ni oke orun. RT""""""""""""""""""""""""""""""""@user: Mo ṣọpẹ́ fún Ọlọ́run. Ọba tó fẹ́ mi tó dá mi tó gbà mí là.""""""""""""""""""""""""""""""""",0,yoruba "RT @user: Ibaje le oro lori ibunkun owo pelu omo""""""""""""""""@user: Òjò ìbùkún ló ń rọ̀ yìí o.""""""""""""""""",0,yoruba ri pe nilo ayẹwo wey ti o nuni ti o nuni ti o lẹ.,0,yoruba "Àwọn ọlọ́pàá kìí jáfara láti dá àlàáfíà padà sáwọn ágbègbè tí wàhálà bá ti ń wáyé A gbọ́ pé ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣẹlẹ̀ lẹ́yìn ìpàdé òṣèlú kan tó wáyé láàárín igun óṣèlú méjì kan lágbègbè náà. Aago márùń ààbọ̀ ìrọ̀lẹ́ lọ́jọ́ àìkú ni ìsẹ̀lẹ̀ náà wáyé ní agbègbè Òkè-Sopen, tó sì sún wọ ìdàjí ọjọ́ ajé, èyí tó tún tàn wọ àwọn àdúgbò míì bíi Òkè Àgbò àti Ojowo. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn èèyàn tí ìṣẹ̀lẹ̀ náà sojú wọn ní ààrin àwọn ọmọ ẹgbẹ́ OPC kan àti ẹgbẹ́ òkùnkùn Aiyé ni rògbòdìyàn náà ti kọ́kọ́ bẹ̀rẹ̀, kí àwọn ọlọ́pàá tó dá síi, tí ẹ̀mí ọmọ ẹgbẹ OPC kan sì bọ́. Àlàáfíà ti ń padà jọba lágbègbè náà Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ogun ni awọn ti ko ikọ Olopaa kogberegbe lọ si agbegbe naa lati lọ wawọ́ ọ rogbodiyan naa bọlẹ. Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa, DSP Abimbọla Oyeyẹmi ni gbogbo awọn ti aje rogbodiyan naa ba ṣi mọ lori ni yoo fi oju wina ofin. Wàyí ò, iléesẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Ògùn ti ń ri dájú pé àlàáfíà ti ń padà jọba lágbègbè náà.",0,yoruba "Ipinlẹ Kano wa lara awọn ipinlẹ to wa lara awọn ipinlẹ to ni ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ ni ipinlẹ naa. Gomina Makinde sọ eyi lasiko ti wọn n se ibura wọle fun awọn aṣofin ipinlẹ ti wọn dibo yan si Ile Igbimọ aṣofin ipinlẹ naa. Iba Gani Adams: Bẹ́ẹ gbé màláíkà kan lọ sí Aso Rock, kò lè ṣàṣeyọrí O ni ijọba oun ṣe tan lati gbogun ti iwa ibajẹ, nitorina ni awọn yoo ṣe rii daju wi pe awọn gbe abadofin jade ti yoo se ifilọlẹ ile-iṣẹ ijọba ipinlẹ ti yoo maa gbogun ti iwa ibajẹ. Agbẹnusọ fun gomina naa, Taiwo Adisa fi kun un wi pe gomina Makinde ṣe tan lati jẹjọ ti ajọ naa ba ri i wi pe oun ru ofin iwa ibajẹ. Awọn iroyin miran ti ẹ le nifẹ sii:",0,yoruba yi kún fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba "@user ló ń bọ́ lọ́wọ́, ọ̀rọ̀ nípa bí a ṣe ń ta ara ẹni láyé ayélujára ló ń sọ #SMWCONTENT @user http://t.co/bIwgfdd9nI",0,yoruba tún ṣe àwọn iṣẹ́ tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa òkè: ti o ní wúlò fún gbogbo.,0,yoruba ahọ́n àteyín ńjà bẹ́ni méjì bá fìjà pẹ́ta kí ọ̀kan tutọ́ sókè fojú gbàá kí ẹnìkejì léríléka ó ní bí a ṣe ń yanjúu rẹ̀,0,yoruba Tọ̀sán tọ̀sán ní ńpọ́n ìtalẹ̀ lójú; bílẹ̀-ẹ́ bá ṣú yó di olóńjẹ. #EsinOro🐎 #Yoruba,0,yoruba ẹ kú ojúmọ́ bàbá wa,0,yoruba òròkí ṣe ẹ wàpá,0,yoruba "Gunnar Solskjaer ti jáwé olúborí ìfẹsẹ́wọnsẹ̀ eré bọ́ọ̀lù márìnlá nínú mọ́kàndínlógún láti ìgbà tí ó ti jẹ́ adelé fún osù mẹ́rin. Ole Gunnar Solskjaer ti ti jawe olubori ifẹsẹwọnsẹ ere bọọlu mẹrinla ninu mọkandinlogun lati igba ti o ti jẹ adele fun osu mẹrin. Osu Kejila, ọdun to kọja ni ọmọ ọdun mẹrindinlaadọta naa pada wa si Man United lati gba isẹ lọwọ Jose Mourinho gẹgẹ bi akọnimọọgba. Manchester United wa ni ipo kẹrin bayii ninu idije Premier League, ti wọn yoo si ma a koju Barcelona ni ifẹsẹwọnsẹ keji to kangun si asekagba idije UEFA Champions League, lẹyin ti wọn fagba han PSG pẹlu ayo meji ni Paris. Bakan naa ni Ole Gunnar Solskjaer ni atilẹyin awọn agbabọọlu Man United tẹlẹri, ati awọn to wa nibẹ lọwọlọwọ. Ti a ko ba gbagbe, saa mọkanla ni Ole Gunnar Solskjaer fi jẹ agbabọọlu Manchester United to si jẹ ẹni to gba bọọlu wọnu awọn ni ọdun 1999 ti wọn fi gba ami ẹyẹ Champions League ti ọdun naa.",0,yoruba ẹ mà kú ọjọ́àìkú o àìkú tí í ṣe baálẹ̀ ọrọ̀,0,yoruba "Elẹ́dẹ̀ náà sọtẹ́lẹ̀ pé Nigeria, Belgium, Uruguay ati Argentina yóò kópa ní ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ tó kángun sí àsekágbá Ife Ẹ̀yẹ Agbaye Russia 2018. Ẹlẹdẹ aramanda naa ti wọn pe orukọ rẹ ni, Mystic Marcus ni ilu Heage ni Ilẹ Gẹsi ni Nigeria pẹlu Belgium, Uruguay ati Argentina ni awọn agbabọọlu orilẹede ti yoo kopa nibi ifẹsẹwọnsẹ to kangun si asekagba naa. Olootu ẹlẹde naa, Juliette Stevens sọ wi pe asọtẹlẹ ẹlẹdẹ naa daju nitori igba akọkọ kọ ni yiI ti ẹẹdẹ naa yoo sọ asọtẹlẹ ti yoo si wa si imusẹ. Russia 2018:Super Eagles ti kẹ́kọ̀ọ́ nínú ìdíje tó kọjá O ni ẹlẹdẹ naa to jẹ ọmọ ọdun mẹjọ sọ asọtẹlẹ wi pe Donald Trump yoo di Aarẹ Ilẹ Amẹrika, ati wi pe Ilẹ Gẹẹsi yoo kuro ni Ajọ Europe.",0,yoruba àkààèèbó ni o èyí tí wọ́n rọra fi awẹ́ ọ̀gẹ̀dẹ̀ kan dé fìlà fún,0,yoruba Femi Fani-Kayode: Wákàtí mẹ́fà ààbọ̀ ni EFCC fi gbà mí ní àlejò pẹ̀lú àpọ́nlé àti ìjáfáfá,0,yoruba "Bata to n ro lakọlakọ to fẹ ya ni ọ̀rọ̀ ìjọba Buhari- Tunde Bakare Ọ̀jẹ̀lú ló bá wa dé ibi ni Naijiria ti kii ṣe iṣelu rara- Pasito Tunde Bakare. O ni: Awọn oloṣelu Naijiria ti gbe pẹpẹ lọ kii ṣe pe wọn n jẹ ni idii pẹpẹ nikan. Tunde Bakare to jẹ ogbontarigi ojiṣẹ Olorun to n dari ijọ Citadel Global Community Church gba BBC Yoruba lalejo. O salaye kikun nipa iṣelu Naijiria lati ọdun 1999. Bakare ni: Mi o ranti boya a ni kọkọrọ ti a fi n tilẹkun nile baba mi. O mẹnuba ipileṣẹ nibi ti ẹru Naijiria ti wọ wa. O ni: Bi ologun ko ba ba ilu jẹ, wọn kii kuro nibẹ, wọn maa n ṣọ ara wọn di 'Ecomog' ni. Nibi ifọrọwerọ pẹlu BBC Yoruba, Pasitọ Tunde Bakare ni iyan Naijiria ti di atungun nitori pe ibeere to yẹ ka maa beere ni pe lati ọdun 1999 n kọ? Se ko tii yẹ ki iyipada wa laye olugbe Naijiria ni? Pasito Tunde Bakare ṣalye fun BBC pe iran ni oun ri ki oun to bẹrẹ iṣelu ati ayipada ni Naijiria lo jẹ oun logun. Lori ọrọ Buhari: Bakan naa lo mẹnuba irinajo rẹ pẹlu aarẹ Buhari, bi wọn ṣe pade ati ọrọ oselu awon mejeeji. O ni titi di isinyi ni oun n ba Buhari sọrọ ṣugbọn o kan maa n gbọ ni, kii gba a wọle. Bakare ni kaka ko san lara ọmọ iya Ajẹ Buhari ni, niṣe nijọba rẹ n fi gbogbo ọmọ bi obinrin ti gbogbo nkan n dojuru Bakare ni ọpọ ọrẹ oun lo n fi Buhari bu oun. O ni Adura lo ku lori ọrọ Naijiria ati pe oun ko ni salọ sibi kankan nitori o ṣi maa dun. Bakare ni koda, oun ati awọn ọmọ oun maa n tọwọ bọwe ni lori pe wọn gbọdọ pada wa si Naijira lẹyin ẹkọ wọn loke okun. Lori ọrọ Sunday Igboho: Tunde Bakare sọrọ lori ọrọ Sunday Igboho pe nitori nkan fi sibi kan ju ibi kan lọ ni awọn ọdọ Yoruba ṣe n gbarata. O ni ti o ba kari, ko sẹni to maa ja. O ni ti igba ba yipada ko ni si wahala ni ẹkun kankan mọ",0,yoruba "Oyedepo ni ọdun yii ko ni lọ lai jẹ pe Ọlọrun bẹ awọn eeyan to n gbẹmi awọn ọmọ orilẹ-ede yii wo Oyedepo kede ọrọ yii lasiko iwaasu to se nibi isin ọjọ isinmi to waye ninu olu ijọ Winners to wa ni Ọta, nipinlẹ Ogun. Gẹgẹ bo ti wi, ọdun yii ko ni lọ lai jẹ pe Ọlọrun bẹ awọn eeyan to n gbẹmi awọn ọmọ orilẹ-ede yii wo, to fi mọ awọn eeyan to n se atilẹyin fun wọn, tabi awọn to n saanu fun awọn apaniyan. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọrẹ Falọmọ: Buhari yóò rí ìbò Yorùbá gbà ju Atiku, Ọbasanjọ lọ Nigba to n gbarata lori isẹlẹ ipaniyan to waye ni ipinlẹ Benue laipẹ yii, nibi ti ọpọ ẹmi awọn araalu ti bọ, olori ijọ Winners lagbaye ni, o dabi ẹni pe ẹmi eeyan ko tiẹ wa jọ awọn apaniyan yii loju mọ, ti wọn ko si bikita mọ rara lati da ẹmi awọn eeyan legbodo. ""Emi ko ri iru isẹlẹ ipaniyan bi eyi ri, ti awọn eeyan n sare kiri, ti ọpọ wọn si n subu lulẹ, ti wọn n ku. O si yẹ ko ye wa pe gbogbo ẹmi lo jẹ ti Ọlọrun, to fi mọ ẹmi awn ẹranko, ti Ọlọrun si ti setan lati gba ẹsan lara ẹnikẹni to ba da ẹmi alaisẹ legbodo, ki ọdun yii to pari."" Oyedepo, ẹni ti iwaasu rẹ kun fun ire fawọn olujọsin rẹ, ati egun lori awọn ẹni apaniyan ni Naijiria, tun gegun pe ẹnikẹni to ba ni oun yoo pa eniyan ko to de ipo oselu, ko ni de ori ipo naa laelae. Oyedepo ni o dabi ẹni pe ẹmi eeyan ko tiẹ wa jọ awọn apaniyan yii loju mọ, ti wọn ko si bikita mọ rara lati da ẹmi awọn eeyan legbodo. Nigba to n tako iroyin kan to ni o n gba owo lọwọ awọn oloselu, Oyedepo ni oun ko gba kọbọ ri lọwọ oludije kankan ko to de ipo, ti oun ko si setan lati gba owo lọwọ oloselu kankan. O fikun pe alaafia orilẹ-ede yii lo jẹ oun logun, eyi ti oun n tiraka fun ni gbogbo igba, bẹẹ si ni wolii Ọlọrun alaaye ni oun bi o tilẹ pe awọn woli eke wa, to fara jọ woli Ọlọrun. Oyedepo tun rọ ojo epe sori awọn eeyan to n ti awọn apaniyan lẹyin pe, egun ati ibi to n bẹ lori awọn apaniyan naa ni yoo jẹ ipin tiwọn naa. Oyedepo ni oun ko gba kọbọ ri lọwọ oludije kankan ko to de ipo, ti oun ko si setan lati gba owo lọwọ oloselu kankan. ""O da mi loju pe awọn alasẹ Naijiria ko lee sọ pe awọn ko ti awọn apaniyan lẹyin nitori gbogbo awọn eeyan tawọn agbofinro mu pe wọn n pa eniyan, ni ijọba ti tu silẹ patapata."" ""Bawo ni wọn se lee maa gba ẹmi awọn ọmọ ilẹ yii ni gbogbo igba, ti a ko si tii ri ẹnikẹni mu lati fi jofin. Koda, ẹni tawọn agbofinro mu pe o pa iyawo oniwaasu kan ni ijọ Deeper Life, lo ti gba idande kuro lahamọ, ti wọn si tun dana sun ọpọ sọọsi lorilẹ-ede yii."" Oyedepo wa leri leka pe, laipẹ ni oun yoo kede iye sọọsi ti wọn ti sọ ina si ni orilẹ-ede yii. Ìkọlù àwọn Fulani Darandaran ti mún ọ̀ps ẹ̀mí lọ Bakan naa, Olori ijọ Living Faith, ti wọn n pe ni Winners Chapel, Bisọọ́bu David Oyedepo ti kepe Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari, lati kọwe fipo silẹ lori ọrọ awọn Fulani darandaran ti wọn n fẹmi awọn eeyan ṣofo. Bisọbu Oyedepo lo jẹ ojiṣẹ Ọlọrun kẹta, ti yoo rọ Aarẹ Buhari lati kọwe fipo silẹ lẹyin ti bisọọbu agba fun Ijọ Aguda l'Abuja, John Cardinal Onaiyekan, ati akẹẹgbẹ rẹ tẹlẹ nipinlẹ Eko, Cardinal Anthony Olubunmi Okogi, sọ fun Aarẹ Buhari lati fipo silẹ lẹyin to kuna lati daabo bo awọn ọmọ Naijiria. Oyedepo sọ pe fifi ẹmi awọn alaiṣẹ Kristẹni ṣofo, papa julọ laarin gbungbun orilẹede Naijiria ti to gẹẹ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: O fi kun ọrọ rẹ pe, kin lode ti awọn Fulani darandaran fi n kọlu awujọ awọn ọmọlẹyin Kristi nikan, ti ọwọ sinkin ofin ko si mu wọn. Ojiṣẹ Ọlọrun naa woye pe, awọn alaṣẹ ijọba lo n tiwọn lẹyin, bibẹẹkọ wọn o ba ti dẹkun ipaniyan.",0,yoruba ìbàdandun ìlú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba ó dárúkọ bọ́lá ìgè àti ọ̀jọ̀gbọ́n wọlé ṣóyínká àwọn wọ̀nyí gbà pé lílo èdè fi kọ́ ọmọ lẹ́kọ̀ọ́ ló dáa jù,0,yoruba "Alex Iwobi darapọ̀ mọ́ ikọ̀ Arsenal nígbà tí ó wà ní ọmọ ọdún mẹ́san Iwobi tọwọ bọ iwe adehun ti yoo pari ni ọdun 2023 pẹlu ẹgbẹ agbabọọlu naa. End of Twitter post, 1 Iwobi to jẹ ọmọ ọdun mejilelogun ti gbayo mẹsan wọle fun Arsenal ninu ifẹsẹwọnsẹ 98 to ko pa ninu rẹ lati ọdun 2015 to ti bẹrẹ si ṣoju ikọ naa. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Lati ọmọ ọdun mẹsan ni Iwobi ti darapọ mọ Arsenal, o ṣoju ikọ naa fun igba akọkọ nigba ti o pe ọmọ ọdun mọkandinlogun. Iwobi dupẹ lọwọ akọnimọọgba tuntun ikọ naa Unai Emery fun igbagbọ rẹ ninu oun, bẹẹni ko gbagbe awọn ololufẹ Arsenal fun atilẹyin wọn.",0,yoruba "Yoruba Nation: Ẹgbẹ́ Ilana Omo Oodua ní arúmọjẹ ló pilẹ̀ ìwé òfin 1999, INEC kò gbọdọ̀ lò ó fún ìbò Ekiti, Osun",0,yoruba rere lojiji. Ọba lo ni àṣà yorubá eyti o gbe lori ọ̀run dídì.,0,yoruba wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o nuni ti o nuni ti o nuni ti o nuni ti o ní wúlò.,0,yoruba "wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìṣẹ́ ọ̀pọ́lọ̀.",0,yoruba tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa òkè: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ àti ìbi tí wọn wà.,0,yoruba "RT @user: """"""""""""""""@user @user Akorin Dekunle Fuji di olugbebi ni ilu America >> http://t.co/vqPkAFLIOQ http://t.co/p9jGup…",0,yoruba "àkokò, Olùwo ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..",0,yoruba "nípa aráyé: ti o nuni ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba rántí wípé ẹní bá fẹ́ jẹ oyin inú àpáta ò gbọdọ̀ wo ẹnu àáké ìwọ ṣá ma ṣe ohun o mọ̀ ọ́ ṣe lọ ire ń bọ̀ níkòpẹ́,0,yoruba "àkokò, Alàji lo ni àṣà yorubá eyti o gbe lori.",0,yoruba Ẹ jẹ́ ká ṣe ohun tí a máa ń ṣe lọ́jọ́ Ọjọ́ru #Ibeere #Yoruba,0,yoruba ẹkọ́ ṣẹlẹ ni Lagos ti gbogbo eniyan sọ o dara. (1999),0,yoruba "tí Bàbá fè se, Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba èdùà má finá ọmọ jó wa,0,yoruba Àwọn olólùfẹ́ẹ Soca kò le è béèrè ju bẹ́hẹ̀ lọ .,0,yoruba "nípa ìbadandun. Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Adajo paṣẹ bakannaa pe ki wọn lọ fi si ahamọ titi di igba ti wọn yoo fi gbẹjọ rẹ. Ọjọ ẹti tii ṣe ọjọ karun un ọsu Kẹrin ni ẹka ọtẹlmuye ọlọpaa to wa ni Panti nilu Eko gbe Inspẹkitọ Ogunyẹmi Olalekan lọ si iwaju adajọ. Ninu atẹjade kan ti alukoro ile iṣẹ ọlọpaa nilu Eko,Bala Elkana fi sọwọ sawọn akọrọyin o salaye pe Adajọ ile ẹjọ kekere to wa ni Ebute Meta,Adajọ A.O Salawu paṣẹ ki wọn fi si ahamọ titi diigba ti Oludari eka olupejo labe ijoba nipinle naa yoo fi lawọn lọyẹ lori ẹjọ naa. Ile ise ọlọpaa ti saaju gba asọ lọrun inspektọ Ogunyẹmi Olalekan lori ipa to ko ninu iyinbọn pa Kolade Johnson. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Okùnrin SARS náà sọ pé òun máa pa èèyàn síbi ni- Aladugbo SARS ti bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ láti yọ àwọn ọ̀bàyéjẹ́ kúro",0,yoruba 4. ⚽️ = bọ́ọ̀lù aláfẹsẹ̀gbá 🏀= bọ́ọ̀lù aláfọwọ́jùsápẹ̀rẹ̀ajádìí 🎾= ẹyin oríi kọnkéré 🏓= #Ibeere #Yoruba #EreIdaraya,0,yoruba "àṣà ni ìwájú lojiji. Ìyá lo tun se joko. Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba jẹ́ ilẹ̀ agbègbè tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba ninu telifisoni leti yaaa o eleyi ko bojumu to sewon ko fun yin laye lati wole ni,0,yoruba "nìkan. Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba ni ìwé orisirisi lo je gbogbo ise ibile tèmi.,0,yoruba lẹ ìkòkò wey ti o nuni ti o dara.,0,yoruba ọ̀rọ̀ náà ń sọ pé obìrin aya ọkùnrin ti wà nílé náà kò sí ohun kan ìyàwóilé pẹ̀lú àlè ìta torípé obìrin ilé ló lọkọ,0,yoruba can one answer in englishọmọ yorùbá you are so speak yorùbá sọ ọ́ lédèe yorùbá rótìmí,0,yoruba mi pe kan lonimo si fe dupe lowo eshe o,0,yoruba "ASUU ṣalaye pe o di igba ti ijọba apapọ ba mu adehun to baa ṣe ṣẹ ki awọn to pada si ẹnu iṣẹ O ti n reti lati di akẹkọọ gboye tuntun ko si bẹrẹ ikọṣẹ ti yoo maa gba owo ni ile iṣẹ iroyin kan. Ṣugbọn dipo ki inu rẹ dun, inu akẹkọọ nipa imọ iroyin yii ko dun si iyanṣẹlodi ẹgbẹ awọn olukọni fasiti(ASUU) to n lọ lọwọ. Awọn akẹkọọ fasiti to ṣe pe ijọba ipinlẹ lo n seto isuna wọn ko tii wọle ẹkọ pada nitori iyanṣẹlodi ẹgbẹ ASUU eyi to jale jako gbogbo orilẹede. Ẹgbẹ naa fi ẹsun kan ijọba pe o kuna lati ṣe ohun ti wọn jọ fẹnu ko si latẹyin wa lori idagbasoke awọn ile ẹkọ giga. Ajọ awọn oṣiṣẹ olukọ ile ẹkọ giga Bakan naa, wọn ja fun ṣiṣe atunṣe awọn ohun elo to ti bajẹ, aito owona àti ẹsun pe wọn fẹ fi kun owo ile iwe. Ẹgbẹ ASUU pẹlu ijọba apapọ ṣepade lọjọ aje nibi ti minisita fun ọ̀rọ̀ oṣiṣẹ, Chris Ngige sọ wi pe igun mejeeji ti fi adehun sọ̀kan. Pe, ijọba ti ṣe tan lati pese 15.5bn ($42m, £33m) fun awọn fasiti ti ijọba. Aarẹ ẹgbẹ ASUU, Biodun Ogunyemi ni ohun aaṣe ṣi ku ki ẹgb to gba ati pe iyanṣlodi ko tii pari. ""O n mu irẹwẹsi ba ọkan, ni arabinrin Tejuoso wi, gẹgẹ bi akẹkọọ ipele to gbẹyin, mi o le rinrinajo kan to ṣe san an, mi o le ṣiṣẹ gidi tori a o mọ igba ti a o wọle pada. ""A o mọ ohun ti yoo ṣẹlẹ, nitori idibo ti sunmọ, wiwọle ninu oṣu keji, bakan meji ni. A o tilẹ mọ bi ọjọ waju ṣe ri fun wa. Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ kan dunnú, àwọn míràn fajúro si iyansẹlodi Asuu Ẹwẹ, adari ẹgbẹ, Ọjọgbọn Oguyemi ti oun funra r ni ọm meji nile iwe giga fasiti ni iyanṣlodi naa wa lati da abo bo ile iwe naa ati ọjọ́ iwaju awọ̀n ọmọ wọn. ""A ti maa n sọ fun awọn akẹkọọ atawọn obi wọn pe tori wọn naa la ṣe n ṣe eyi."" ni Ọjọgbọ Ogunyemi sọ. A fẹ ki wọn gba iwee ẹri to ko ni niyii. Ijọba naa ti gbe ọpọlọpọ owo silẹ lati san owo ti wọn n jẹ awọn olukọ. O fẹrẹ jẹ pe ọdọọdun ni ASSU n gunle iyanṣẹlodi. ọ̀dọ́ ni agbara orilẹ-ede nibi ti eto ẹkọ ti ṣe koko Ohun to ku ni lati ati ri adari lere ti yoo mọ riri eto ẹkọ si idagbasoke ọlọdani ninu orilẹede. Lasiko idibo yii, ẹni to ba fẹ polongo ibo, ẹka yii lo yẹ ko wa. Lati igba ti iyanṣẹlodi ti bẹrẹ, owo ori ẹrọ ayelujara lo n ṣe eyi to si wọpọ laarin awọn ọmọ. Bakan naa, ọkan pataki lara awọn owo ori rọayelujara, Jobberman jẹ iṣẹ ọeọ awọn akẹkọọ kan nigba iyanṣẹlodi ASUU lọdun 2009. Bi o tilẹ jẹ pe omidan Agu Uka n gbadun owo rẹ, o ni idamu nipa bi akoko iyanṣẹlodi naa ṣe n pa ẹkọ rẹ lara. Nigba ti awọn akẹkọọ bii arabinrin Tejuoso ni ireti pe abajade ifọrọwerọ ijọba ati ASUU yoo ṣọmọ ire, bẹẹ naa ni ibanilọkan jẹ n wa pe bi wn ko ba wa wọrọk fi ṣada, iyanṣẹlodi yoo di baraku ninu igbe aye awọn akẹkọọ Naijiria.",0,yoruba ènìyàn a yi yi ti o ní wúlò.,0,yoruba Ǹjẹ́ ìran #Itsekiri bá Yorùbá tan? Ìbátan ni Ìbíní àti Ìtṣẹ̀kírì na? #Warri #Benin #Yoruba,0,yoruba òní.. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ àti ìbi tí wọn wà.,0,yoruba "Iya Ife: Said Balogun, Kemi Afolabi àtàwọn òṣèré míràn ń ṣèdárò Iya Ife tó fayé sílẹ̀",0,yoruba RT @user: @user Ogun abele l'eleyi ti awon efon mba onile du ile. Won tun fe gbon ju onile lo! E gbiyanju lati ra awon (n ...,0,yoruba "Ìyá, múṣẹ́ ọrọ̀ ọmọ lókùnúnkúndùn, rántí wípé ọmọ t'ó bá dáa ni ti bàbá, ìdàkejì rẹ̀ ni ti ìyá. Ó d'ọwọ́ọ yín, ẹ̀yin ìyáa wa! #AyajoOjoIya",0,yoruba Àwọn ẹ̀kọ́ dídì yìí ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ìyá lo tun se joko.,0,yoruba "Wọn ti gbe awọn to farapa lo si ile iwosan Ijamba ọkọ naa la gbọ wi pe o ṣẹlẹ ni ibudo iwọkọ Ilasamaja loju ọna marose Apapa-Oshodi nigbati ọkọ akero ajagbe kan kọlu katako ipolowo nla kan, eyi ti o wo lu ọkọ akero kan. Wọn ti gbe awọn to farapa lo si ile iwosan Agbẹnusọ fun ileeṣẹ to n risi iṣẹlẹ pajawiri ni ipinlẹ Eko, Adebayo Kehinde (Lasema) to si fi idi isẹle naa mulẹ so wi pe iṣẹlẹ ijanba yi da ẹmi awọn ọkunrin mẹta legbodo lẹsẹkẹsẹ. O ṣalaye siwaju sii wipe awọn ọkunrin mẹta miran pẹlu obinrin mẹrin tun fara kaaṣa yanyan ti wọ̀n si ti gbe wọn lọ si ile iwosan fun itọju pipe. Ara adugbo ati awọn arinrinajo pejọ nibi isẹlẹ naa Atẹjade naa wipe ọga agba ileeṣẹ to n risi iṣẹlẹ pajawiri ni ipinlẹ Eko (Lasema), Adebayo Tiamiyu n rọ̀ awọ̀n awakọ̀ lati ṣe jẹjẹ loju popo, ki wọn si bikita fun ere asapajude. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:",0,yoruba Owó ìgbẹ́ kì í rùn. #Owe #Yoruba,0,yoruba "Ẹni tí kò mọ bí ẹgbẹ́ rẹ̀ ṣe là, á sá àsákú. / Whoever unduly bothers about his or her peers' relative successes, will hustle himself or herself to death. [Compare yourself to no one; stay in your lane.] #Yoruba #proverb",0,yoruba "RT @user: Yorùbá Word of the day """"""""""""""""Ìbínú"""""""""""""""" ⠀ ⠀ #learnyoruba #yorubawords #AngerinYoruba #ìbínú #nigerianlanguage #yorubalessons #yor…",0,yoruba "ANC kọ'we si aarẹ Jacob Zuma lati kọ'we f'ipo rẹ silẹ Igbesẹ lati yọ aarẹ Zuma naa ko sẹyin ọpọlọpọ ipade idakọnkọ ti awọn olori ninu ẹgbẹ oselu naa se titi di afẹmọjumọ ọjọ iṣẹgun oni. Iroyin wipe ti aarẹ Zuma ko ba kọ'we f'ipo s'ilẹ, awọn asofin lorilẹede naa yoo d'ibo mi o ni igbẹkẹle ninu rẹ, (vote of no confidence)"". Eleyi ti wọn gbagbọ wipe yoo sokunfa ifipo silẹ aarẹ Jacob Zuma. Ẹgbẹ́ òṣèlú ANC fẹ́ ki Jacob Zuma o kọ̀wé fi ipò sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bi ààrẹ South Africa Ẹgbẹ oselu ANC ko i ti fi abajade ipade rẹ sita, sugbọn lara awọn ọmọ ẹgbẹ oselu naa lo fi ọrọ naa lede fun awọn oniroyin lorilẹede South Africa ati ile isẹ iroyin Reuters News Agency. Opin Zuma: ANC se'pade lori aarẹ ANC fẹ yọ Zuma Lọpọ igba ni aarẹ Zuma ti kọ jalẹ lati kọwe fipo silẹ lori ẹsun iwa ibajẹ ati lilu owo ilu ni ponpo. Eyi to mu ki ẹgbẹ oselu rẹ yan Cyril Ramphosa lati dipo rẹ gẹgẹ bi asaaju ninu ẹgbẹ oselu naa. Awọn alakoso igbimọ pe ipade pajawiri fun ọjọ aje lati jiroro lori Aarẹ Zuma Amọ, ko i ti di mimọ fun awọn oniroyin bi aarẹ Zuma yoo se fesi si iwe ti wọn kọ sii lati kọwe fipo silẹ. Iroyin fi lede wipe, olori tuntun fun ẹgbẹ oselu ANC, Cyril Ramphosa kuro nibi ipade ẹgbẹ naa, lati lọ sọ fun aarẹ Zuma wipe ki o tete kọwe fipo silẹ, ki wọn ma ba a le kuro lori oye. Lẹyin naa ni Ramphosa pada sibi ipade idakọnkọ naa.",0,yoruba "tí Ọba fè se, Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.",0,yoruba "jú, àwọn ènìyàn ni ó pa Bàbá lo ni iwa rere.",0,yoruba "Ìpàdé oníròyìn ni a fi bẹ̀rẹ̀ ètò ní Ilé Ẹgbẹ́ Akọ̀ròyìn ní Lahore níbi tí wọ́n ti fi ẹ̀dùn ọkàn - an wọn hàn ; lẹ́yìn náà ni wọ́n yide kiri dé Ilé Àṣà Al Hamra níbi tí wọ́n ti jó , kọrin lọ́nà , kí wọn ó tó fọ́nká lẹ́yìn tí wọ́n jẹun tán .",0,yoruba "Gẹ́gẹ́ bí òfin , ilé ẹjọ́ lé gbé ìgbésẹ̀ tí ó tako irúu ìdájọ́ báwọ̀nyí yálà láti ọ̀dọ̀ àwọn panchayat tí ìbó yàn àti panchayat ipò - ìsàlẹ̀ .",0,yoruba "Ajọ ọlọpaa Benue fi idi iṣẹlẹ naa mulẹ fun awọn oniroyin Iboji naa ni awọn ọlọpaa ṣawari rẹ lagbegbe Gbatse, ni ijọba ibilẹ Ushongo, ni ipinlẹ lẹyin ti ọwọ ajọ ọhun tẹ awọn ajinigbe mọkanla. Awọn ajinigbe naa ni ajọ ọlọpaa ni wọn jẹwọ pe iboji naa ni wọn ma na sin awọn ti wọn ba si. Alukoro ajọ ọlọpaa ni ipinlẹ naa, Catherine Anene fi idi ọrọ yii mulẹ fun awọn oniroyin. Adari ikọ agbofinro ""Operation Zenda"" to mu awọn afurasi naa, ni marun un ninu awọn afurasi ọhun ti na papa bora, ti wọn si ti n wa wọn bayii. Ajọ ọlọpaa ni, awọn ọdaran naa lo ma n pa awọn eeyan lọna lati bo aṣiri wọn, lẹyin ti ti wọn ba ti ja wọn lole tan. Nibayi, awọn ẹbi awọn ti ọrọ naa ṣẹlẹ si ti kesi ajọ ọlọpaa lati sa ipa wọn lọna lati rii pe wọn wa okodoro ọrọ naa, ki wọn si fi awọn aje ọrọ na ba ṣimọ lori jofin.",0,yoruba "Àgbá bọ̀, wọ́n ní """"""""""""""""kékeré la ti ńpẹ̀ka ìrókò, tó bá dàgbà tán apá ò ní káa"""""""""""""""" #ISupportBreastCancerAwareness .",0,yoruba "Emeka Abugu ni oun di afoju lọmọde tori aisan igbona. Awọn obi rẹ gbiyanju titi wọn ṣa ipa wọn, wọn gbe e kaakiri fun ayẹwo ati itọju. Àrà méèrírí! Ọkùnrin tí kò ríran kan rèé tó ń lọ ẹ̀rọ ata Afọ́jú akẹ́kọ̀ọ́gboyè sọ̀rọ̀ nípa ìrírí rẹ̀ 'Dokita ilé ìwòsàn ló gba ẹsẹ̀ lọ́wọ́ mi' Nigba to dagba tan lawọn dokita sọ fun un pe oju rẹ ti fọ tan patapata ko le riran mọ Ọdọ baba rẹ lo ti bẹrẹ si ni lo irinṣẹ bii ""Spanner"" lati tun kẹkẹ ṣe. 'Mo fọ́ lójú ṣùgbọ́n mò ń tún àwọn ọkọ̀ tí iṣẹ́ rẹ̀ lè ṣe. Amotekun kò ní gbé ìbọn o! Ẹ wo ohun tí wọn yóò máa ṣe ní ìpínlẹ̀ - DAWN Commission 'A rí wàhálà táwọn Yorùbá ń kojú la ṣe fi ""Amotekun"" mú ọkàn wọn balẹ̀' 'Àwọn òyìnbó máa ń fẹ́ tọ́ oúnjẹ mi tí wọ́n rí lórí Instagram wò' Oju inu ni Emeka fi n ṣe gbogbo iṣẹ rẹ̀ to si fi n wo gbogbo awọn irinṣ to yẹ ko lo. ""Mo máa ń rí wọn pẹ̀lú ojú ẹ̀mí. Emi gan ni mo maa n lọ ra ẹya ara ọkọ fun'ra mi"".",0,yoruba "Ikọ onimọ ilera mejidinlaadọta lo ṣe iṣẹ abẹ naa lori awọn ibeji ọhun lẹyin oṣu mẹjọ ti wọn bi wọn. Eyi ni igba kẹta ti ile iwosan ijọba to wa ni Yola ti ṣiṣẹ abẹ lori awọn ibeji ti wọn bi bẹẹ ti wọn lẹpọ gẹgẹ bi adari ile iwosan naa, Ọjọgbọn Auwal Abubakar ṣe sọ ọ. Awọn to wa ninu ikọ to ṣe iṣẹ abẹ naa ni awọn dokita oniṣẹ abẹ atawọn onimọ ilera mii ti wọn lo wakati mẹta lati doola awọn ọmọ mejeeji lọjọ kẹwaa oṣu kẹjọ ọdun 2020 ti wọn bi wọn pẹlu ẹdọ ati eegun aya kan naa ti wọn jọ mu wa latọrun. Oniṣẹ abẹ agba to tun jẹ oludari ile iwosan FMC ni ilu Yola, Ọjọgbọn Auwal sọ pe iṣẹ abẹ naa jẹ aṣeyọri. ""Ẹdọ kan naa ati egungun aya kan naa ni wọn ni ṣugbọn a ti irinṣẹ kan wa ti a lo eyi to ran wa lọwọ gan lati din ẹjẹ ti yoo ṣofo ku ti yoo si mu iṣẹ naa pari laarin akoko kukuru"". Ọjọgbọn naa fi kun un wipe, wọn ti n ṣeto lati ṣe ipinya awọn ọmọ naa tipẹ ṣugbọn wọn ni lati dawọ duro di ọjọ kẹwaa, oṣu kẹjọ. Wo bí Sunday Orimola ṣe gba ikú ẹranko kú ní Ifon ni Ondo lórí ọ̀nà àtijẹ Bakan naa, awọn ọmọ naa wa daadaa ti wọn si ti bẹrẹ si nii ṣere lẹyin ọjọ mẹta ti wọn ti pari iṣẹ abẹ naa. ""Wọn ti gbe wọn pada si ilu wọn a si n pe wọn lori ago lai si iyọnu kankan. Awọn ibeji naa, Grace ati Mercy ti iya wọn, Aibekipriye Ebinyefa ni ọkan oun ti lọ lasiko ti wọn n ṣe iṣẹ abẹ naa toripe ẹu n ba oun fun ọjọ iwaju awọn ọmọ oun. ""Nigba ti wọn ni a maa ṣe iṣẹ abẹ, ẹru ba mi diẹ tori eeyan ẹlẹran ara lemi naa ati pe gẹgẹ bii abiyamọ, ẹru ba mi"". ""Inu mi ko dun pe emi ni obirin akọkọ to kọkọ bi ibeji to lẹpọ ni ilu wa ati ni ipinlẹ wa"". O ni awọn eeyan dẹyẹ si mi, wọn fi mi ṣe yẹyẹ, oju si n ti mi, ṣugbọn ni bayii inu mi dun tori ko sewu nibẹ. Lonii a ti n lọ ile. Ebinyefa sọ bẹẹ. Arabinrin naa sọ pe yoo wu oun ki awọn ọmọ oun naa di dokita ti wọn ba dagba. ""Mo kan ṣaa fẹ ki wọn di dokita ni ṣugbọn mi o mọ ohun ti wọn maa fẹ funra wọn ti wọn ba dagba tori gbogbo eeyan to dagba lo lẹtọ lati yan ohun to ba wu wọn"". Ṣugbọn o ni oun maa sọ fun wọn pe ki wọn naa le ran awọn mii to lẹpọ bii tiwọn lọwọ lọjọ iwaju"". 'Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé' Baba awọn ọmọ ọhun ni ""nigba ti iyawo mi bi awọn ibeji yii, mo ro o pe kilode ti eyi ṣẹlẹ si mi ni ọjọ ori mi yii ṣugbọn nibayii mo ti dupẹ lọwọ Ọlọrun"". Ijọba ibilẹ Nembe ni ipinlẹ Bayelsa ni iha Guusu Naijiria ni wọn ti bi awọn ọmọ naa ti wọn si gbe wọn wa si iha Ariwa nipinlẹ Adamawa latinu oṣu kini ọdun yii fun iṣẹ abẹ. Eyi ni igba ẹkẹẹta ti ileewosan ijọba ti Yola yoo ṣe iṣẹ abẹ fun awọn ọmọ to lẹpọ lẹyin eyi ti wọn ṣe lati ọdun 2018.",0,yoruba 👊Wà á gbayì!!! https://t.co/3PscPQXOTi,0,yoruba "àgbà ri pe lẹ ìkòkò wey ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Bàbá lo ni ìgbà mi owó àkokò, Olùwo ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni.",0,yoruba "Lootọ ni ibalopọ laarin ọkunrin ati obinrin jẹ nkan to ni adun pupọ, to si ma n mu ara ya daada, ṣugbọn bo sẹ dun to, awọn kan pinnu lati mu ara duro fun asiko kan. Imọ ijinlẹ sayẹnsi fihan pe ọpọlọpọ anfaani lo wa ninu ibalopọ loore-koore fun awọn ololufẹ. Igbagbọ awọn eeyan kan ni pe o lewu fun ẹni ti ko ba ni ibalopọ fun ọjọ pipẹ, to si le koba ilera ara wọn. Ṣugbọn ṣe lootọ ni? Iwadii kan ti BBC Igbo ṣe nipa ifọrọwanilẹnuwo pẹlu dokita onimọ iṣegun oyinbo kan, Udodi Okoli dahun ibeere yii. Dokita Okoli sọ pe imọ sayẹnsi ko tii sọ boya ewu kankan wa fun ilera ẹnikẹni ti ko ba ni ibalopọ . O ni nkan ṣoṣo ti sayẹnsi sọ ni pe o le nipa lori ironu iru ẹni bẹ́ẹ̀, paapaa nitori bi awọn eeyan ṣe le ma a fi ẹni naa ṣe yẹyẹ. Lara anfaani ibalopọ gẹgẹ bi dokita ṣe sọ ni pe, o ma n mu ki ara eeyan sinmi lẹyin wahala. Dokita miran, Malik Haruna King sọ pe ko si nkan to buru ninu ki eeyan pinnu pe oun ko fẹ ni ibalopọ. Iru ẹni naa ko le ni wahala kankan ni agọ ara rẹ. ""Koda, obinrin tabi ọkunrin ti ko ba ni ibalopọ fun igba pipẹ, yoo gbe igbeaye to dara bi awọn to n ni ibalopọ. Dokita Okoli sọ pe irọ patapata ni bi awọn kan sẹ ma n sọ pe ọkunrin ti kii ba ni ibalopọ rara tabi ni igba gbogbo yoo ni jẹjẹrẹ ni koropọn rẹ, Okoli sọ pe yatọ si ibalopọ pẹlu obinrin, awọn ọkunrin ma n da atọ loju orun, eyi ti awọn oni Gẹẹsi n pe ni 'Wet Dream'. Fun obinrin, ọ̀kan lara kudiẹ-kudiẹ to wa ninu aini ibalopọ fun igba pipẹ ni pe o le fa irora nigba to ba fẹ ẹ ni.",0,yoruba "Ajọ eto ilẹra ni Naijiria, Nigeria Medical Association, (NMA) ti sọ wi pe o kere tan eniyan mẹtala lagbaye ni yoo ni aisan rọpa-rọṣẹ lagbaye. Alaga Ajọ NMA ni ipinlẹ Kwara, Ọjọgbọn Baba Issa ni awọn fi ikilọ naa lede lati ṣayajọ Ọjọ aisan rọpa-rọṣẹ lagbaye, World Stroke Day. NMA ni o kere tan eniyan miliọnu mẹtala ni yoo ni aisan rọpa-rọṣẹ lagbaye, ti o kere tan eniyan miliọnu marun un yoo ba arun naa lọ. O salaye pe Ọjọ Kọkandinlọgbọn, Osu Kẹwaa, ọdun 2021 ni ayajọ ọdun naa ni agbaye, to si ni ikede yii yoo mu ki awọn eniyan kiyesi aisan yii lagbaye, nitori o ti fẹ di aisan tile -toko. Bakan naa ni wọn fikun un pe aisan rọpa-rọṣẹ ni ohun pa awọn eniyan julọ ni agbaye ati awọn to ti da dubulẹ si ti le si ni ojoojumọ. Bi o ṣe le da aisan rọpa rọṣẹ mọ ti o ba n bọ; Kiakia ni ki ẹ pe ileewosan pajawiri ti o ba ri awọn ami wọn yii.",0,yoruba "àkokò, Bàbá lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa òkè: ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo.",0,yoruba "Rédíò ẹlẹ́rọ - amìtìtì orílẹ̀ - èdèe Nàìjíríà ń jí gìrì sí ọ̀rọ̀ àṣàròo rẹ̀ tí ó ní “ ìgbésókè àwọn ènìyàn àti ṣíṣe ìsọdọ̀kan ètò afúnilóye , akọ́nilẹ́kọ̀ọ́ àti aṣínilétí tó ń ró àwọn ọmọ orílẹ̀ - èdèe Nàìjíríà lágbára láti ní ìfẹ́ ìlú ẹni .",0,yoruba ẹkọ́ ṣẹlẹ ni Lagos ti gbogbo eniyan sọ o dara. (2019),0,yoruba "Ọpọ eeyan nilẹ naa fẹran Magufuli, wọn gbagbọ pe iṣẹ ribi ribi lo ṣe nipa gbigbe ogun ti iwa ajẹbanu. Onwoye kan, Atilio Tagailile tiẹ sọ pe ọga ni Magufuli pẹlu ohun to ṣe lẹyin to di aarẹ orilẹede Tanzania titi o fi ku. Wọn dibo yan John Magufuli gẹgẹ bi Aarẹ karun un Tanzania lọdun 2015. Katakata ''bulldozer'' ni wọn n pe e wọn gboriyin fun Magufuli fun bi o ti gbogun ti iwa ajẹbanu ati inakuna ijọba lorilẹede naa. Magufuli ni arun jẹjẹrẹ ni iwa ajẹbanu eyi to nilo ki ijọba fi ọwọ lile mu.",0,yoruba Isegun yi isegun lo je gbogbo ise ibile tèmi. A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba "Ní igba mi owó àkokò, Ọmọ lo ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "Idagbasoke ọrọ aje orilẹede Ghana ti n mu ireti idagbasoke ọtun ba awọn eeyan ibẹ Lasiko to fi n ba awọn eeyan orilẹede Ghana sọrọ ni Aarẹ Akufo Addo ti sọ eyi di mimọ. Ọkan-o-jọkan isẹlẹ idigunjale, ifipa se'wọde ati ipaniyan to lọwọ awọn darandaran lọwọ lo ti n ranju mọọ mọeto abo lorilẹede Ghana. Idagbasoke to n de ba ọrọ aje Ghana ko tii han lara awọn ọ̀mọ orilẹede naa Saaju, owo to to ọgọsan miliọnu dọla owo ilẹ Amẹrika ni ijọba ti kọkọ gbe kalẹ lorilẹede naa lati kin awọn ọlọpa lẹyin ninu isẹ gbigbogunti iwa ọdaran eleyi ti aarẹ orilẹede Gahana ni yoo tubọ se miranwọ fun eto abo to munadoko. Aarẹ orilẹede Ghana ni igbesẹ to loorin ti n lọ lati wa ojuutu ẹlẹkunjẹkun si iwa ipa ati ikọlu awọn darandaran nibẹ Bakannaa ni aarẹ orilẹede Ghana tun kede wipe ayipada ti n de ba ọrọ aje oril€de naa pẹlu afikun pe ni opin ọdun yii ni owo iranwọ ti orilẹede naa gba lọwọ ajọ isuna agbaye, IMF yoo pari ti o si ni igbesẹ to yanranti ti wa nikalẹ lati rii daju wipe orilẹede naa ko maa sa tọ awọn orilẹede ati ajọ okeere mọ fun iranwọ. Aisi isẹ fun awọn ọdọ kun ara ipenija to n ba orilẹede Ghana finra Banki agbaye ti salaye saaju asiko yii wipe idagbasoke oniida mẹjọ ninu ọgọrun ni yoo de ba ọrọ aje orilẹede Ghana eyi ti yoo sun soke gẹgẹbii ọrọ aje to n dagbasoke ju lọ lagbaye. Amọsa o, ipa ayipda ati idagbasoke ọrọ aje yii ko tii maa fi ara han ninu igbe aye awọn ọmọ orilẹede Ghana. Bẹẹni Aarẹ Addo ko mu ẹnu lọ si ori ọrọ nipa ẹkunwo epo bẹntiroolu lorilẹede naa eleyi ti awọn ọmọ orilẹede naa kan tori rẹ se iwọde ni ọjọọru.",0,yoruba _Pa Àkọlé Jẹ,0,yoruba ilera ṣẹlẹ ni Ibadan ti gbogbo eniyan sọ o ṣe pataki. (2025),0,yoruba fún àwọn ìkòkò tí ó ga ju lọ nínú Nàìjíríà.,0,yoruba pe lẹ ìkòkò wey ti o ní wúlò.,0,yoruba "Oluwatobiloba Ipense jẹ oluṣọ ni Holy Gathering Evangelical Church of God, Papalanto ni Ewekoro Oluwatobiloba Ipense jẹ oluṣọ ni ileejọsin Holy Gathering Evangelical Church ti o wa ni Papalanto, ni agbegbe ijba ibilẹ Ewekoro. Kọmiṣọna fun ọlọpa ni ipinlẹ Ogun, ọgbẹni Ahmed Iliyasu ti o ṣe afihan afusari apaniyan yi ṣalaye wipe pasitọ naa pa ololufẹ rẹ lati fi ṣe aajo owo gẹgẹbi iwadi wọn ṣe sọ. Oluwatobiloba Ipense sinku arabinrin ololufẹ rẹ sinu ileejọsin rẹ Ọgbẹni Illiyasu wipe arakunrin kan to roukọ rẹ n jẹ Adebola Saheed ta awọn lolobo nigbati wọn ko ri ẹgbọn rẹ, Raliat Sanni ti o jẹ ẹni ọdun márùndínlógójì pẹlu ọmọ marun nile mọ lati ọjọ kejilelogun oṣu kẹta ọdun. O wipe ""Ninu ọrọ rẹ, oluṣọ-aguntan yi jẹwọ pe oun pa arabinrin naa ati pe oun sin oku rẹ sinu ijo oun lẹhin ti o ti bẹ ori rẹ ati ọwọ rẹ mejeeji fun awọn idi ti o kọ lati sọ fun awọn ọlọpaa."" ""Mo bẹ awọn eniyan lati maa ṣe akiyesi gbogbo awọn ti wọn ṣe alabapin pẹlu ati nigba gbogbo lati maa ṣe ayẹwo awọn ara adugbo wọn pẹlu loore-koore lati dẹkun irufẹ ijamba bayii lawujọ"". Awọn ọlọpa hu oku arabinrin naa jade ninu ṣọọṣi Ṣugbọn nigbati o n sọrọ pẹlu awọn oniroyin, afurasi naa sọ pe oun kii ṣe oun ni o pa arabinrin naa, o sọ pe ẹlomiran ni o ṣe ọṣẹ naa. Bakanna ni afurasi yi ti o jẹ olukọ ni ile-ẹkọ giga aladani Methodist ti o wa ni Arigbajo, sọ pe wọn fi ipa mu oun darapọ mọ ẹgbẹ okunkun ni. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:",0,yoruba Àwòrán ìsàlẹ̀ yìí ni àwọn ilé àjogúnbáa Bangladeshi tí àdàwólulẹ̀ ń bá :,0,yoruba C. Ronaldo: C. Ronaldo fi góòlù mẹ́ta bẹ̀rẹ̀ ọdún 2020 pẹ̀lú Cagliari,0,yoruba "Pẹlu omije ni May fi ṣe ikede rẹ ni adugbo Downing May kede ni owurọ ọjọ Ẹti pe oun yoo fi ipo naa silẹ ni ọjọ keje, oṣu Kẹfa, 2019, eyi ti yoo mu ki idije lati yan ẹlomii sipo naa o waye. Ninu ọrọ to sọ tẹdun-tẹdun, Abilekọ May sọ pe ''oun ti ṣe eyi ti agbara oun ka'' lati ṣe ègbè lẹyin abajade idibo apapọ ilẹ Yuroopu to waye l'ọdun 2016. Ni adugbo Downing street ni May ti ṣe ikede yii pe ó tó gẹ́, O digba ti wọn ba yan adari miran sipo ki Theresa May to kogba wọle patapata. Footballers: ìkà láwọn aṣojú agbábọ̀ọ̀lù míì lágbàyé Pẹlu omi ẹkun loju ni Theresa May fi ṣe ikede yii ni eyi to fidi aṣayan ọrọ Yoruba mulẹ pe ko si agbara ti ẹnikẹni le sà ju ti ẹni to juni lọ. Abdulfatah Ahmed: Àwọn Kwara fẹ́ dán ilé ọkọ kejì wo ni lásìkò yí",0,yoruba @user Ó yé mi! ó dára o! O yẹ kí a gbọ́ èdè arawa :) ṣé pé aláwọ̀ funfun ni yín?,0,yoruba Mo kọ́ bí a ṣe ń tọ́jú nǹkan ìní ẹni di ọjọ́ pípẹ́. #mothersday #Yeye #Yoruba #AbiamoAbojaGborogboro,0,yoruba "Jó ní ìgbà kan, a ri ìwájú to ba nìkan. Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba "@user: """"""""""""""""@user: #Jos lọ́ tún kàn, #Borno ti súu yín | #BokoHaram"""""""""""""""" o gaa"""""""""""""""" nǹkan ṣe",0,yoruba ẹ̀kó. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Bàbá lo lọ.,0,yoruba "Oun ni oludasilẹ Blindian Project to jẹ eto ori ayelujara to fi n yẹ awọn eeyan alawọdudu si latari irinajo ifẹ wọn pẹlu awọn ara Asia. ""Bawo ni mo ṣe le fi afẹsọna mi han fawọn obi mi"". Eyi ni ibeere to Jonah maa n ri gba ju latọdọ awọn ara Asia to maa n kan si i. ""Niṣe lẹru n ba mi gaan to nira fun mi lati wo oju baba mi, gbogbo igba ni mo n doju bolẹ. Ọpọlọpọ ni ko ni ireti mọ nitori eyi"". Ajoṣepọ eto ti Jonah n ṣe pẹlu iyawo rẹ Swetha ni wọn n ṣe lati ṣeranwọ fawọn eeyan bii tiwọn to n ronu bi wọn ṣe le mu ọkọ tabi iyawo afẹsọna dele. Risikat Moromoke Azeez: Inú èmí àti Òbí mi dùn nígbà ti Risi bí ọmọ olójú búlù- Wasiu Jonah ati Swetha bẹrẹ eto ti wọn n ṣe yii lọdun 2017. Awọn ololufẹ mejeeji pade lọdun 2015 ti wọn si bẹr si ni yofẹ ara wọn lẹsẹkẹsẹ bo tilẹ jẹ pe wọn kii ṣe ọmọ orilẹede kan naa. Wọn ri i wipe awọn jọ fran ohun kan naa to pọ loriṣiriṣi - ounjẹ, orin, afojusun iṣẹ, idagbasoke idile to jọrawọn. Ti wọn ba n ṣe eto ori ayelujara yii, wọn ni ọpọ eeyan lo maa n bere fun imọran awọn ti ibeere to ma n wọpọ si jẹ ""bawo ni mo ṣe le fi afẹsọna mi han fawọn obi mi"". Swetha ni ""ẹru maa n ba awọn eeyan, awọn eeyan ni ọpọlọpọ iṣoro to tan mọ aṣa nibi ti wọn ti wa paapaa ni Asia"". O ni wọn maa n ronu bakan bakan boya nipa ohun ti awọn eeyan alawọdudu lee ṣe si tabi ko ran awọn ara Asia. Eeyan kan tilẹ pe sori eto to n yọlẹ sọrọ kẹlẹ kẹlẹ torii pe ko fẹ ki awọn mọlẹbi rẹ gbọ ohun to n sọ. ""Mo ti wa pẹlu ololufẹ mi fun ọdun meji ati abọ bayii o si ti su mi ki n ma gbe igbe aye oloju meji"". O sọ fun Jonah pe aburo oun obinrin nikan loun ti sọ fun to si n gbero lati sọ fun gbọn rẹ ọkunrin naa laipẹ ki ọrọ tilẹ to lee kan awọn obi wọn rara. ""Ọkan mi n gbọn nipa ohun ti awọn obi wa maa sọ bi mo ba sọ fun wọn"". Jonah ati iyawo rẹ Swetha ti ran ọpọlọpọ eeyan lọwọ lati kọ wọn ni ọna ti wọn lee gba sọ fun obi wọn nipa ẹni ti wọn yan lati fẹ. Ki lo le ṣe too ba ba ara rẹ nipo ẹni to di ololufẹ ọmọ orilẹede tabi ya mii? Riri eeyan ti yoo to si ọ lẹyin ninu idile rẹ jẹ ohun kan. Sanya Salim ni nkan toun ṣe niyii o si rii pe ẹgbọn rẹ kunrin lo kọkọ ri ololufẹ rẹ soju. ""Asiko kan wa ti baba mi kọ lati ba mi sọrọ fun ọpọlọpọ oṣu lẹyin ti mo s fun un nipa Michael, ẹgbọn mi lo ṣi aṣọ loju ọrọ eyi si ni ọrọ to tobi ju taa sọ papọ nipa ololufẹ mi"". Ẹwẹ, oniruuru iṣẹlẹ to ti ṣẹlẹ nilẹ Amẹrika laipẹ yii ti ja funrarẹ fun awọn eeyan alawọdudu laarin awn araa ilẹ Asia. Apẹrẹ ni ifẹhonuhan #Blacklivesmatter. ""Mo yaa kẹnu bọ ọ̀rọ̀ gbogbo ifhonuhan to buru taa ri, nigba ti Kamala Harris tun wọle ggẹ bi igbakeji aarẹ Amẹrika, mo n sọ fun iya mi pe ṣẹẹ mọ pe abẹyameji loun naa bi emi ati Michael"". Asiko ti oo tu kẹkẹ ọrọ naa ṣe pataki ""Mo lero wipe asiko ti a yan bọ si dede. Asiko ti awa sọ baba ọrọ ṣe kongẹ ohun daadaa fun wa, asiko ti ololufẹ meji lee ni ifọkanbalẹ lati jẹ ki awọn eeyan mọ wọn papọ ki wọn si maa ri wọn ni gbangba"". Jonah ati Swetha ni ireti pe iriri awọn ati igbesẹ iranwọ tawọn n gbe yoo ran awọn eeyan alawọdudu to wa ni Asia ati lagbaye lọwọ. ""Awọn ọmọ wa jẹ ọdun mẹrin ati mẹfa a si n jẹ ki wọn dagba papọ ti wọn si fẹran awọ ara wọn bo ṣe ba jade.",0,yoruba "se. Nitori eyi, ara eni lo ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..",0,yoruba olùparapọ̀ ri pe jẹ́ pàtàkì wey ti o nuni ti o lẹ.,0,yoruba onìṣẹ́ ri pe jẹ́ pàtàkì wey ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ẹkọ́: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ àti ìbi tí wọn wà.,0,yoruba RT @user: Our #Kọ́MiLédè Today The words examined in this video are: - Àgbọ̀n (basket - Agbọ́n (wasp) - Àgbọn (coconut) - Àgbọ̀n…,0,yoruba "Daadaa la o ji o a o nii toju oorun doju iku o""""""""""""""""""""""""""""""""@user: A ò rọ́jọ́ so lókùn. #odaaro""""""""""""""""""""""""""""""""",0,yoruba Ọmọ tá o kọ́ ló ngbélé ta kọ́ tà. https://t.co/gIH38MUefS,0,yoruba Ìbà rẹ Ọlọ́run Ọba. Ọba tó jí wa sáyé lọ́jọ́ òní. Mo júbà rẹ Olódùmarè.,0,yoruba "Ọmọ Prof. Peller gbé 'gbá ìbò fún 2019 Shina Peller to jẹ́ ọmọ bíbí inú gbajúgbajà onídán tí gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Professor Peller ní òun yóò díje láti sojú kùn ìdìbò Iseyin, Itesiwaju, Kajola àti Iwajowa ti ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́. End of Twitter post, 1 Àwọn tó ní dandan àfi kí Shina Peller rawọ́lé òsèlú sọ pé àksìkò tó kí àwọn ará Ọ̀yọ́ wá ọ̀dọ́ tó sì ní òye sínú ìjọba fún ìdàgbàsókè ìpínlẹ̀ náà. Ó sọ ọ́ di mímọ̀ pé ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìgbà ni wọ́n ti rọ òun láti lo ànfàní pé ó jẹ́ gbajúgbajà mí ìpínlẹ̀ náà fún òsèlú sùgbọ́n tí kò tíì pinnu lọ́kàn rẹ̀. Shina ti fi ìgbà kan f'èsì wí pé ""ní báyìí, òwò mí ló jẹ́ àkọ́kọ́ lọ́kàn mi, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn ènìyàn mi ń fàmi n''ihìín lọ́hùún láti dara pọ̀ mọ́ òsèlú, sùgbọ́n mi ò tíì pinnu ọkàn mi"" Ọmọ bíbí ìsẹ́yìn náà sọ pé láti ìgbà tí 'ti wà nílé ìwé gíga fásitì Ladoke Akintola ní Ogbomosho lòun ti ń sèrànwọ́ àti ìgbaniníyànjú fún àwọn ènìyàn, èyi ni bí ó se di gbajúgbajà. Àworan Shina Peller Shina Peller tún mẹ́nu ba ọrọ̀ ajé orílẹ̀èdè Nàìjíríà, ó tẹnu mọ ọ wí pé ìgbafẹ́ ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ ànfàní tó le è mú ọrọ̀ ajé Nàìjíríà gbòòrò síi. Ó rọ ìjọba láti yé se ojú ayé lórí ọ̀rọ̀ à ń sọ ọrọ̀ ajé di ọ̀pọ̀ yanturu sùgbọ́n kí wọ́n dojú kọ ọ́ bó ti tọ́. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìṣẹlẹ iyinbon APC Ekiti : Ki gaan lo ṣẹlẹ?",0,yoruba ìwájú. Ọba lo ni àṣà ìdílé lo je ti ibile.,0,yoruba "Saheed Oṣupa on Nigeria's Politics: Mi ò ní ìyàwó nílé, àmọ́ bí mo ṣe ní ọmọrẹpẹtẹ rèé",0,yoruba @user @user Toò. a nretí o. Ọlọ́run a ṣọ́ wa dọ̀lá.,0,yoruba Ẹjọ mo bẹ àwọn aṣojú wá ní ilé igbimo asofin ti agbegbe wa.Kí wọn jọ se ìdìbò to tọ ati to yẹ fún òfin asopapo orílẹ èdè wà #TweetinYoruba,0,yoruba "ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn ẹ̀kọ́ ọmọ aláwọ̀ wà níṣẹ̀.",0,yoruba "Àkọ́kọ́, Alàji joko lòdì Òyó. A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà.. Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba ọkunrin ri pe jẹ́ pàtàkì wey ti o nuni ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó ga jù.,0,yoruba "Àṣà ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ohun ayé tí Ọ̀gá fi lé wa lọ́wọ́ l'ó fa jẹgúdújẹrá, ìjẹ àwòdì jẹun èpè sanra t'ó gbàlú kan. #OminiraNigeria #NigeriaAt56",0,yoruba "Amọṣa, yoo to ọsẹ mẹjọ si asiko yii ki wọn to ran an lọ si ẹwọn bi o tilẹ jẹ wi pe ahamọ awọn ọlọpaa ni yoo wa titi di igba naa. Ọlọpaa ni Derek Chauvin ni ipinlẹ Minnesota lorilẹ-ede Amẹrika ti fidio kan ti ọdọbinrin kan ti orukọ rẹ n jẹ Darnella ya lasiko ti Derek fi gbe orunkun le ọkunrin alawọdudu kan ti orukọ rẹ n jẹ George Floyd lọrun nigba ti wọn fẹ fi panpẹ ofin mu. Fidio yii lo di ilu mọọka lori ayelujara ti gbogbo agbaye fi kọminu lori iwa kotọ awọn ọlọpaa si araalu paapaa awọn Adulawọ nibẹ, eleyi to bi iwọde ""Black lives matter"" Ni ọjọ Iṣẹgun lawọn igbimọ oludajọ nile ẹjọ to gbọ ẹsun ti wọn fi kan ọlọpaa naa, Derek Chauvin gbe ero wọn sita lori ẹsun naa ti wọn si ni pe o jẹbi ẹsun naa. Ki lawọn adari lagbaye n sọ? Aarẹ Biden ati igbakeji rẹ Kamala Harris Aarẹ Biden ati igbakeji rẹ Kamala Harris wa lara awọn aṣiwaju lagbaye ti wọn kọkọ sọrọ lori idajọ naa. Biden ni idajọ naa ko to o, o fihan pe omi ṣi n bẹ lamu fawọn adari lorilẹ-ede Amẹrika. O ni wọn ni lati dẹkun iwa ẹlẹyamẹya lẹka gbogbo lorilẹ-ede Amẹrika. Biden ni ""a o le e dawọ duro nibi ti a de yii,"" ti oun ati igbakeji rẹ si, Kamala Harris si ṣalaye pe iwa ẹlẹyamẹya lẹkajẹka gbogbo to ti n waye ninu itan orilẹ-ede Amẹrika jẹ ""abawọn lara ẹmi orilẹ-ede wa"". Bakan naa ni Aarẹ Joe Biden, aya rẹ, pẹlu igbakeji rẹ Kamala Harris tun pe ẹbi oloogbe Floyd ni kete ti idajọ naa jade ti wọn si ki wọn ku irọju. Koda, wọn tun ṣe ileri pe igbesẹ yoo tọ idajọ naa lẹyin fun ayipada to yẹ lori ọrọ ẹlẹyamẹya nilẹ Amẹrika lati rii pe iku ẹni wọn ko ja si asan. Boris Johnson, olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi Ninu ọrọ tirẹ, olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi, Boris Johnson wa lara awọn olori orilẹ-ede lagbaye to kọkọ sọrọ lori idajọ naa. Boris Johnson, loju opo Twitter rẹ, kan sara si idajọ naa. ""Iku Floyd bami ninu jẹ gidi, inu mi si dun si idajọ naa."" Al Sharpton, ajafẹtọ ọmọniyan lorilẹede Amẹrika Ẹwẹ, eekan ajafẹtọ ọmọniyan lorilẹ-ede Amẹrika, alagba Al Sharpton tọka si idajọ naa gẹgẹ bi akoko imọlẹ laarin kurukuru ọjọ. ""Loni, a le e nu omije wa nu kuro ki a si tun mura ija fun ọjọ miran"" Bakan naa ni alagba Sharpton ṣeranti awọn alawọdudu gbogbo ti wọn ku latọwọ awọn ọlọpaa alawọfunfun. O si ran awọn ajafẹtọ bii tirẹ leti nibi ipade adura kan lẹyin idajọ naa pe isinku Daunte Wright, ọmọ ogun ọdun tawọn ọlọpaa yinbọn pa lọsẹ to kọja ku ọjọ meji pere. Barack Obama ati aya rẹ Michelle Barack Obama ati aya rẹ Michelle pẹlu ti sọrọ lori idajọ naa. Ninu atẹjade kan ti wọn fi sita, awọn mejeeji ni ""ohun to tọna ni ilu Minneeapolis ṣe"" ati pe ""igbesẹ to yẹ loju ọna ilọsiwaju"" ni. Nigba wo ni Dereck Chauvin yo bẹrẹ gbigba ijiya rẹ? Nibayii ni wọn ti gbe idajọ rẹ kalẹ, yoo to bii ọsẹ mẹjọ ki wọn to gbe ijiya rẹ sita. Amọṣa, niwọn to jẹ wi pe ko fi jẹ pe ko ni akọsilẹ iwa ọdaran kankan sẹyin, ilakalẹ ofin ni ipinlẹ Minnesota fihan pe o le e lọ si ẹwọn ọdun mejila. Awọn olupẹjọ lee gbe awijare kalẹ niwaju ile ẹjọ naa pe ki wọn fun un ni ẹwọn to to ogoji ọdun iyẹn bi onidajọ Peter Cahill to n gbọ ẹjọ naa ba wo o pe ọran rẹ le pupọ. Black lives Matter: Ọmọ Naijiria sọ ìrírí rẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ọlọ́pàá nílẹ̀ Amerika. Ni kete ti wọn gbe idajọ kalẹ ni ariwo ayọ lo gbode ni gbagede ile ẹjọ naa ti awọn eeyan kaakiri orilẹ-ede Amẹrika ti wọn ti peju lati mọ bi idajọ naa yoo ṣe lọ si n fo fayọ pe idajọ ododo fidi mulẹ lori iṣẹlẹ iku Floyd.",0,yoruba ẹkọ́ ṣẹlẹ ni Eko ti gbogbo eniyan sọ o ṣe pataki. (2014),0,yoruba "Ọkọ̀ọ Radio Nigeria ṣe ìpolówó ara rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi """""""" iléeṣẹ́ ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ ẹgbẹẹgbẹ̀rún ọdún , """""""" tí ó sì darapọ̀ mọ́ àwọn òṣìṣẹ́ rédíò kárí ayé fún ìsààmì ayẹyẹ Ọjọ́ Ẹ̀rọ - ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ Àgbáyé ọdún - un 2020 .",0,yoruba rò papa re yóò ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba "Oluwatoyin jẹ ko di mimọ wi pe ""ko si nkan ti ẹda alaye le da ẹ duro fun lati di nkan ti o fẹ di, bi o ba ṣaa ti le gbadura"". Owe ni Woli Arole fi ọrọ to wa loke yii pa nitori o mọ ohun ti o ti la kọja ninu irin ajo ere sinima o si mọ ohun ti awọn eniyan ti sọ si i. Eyi wa tun ṣe gẹgẹ iha ti awọn eniyan maa n kọ si didi eniyan nla laye ari itanjẹ ti wọn maa n gbagbọ gẹgẹ bi Arole ṣe ṣalaye ẹ ninu ọrọ rẹ. Ninu oṣu kẹrin ọdun 2019 ni Woli Arole bẹrẹ si ni ṣe agbejade ere agbelewo tuntun eyi ti o ko ọpọlọpọ gbajugbaja oṣere sinu ẹ.",0,yoruba "Bí kò bá sí alátakò , ó ṣe é ṣe kí ojú àwọn onírúurú ìyàtọ̀ ohun tí ọmọ - ìlú nílò ó máa jẹ́ ṣíṣe bí ó ti ṣe tọ́ .",0,yoruba ọ̀rọ̀ yi kún fún àwọn ìkòkò tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ẹkọ́: ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa.,0,yoruba "Bakan naa lo ni ki awọn gomina naa pe ipade apero lati jiroro lori awọn iṣoro Naijiria, ki wọn si wa ojutu si awọn iṣoro naa laarin ara wọn. Atiku lo sọ ọrọ ọhun ninu atẹjade kan to fi lede loju opo ibadọrẹ Facebook rẹ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Igbakeji Aarẹ tẹlẹri naa ni, ṣe lo yẹ ki awọn ọmọ Naijiria rere wa ojutu si awọn idojukọ ti Naijiria n koju lai fi ti ẹsin tabi ẹya ṣe. Oludije sipo Aarẹ labẹ asia ẹgbẹ PDP lọdun 2019 naa sọ siwaju si pe, igbagbọ oun ni pe Naijiria yoo bori gbogbo iṣoro to n dojukọ. O ni ""Iṣoro ti Naijiria n dojukọ ni pe a n pinya laarin ara wa, yatọ si pe a n pinya nipa ti ẹgbẹ oṣelu ati ẹsin."" ""Mo ti maa n sọ lọpọ igba pe iyatọ to wa laarin wa kii ṣe ni ti Guusu tabi Ariwa, bi ko ṣe nipa awọn eeyan rere atawọn eeyan buburu. Mo tun ti maa n sọ lọpọ igba pe ọmọ Naijiria pọmbele ni mi, o si yẹ ki a beere lọwọ ara wa, oun to n tumọ si lati jẹ ọmọ Naijiria."" Atiku sọ pe ojulowo ọmọ Naijiria ni ẹni to n bọwọ fun ẹtọ ẹlomiran labẹ ofin, ti ko si fi ti ẹsin tabi ẹya ṣe, to si n wa ilọsiwaju Naijiria pẹlu gbogbo ipa rẹ ni gbogbo igba. Africa Eye: Ahmed Isah rèé tíí ṣe ààrẹ lásán làsàn ní Nàíjíríà tí inú aráàlú dùn sí O ni ọmọ ""Naijiria rere kii da ilu laamu kii si ṣẹruba awọn alabagbe rẹ."" ""Titi di nnkan bii ọdun mẹwa sẹyin, ko si ohun to n jẹ ajinigbe-powo nilẹ yii, o si jẹ ohun ti ko fẹ ẹ ṣẹlẹ ri ninu itan orilẹ-ede wa."" Agba oselu naa sọ pe, a ko le tan iṣoro wa to ba jẹ pe bi a ṣe n ronu lati atẹyinwa naa ni a si ṣe n ronu bayii gẹgẹ bii ọrọ ti onimọ ijinlẹ Albert Einstein sọ. Atiku wa ke si awọn gomina ni Naijiria lati pe ipade apero laarin ara wọn lori ọna ati wa ojutu si ogunlọgọ iṣoro ti Naijiria n dojukọ nitori awọn iṣoro naa yoo pẹ titi ti wọn ba n duro de ijọba apapọ. Face Transplant: DiMeo ṣùn lásìkò tó n wa ọkọ̀ lálẹ́, ló bá jóná nígbà tí ọkọ̀ gbiná Lẹyin naa lo ke si gbogbo ọmọ Naijiri lati wa ni iṣọkan ki alaafia le jọba dipo iyapa ti awọn ẹgbẹ kan n pe fun.",0,yoruba àbùkù nlá gbáà lójẹ́ pé kòsí irúfẹ́ ẹ̀rọ iṣẹ́abẹ tí wọ́n nílò ní adúrú naija,0,yoruba "Igba mi owó àkokò, Ọba lo lọ. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..",0,yoruba Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó ṣe pàtàkì. (Item 125),0,yoruba "ÀÀRÙN COVID - 19 , NÍ ÈYÍ TÓ WÁYÉ NÍLÙÚ ÀBÚJÁ LỌ́JỌ́ AJÉ , ỌJỌ́ KẸTÀDÍNLỌ́GBỌ́N , OSÙ KẸRIN , ỌDÚN , 2020 ( MONDAY , 27th APRIL , 2020 ) .",0,yoruba "ìwájú. Nitori eyi, ara eni lo ni ọ̀gbọ́n.",0,yoruba Àwọn ẹ̀kọ́ dídì yìí ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó ga.,0,yoruba aláìì a yi fi ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Bàbá lo ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba jẹ́ ilẹ̀ agbègbè tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba iṣẹ́ ṣẹlẹ ni Eko ti gbogbo eniyan sọ o ṣe pataki. (1999),0,yoruba Edo State House of Assembly: Obaseki ní Oshiomole fẹ́ fipá gbàjọba lọ́wọ́ òun,0,yoruba _Fikún Dúrọ́wà...,0,yoruba ni ìlú tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba aráyé: ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọba lo lọ.,0,yoruba Àwọn ọ̀gá ti ní k'á máa jẹ ẹran ìgbẹ́ẹ wa lọ padà. #Ebola,0,yoruba "Satguru Maharaj Ji: Awọn ọmọ onílẹ̀ àti ọlọ́pàá jọ gbìmọ̀ pọ̀ láti gba ilẹ̀ mí Agbẹnusọ Maharaj, ọgbẹni Ojo Peter lo sọ eyi lasiko to ń ba BBC Yoruba sọ̀rọ̀ lórí bí àwọn ọmọ onílẹ̀ àti àwọn ọlọ́pàá ṣe yabo abúlé Maharaj ti àwọn ọlọ́pàá naa sì dúró tìwọn. O ní sáájú ni ilẹ̀ náà ti ń dá wàhálà sílẹ̀ láàrin Guru Maharaj àti Adegoke Amao pẹ̀lú Ṣoara Atere. Ṣùgbọ́n ilé ẹjọ́ ti fìdí rẹ̀ múlẹ̀ ní ọdún 2016 pé ebí ìyá Aláàdọ́rin, ló nilẹ̀ tí Guru Maharaj sì ti ràá lọ́wọ́ wọ́n. Lẹ́yìn èyí ni àwọn ọmọ ilẹ̀ Iragbiji tún de pe àwọn gan an ní àwọn nilẹ̀, Wọn ni o sì di dandan kí Satguru tún ilẹ̀ náà rà, àti ìgbà yìí ni wọ́n ti maa ń wá láti da omí aláafia abúlé Guru Maharaj rú agbẹnusọ fun Guru, Ojo ni: Sátide, ọjọ́ kẹtàdínlọ́gbọ̀n ní àwọn ọmọ onílẹ̀ kan wa pẹlu awọn ọlọ́pàá láti wá fi katakata hú gbogbo ǹkan ti wọ́n gbìn sórí ilẹ̀ náà ti wọ́n sì tún ṣe àwọn ọmọlẹ́yìn Maharaj tí wọ́n ń ṣiṣẹ́ lọ́wọ́ níbẹ̀ léṣe yánayàna. Ojo ni: ""Nígbà kan ti a lọ fi ẹjọ́ sùn nilé iṣẹ ọlọ́pàá ""Toll gate"" wọ́n padà dá ẹjọ náà nù ni lẹ́yìn tí wọ́n gbà àbẹ̀tẹ́lẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ọmọ onílẹ̀."" Lásìkò yìí bákan náà, àwọn ọmọ onílẹ̀ kó àwọn ọlọ́pàá leyin ni ti wọ́n sì ṣe àwọn tó n ṣiṣẹ́ lóri oko náà léṣe' Ó rọ ìjọba àpapọ àti ijọba ìpińlẹ̀ Oyo láti dá si ọ̀rọ̀ náà nítori ìdájọ ilé ẹjọ to waye ni 13/07/2016 ti parí ọ̀rọ̀ sùgbọ́n ti àwọn ọmọ onílẹ̀ Iragbiji tún wá lọ ń kó ọlọ́pàá sodí láti wá gba ilẹ̀ náà. Kini ile iṣẹ Ọlọpaa ipinlẹ Oyo sọ lori ẹsun Guru yii? Nigba ti ileṣẹ iroyin BBC kan si ọdọ awọn ọlọpaa ni ipinlẹ Oyo lati fi idi ọrọ yii mulẹ, awọn agbofinro ni ọrọ ko ri bẹẹ. Agbẹnusọ fun awọn ọlọpaa ni ipinlẹ Oyo, Olugbenga Fadeyi, ṣalaye pe oun gan an ko gbọ iru nkan to jó bẹẹ ri. Fadeyi ni iru rẹ ko le ṣẹlẹ pe ki awọn agbofinro tẹlẹ awọn ọmọ onilẹ lọ maa ja lẹyin idajọ ile ẹjọ. Eyi fihan pe, agbọn n ṣe bayii, ikamọdu naa n ṣe, bẹẹ oju oloko ree to wu yii. Kemi Dairo: Iṣẹ́ abẹ nínú ọpọlọ àti ẹ̀rọ ni mo fi ń gbọ́ ọ̀rọ̀ báyìí",0,yoruba "Adeherself fi ọrọ naa soju opo Instagram rẹ nibi to ti sọ pe gbogbo eeyan lo ti ri bayii pe iṣẹ loun ati Cute Abiola n ṣe pẹlu awọn fọto tawọn ti maa n fi sori ayelujara. ''Emi ati Cute Abiola dabi tẹgbọn taburo, ọrẹ kidi si ni ajọ jẹ. Akẹgbẹ mi ti mo bu iyi fun gidi ni Cute Abiola, gbogbo ohun tawọn eeyan n gbe kiri lori ọrọ naa bayii fihan pe iṣẹ awọn ni ipa gidi lori awọn eeyan ni. O jẹ ohun iwuri fun mi pe awọn ololufẹ wa n gba awada ti a n ṣe tọwọ tẹsẹ. Amọ ere lasan ni gbogbo rẹ, kii ṣe wi pe a n fẹ ara wa. Wọ́n rò pé mo ya wèrè ni Saudi lẹ́yìn ikú ọkọ mi Irufẹ iṣẹ ti a n ṣe lọwọ lo jẹ ki emi ati Cute Abiola ti a n ṣe ti a ṣe n fi fọto lọkọ laya ara wa sori ayelujara. Nitori naa, gbogbo awọn to ti n fede fọ lori ọrọ yii, ẹ ṣee. Simple tricks to identify designer shoes: Ṣe ìwọ lè wọ bàtà #2 mílíọ̀nú Mo le fi gbogbo ẹnu sọ pe inu mi dun pe emi ati Abiola ṣiṣẹ to jẹ nnkan iwuri,'' Adeherself lo ṣalaye bẹẹ. India, Coronavirus: Ìtọ́jú aláìsàn ló jẹ́ mi lógún nítorí ètò ìlera wa mẹ́hẹ- Nọ́ọ̀sì Kama",0,yoruba "Ikọ agbabọọlu Naijiria, Super Eagles tun ṣe kẹrẹkẹrẹ sun mọ ipele to kan ninu ifẹsẹwọnsẹ lati mọ awọn orilẹede wo ni yoo kopa ni idije ife ẹyẹ bọọlu agbaye lọdun to n bọ. Nibi ifẹsẹwọnsẹ wọn pẹlu awọn ikọ Lone Stars ti Liberia ni ilu Tangers lorilẹede Morocco, ikọ Super Eagles bori pẹlu goolu meji. Victor Osimhen lo gba goolu akọkọ wọlu pẹlu pẹnariti nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju karundinlogun ki Ahmed Musa to fọba lee pẹlu pẹnariti miran nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju kẹrinlelaadọrun. Pẹlu esi ifẹsẹwọnsẹ yii orilẹede Naijiria lo n leke ipin 'C' bayii pẹlu ami mejila ti Cape Verde, Central African Republic ati Liberia si n tẹle pẹlu ami mẹwaa, mẹrin ati mẹta ni ṣisẹ n tẹle. Ilu Tangers lapa ariwa orilẹede Morroco ni ifẹsẹwọnsẹ naa ti waye lẹyin ti ajọ ere bọọlu afẹsẹgba lagbaye sọ pe papa iṣire to wa ni ilu Monrovia lorilẹede Liberia ko ku oju iwọn rẹ.",0,yoruba Aago mélòó l'ó lù? Òkúta yìí jọ ẹ̀rọ ìdínwọ̀n ojúọjọ́ tí a mọ̀ sí #sundial lédè Gẹ̀ẹ́sì. #Yoruba #IleIfa #OgunEsa https://t.co/NQaSBrbdk5,0,yoruba nípa ìbadandun. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò.,0,yoruba "Agbẹjọ́rọ̀ fún El-Zakzaky, Femi Falana ní lóòtọ́ ni Àjọ DSS tí fún adarí IMN ní Naijiria náà láàyè láti lọ gba ìwòsàn. Agbẹjọrọ fun El-Zakzaky, Femi Falana lo sọ bẹẹ fun BBC Yoruba Falana ni asalẹ oni ni awọn mejeeji yoo gbera kuro ni ilu Abuja lọ si India lati lọ gba itọju. Kílò fa èdè àìyedè láàrin ìjọba àti àwọn ọmọ lẹ́yìn El-Zakzaky? O fikun wi pe awọn ko damu ara awọn lati mu asẹ ijọba ipinlẹ Kaduna se lori awọn ilakalẹ ti wọn fi le le lori irinajo El-Zakzaky lọ si India, nitori Ajọ DSS ti ni awọn yoo mu asẹ ile-ẹjọ sẹ. Bakan naa lo fi kun wi pe ohun ko ni ẹjọ kan kan ba ijọba ipinlẹ Kaduna ro. Agbẹjọ́rọ̀ fún Elzakzaky, Femi Falana ní ọdún 2015 tí wọn ti wà látìmọ́lé ni wọ́n kò tíì ní ìtọ́jú tó péye.",0,yoruba Ṣeun Ogundiya sọrọ lori igbesẹ akin to gbe lati lọ kawe nipa iṣẹ olukọni NCE ati ni fasiti OAU ni Ile Ife léyin iṣẹlẹ to gbe oun sori kẹkẹ fun BBC Yoruba. O rọ àwọn Dokita lati mu iṣẹ wọn ni ọkunkundun láì ba ayé àwọn alaisan jẹ́ nitori pe 'Bayii kọ ni wọ́n ṣe bi mi o!'. O gba gbogbo àwọn ti wọn ni ipenija oriṣii lati ma ṣe sọ ìrètí nù rara. Ní ipari Ṣeun Ogundiya rọ àwọn eniyan ki wọn dẹkun ìdẹ́yẹsí àwọn ti wọn ba ni ipenija ara nitori pe kò wù wọn bẹ́ẹ̀ rara.,0,yoruba Ilẹ̀ Ìbínú - land of anger. Ìbínú ► Ìbíní ► Benin #etymology #origin #yoruba #yobamoodua,0,yoruba "Níbì tí a ti máà gba kúkì. Àwọn fálù tó lè̀jẹ́ ni ""ibikíbi"", gbàgede lọ́wọ́ĺọ́wọ́"" àti ""àìsí-níbikíbi"".",0,yoruba ni òun tí a kọ eḳọ nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò.,0,yoruba iṣẹ́ ṣẹlẹ ni Lagos ti gbogbo eniyan sọ o ṣe pataki.,0,yoruba "ní àìlẹ̀, Baàlè ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba "ayé ọ̀ṣun. Nitori eyi, ara eni lo je gbogbo ise ibile tèmi.",0,yoruba Ìyá se. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba Ìyá lọ. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba Ìpalẹ̀mọ́ ọdún Kérésìmesì ọdúnìí mà pọyọyọ o. Ẹ wá wo bí wọ́n ti so'ná káàkiri gbogbo òpó-iná òpópónà.,0,yoruba Ẹ mà kú ojúmọ́ọ̀! Ṣé dáadáa la jí? Ara ò le bí?,0,yoruba Merry Christmas to all my people. ọdún yíì á san wá sówó á san wá sí aìkú báàlẹ̀ ọrọ̀. #yoruba #christmas #christmas song #sukutuibadan https://t.co/VhLgu3fSfT,0,yoruba "Ẹgbẹ Agbẹjọro nilẹ Naijiria, NBA, tí koro oju sì bí awọn ọlọpaa ṣe ṣekupa ọkan lara ọmọ ẹgbẹ wọn, Omobolanle Raheem lọjọ ọdun keresimesi ni agbegbe Ajah nilu Eko. NBA ni kiakia, ki ileeṣẹ ọlọpaa kede orúkọ ọlọpaa to ṣe kọlu naa sita. Iṣẹlẹ ọhun waye nigba ti oloogbe ati awọn mọlẹbi rẹ n ti ile jọsin bọ lọjọ Aiku to jẹ ọjọ keresimesi. Ninu atẹjade to fi lede, Aarẹ NBA, Yakubu Chonoko ni ẹgbẹ naa n ṣe akitiyan lati ba awọn mọlẹbi ọhun kẹdun lori iku ọmọ ẹgbẹ. O ni awọn si ti pinnu lati dìde iranlọwọ fun mọlẹbi ọhun. Chonoko ni awọn ti bẹrẹ iwadi lori ọlọpaa to ṣe iṣẹ buruku ọhun, ti awọn si ti kan si Kọmisona fun Ileeṣẹ ọlọpaa fun ipinlẹ Eko, Abiodun Alabi. O tẹsiwaju pe ileeṣẹ ọlọpaa ti fi idi rẹ mulẹ fun awọn pe orúkọ afurasi ọlọpaa to ṣekupa oloogbe naa ni ASP Drambi Vandi, ẹni to ti wa lẹnu isẹ ọlọpaa fun ọpọlọpọ ọdun. ""A rọ ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Eko lati kede orúkọ awọn ọlọpaa wọnyi fun gbogbo ọmọ Naijiria. ""Ẹ kede wọn fun wa, gbogbo nnkan to yẹ ka mọ ni kí ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Eko kede fun awọn ọmọ orile-ede Naijiria."" Bakan naa ni Gomina Ipinlẹ Eko, Gomina Babajide Sanwo-Olu ti ransẹ ibanikẹdun si mọlẹbi oloogbe Omobolanle Raheem. Sanwo-Olu wa n fi da awọn mọlẹbi loju pe ijọba yoo ri pe idajọ òdodo waye lori isẹlẹ naa. Sanwo-Olu ni o ṣe ni laanu pe awọn to yẹ ko da bobo awọn araalu naa lo tun ṣekupa wọn, sugbọn ijọba oun ko ni fi ọwọ lẹran lori ọrọ naa. O ni inu oun dun pupọ pe afurasi apaniyan ti wa ni atimọle ileeṣẹ ọlọpaa, ti wọn si ti gba gbogbo ohun ija lọwọ re. Gomina wa ro awọn eeyan ipinlẹ Eko lati ṣe suuru lori ọrọ naa atipe ìjọba ìpinlẹ Eko ti setan lati ri pe idajọ jẹyọ lori iku Omobolanle Raheem Ọga agba ọlọpaa lorilẹede Naijiria, Usman Alkali Baba ti paṣẹ pe ki iwadii to ya kanmọ-kanmọ waye lori iku Amofin Ọmọbọlanle Raheem, ti ọlọpaa kan yinbọn pa. Ọga ọlọpaa Alkali Baba tun paṣẹ pe ohunkohun ko gbọdọ di fifi kọlọransi ọlọpaa naa jofin ni kiakia. O ṣalaye ninu atẹjade kan, eyi ti alukoro ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria, Ọmọọba Olumuyiwa Adejọbi fọwọsi, pe iṣẹlẹ buruku naa kii ṣe afihan ihuwasi ileeṣẹ ọlọpaa ni Naijiria. Bakan naa lo tun ba awọn ẹbi oloogbe naa kẹdun ẹni wọn to lọ. O si tun kilọ fawọn ọlọpaa pe ki wọn maa fi iwa ọmọluabi kun iṣẹ wọn ni gbogbo igba. Ọga agba ọlọpaa ni Naijiria naa tun fi da awọn ọmọ Naijiria loju pe gbogbo ika to ba ṣẹ lori ọrọ naa ni ida ofin yoo ge. Ọlọpaa kan ti wọn ko darukọ rẹ ti yinbọn pa obinrin agbẹjọro kan, Bolanle Raheem, lagbegbe Ajah, nipinlẹ Eko. Iroyin ni asiko ti oloogbe naa atawọn ẹbi rẹ n bọ lati ijọsin ọjọ ọdun Keresimesi ni iṣẹlẹ naa waye. Gẹgẹ bi ohun ti a gbọ, ọlọpaa ọhun atawọn akẹgbẹ rẹ gbiyanju lati mu ọkọ Bolanle duro ki iṣẹlẹ naa to waye. Asiko ti ọkọ ti Bolanle wa ninu rẹ n gbiyanju lati yi obiripo to wa labẹ afara Ajah ni ọlọpaa naa ṣina ibọn bolẹ. Amọ nigba ti wọn yoo fi gbe dele iwosan Bolanle ti jade laye. Ẹwẹ, agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko, Benjamin Hudeyin ti sọ pe iṣẹlẹ naa jẹ eyii to ṣeni laanu. Ninu atẹjade kan loju opo Twitter rẹ, ọwọ awọn ti tẹ ọlọpaa to yinbọn pa oloogbe naa, yoo si foju wina ofin. Hundeyin sọ pe “A ti fi ọlọpaa to yinbọn atawọn meji mii si atimọle.” O fi kun pe awọn yoo tun tare ẹjọ naa lọ si ẹka ileeṣẹ ọhun to n ṣewadii iwa ọdaran ni Panti fun iwadii ni kikun. Lẹyin naa lo ni ni kọmiṣọna ọlọpaa ipinlẹ Eko ti kan si awọn mọlẹbi oloogbe ọhun. O ni “Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko ba awọn ọrẹ ati mọlẹbi agbẹjoro Bolanle Raheem kẹdun.” “Kọmiṣọna ọlọpaa, CP Abiodun Alabi ti kan si awọn ẹbi oloogbe naa ati ẹgbẹ awọn agbẹjọro, NBA lana, o si fi da wọn loju pe wọn yoo ri idajọ ododo gba.” Wayi o, ọpọ awọn araalu lo ti bẹrẹ si n bu ẹnu atẹ lu ileesẹ ọlọpaa fun bi awọn oṣiṣẹ rẹ ṣe n dukoko, ti wọn si maa n fi iya jẹ araalu lọna ti ko ba ofin mu.",0,yoruba ó dàbí ẹni pé o fẹ́ràn èmi náà like bọ̀bọ́ yẹn ganan,0,yoruba to greet a pregnant woman say things like ẹ kú ìkúnra ẹsẹ̀ á tẹlẹ̀ ayọ̀ à á gbóhùn ìyá àti tọmọ wẹ́rẹ́ la máa gbọ́ wọn ò ní gbókùú jáde nínú alààyè wọn ò ní gbálààye jáde nínú òkú b,0,yoruba "Makinde ti tu aṣiri bi wọn ṣe n pin owo ti wọn ba ya sọtọ fun akanṣe iṣẹ ni ipinlẹ Ọyọ, lasiko ijọba gomina ana ni ipinlẹ naa. Makinde ni bi gomina ana ṣe n gba, ni iyawo rẹ naa n gba owo bọbẹ lara owo ti wọn ba ya sọtọ fun ṣiṣe akanṣe iṣẹ agbaṣe ni ipinlẹ Ọyọ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Gomina ipinlẹ Ọyọ, Onimọ ẹrọ Ṣeyi Makinde sọ ọrọ yii o lasiko to n fọrọ werọ pẹlawọn araalu lori ọgọrun ọjọ iṣejọba rẹ. Ṣe ẹ ranti pe Seyi Makinde funrarẹ lo sọ ko to de ori oye pe, gbogbo ohun ti araalu n foju wo gẹgẹ bi aṣiri imulẹ ninu iṣejọba ni oun yoo ṣi aṣọ loju rẹ ni kiakia. ""Ohun ti a ba nilẹ ni pe ki wọn gbe owo jade fun iṣẹ agbaṣe ki o jẹ pe ida mẹwa ninu ọgọrun owo ti wọn gbe jade ni wọn yoo fi ṣe iṣẹ akanṣe ti wọn tori gbe owo naa jade. ""Ohun ti wọn sọ fun wa ni pe, ilaji owo ti wọn gbe jade fun iṣẹ agbaṣe ọhun ni yoo pada si apo gomina, ida ọgbọn ninu ọgọrun owo yoo lọ si ọdọ ẹni to fi ọwọ si gbigbe owo naa jade. Ninu ida ọgbọn yii ni wọn yoo si tun ti yọ ida mẹwa fun iyawo gomina. Ṣugbọn emi ti wa sọ fun wọn pe, ẹnikẹni to ba san iru aṣọ bẹẹ ṣoro labẹ iṣejọba mii yoo jẹ iyan rẹ ni'ṣu."" Gomina Makinde ni igbesẹ to lamilaaka ni iṣejọba oun n gbe bayii, lati dẹkun iwa jẹgudujẹra lẹnu iṣejọba. O ni idi gan an niyi ti oun fi gbe aba kan kalẹ fun idasilẹ ajọ ti yoo maa gbogun ti iwa ijẹkujẹ ni ipinlẹ Ọyọ. Lootọ gomina Makinde ko darukọ ẹnikẹni ṣugbọn ọpọ araalu lo ti n na ika si Sẹnetọ Abiọla Ajimọbi, nitori pe oun naa lo ṣe ijọba ki Makinde to gba ipo naa ni oṣu karun ọdun yii.",0,yoruba @user Ẹ ẹ̀ bámi dúpẹ́ lọ́wọ́ Ilé-iṣẹ́ asọ̀rọ̀mágbèsì Abẹ́òkút. Àwọn ni wọ́n ṣe irú ànfàní yìí. http://t.co/sZB4VSn2,0,yoruba Ìròyìn tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ẹkọ́: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọmọ lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ẹkọ́: ti o pataki.,0,yoruba "Ojogbon Soyinka maa n s'ọrọ lori eto ilu loore-koore Ọjọgbọn naa tun beere fun pe ki minisita fun eto aabo ko ọrọ ti o sọ danu, eyi ti o n gbe agbara wọ awọn darandaran lati tẹsiwaju iwa ipaniyan. Soyinka tẹsiwaju pe gbigba awọn darandaran yii laaye fun igba pipẹ ni ohun ti o fa bi iwa ipaniyan yii se waa peleke si lorilẹ-ede Naijiria bayii. O sọ pe, ""A ti gba iparun oko awọn agbẹ lọna ti eyikeyi iru agbegbe ti ọrọ ba kan ko lee f'arada mọ, eyi ti o si jẹ ohun meeriri fun ọpọlọpọ wọn. ""Ti a ko ba kọ ibi ara si nnkan bayi lati ibẹẹrẹ, ohun ni o maa n fa ki ipaniyan o peleke sii. A gbọdọ koju irufẹ iwa bayii lẹsẹkẹsẹ."" Nigbati o n gba awọn agbẹ ati awọn olori igberiko ni imọran lati daabobo ara wọn kuro lọwọ ipaniyan awọn darandaran, Soyinka sọ pe ""ijafara lewu, ati pe awọn eniyan ko gbọdọ duro ki awọn darandaran gb'ẹmi wọn ki Naijiria to bẹrẹ iṣẹ lati dena ipaniyan bayi. Ọjọgbọn Wọle Soyinka bu ẹnu ẹtẹ lu aarẹ Buhari fun ipaniyan awọn fulani darandaran Soyinka tun sọ wipe awọn ọmọ-ogun orilẹede Naijiria ni lati mu awọn alamojuto eto aabo ṣinṣin ati pe wọn gbọdọ daabo bo ẹmi awọn ara ilu ati dukia wọn pẹlu. Ọpọ asise to kun inu ijọba Buhari lo jẹ afọwọfa Soyinka wa mẹnuba igbesẹ bi Buhari se pe akọwe apapọ fun ajọ to nse amojuto eto adojutofo nidi ilera (NHIS), Usman Yusuff pada sẹnu isẹ, lẹyin ti minisita feto ilera, Ọjọgbọn Isaac Adewọle ni ko lọ rọọkun nile na nitoripe o se owo ilu basubasu, gẹgẹ bii apẹrẹ kan to n safihan pe oniruuuru asise afọwọfa lo kun inu isejọba Buhari dẹnu. Sugbọn awọn agbẹnusọ fun aarẹ Buhari ko tii fesi pada lori ọrọ yi. A o maa mu esi wọn wa fun yin ni kete ti wọn ba ti fesi. Gbogbo akitiyan BBC Yoruba lati ba awọn agbẹnusọ fun aarẹ Buhari s'ọrọ ja si pabo.",0,yoruba A lò ó pẹlú àṣẹ .,0,yoruba Gbeŕ fèrèsé ga ju àwọn fèrèsé mìíràn lọ,0,yoruba a kú ọdún ooooo kí gbogbo yín ni ọjọ́ kerésìméèsì tó dùn yùngbàyùngbà,0,yoruba jẹ́ pàtàkì wey ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò.,0,yoruba "Àwọn ọ̀nà ti ẹ lè gbà kojú omí yale àgbára ya sọọbù Ní ọdún yìí àjọ tó ń ri sí bí ojú ọjọ ṣe ri ti kìlọ pé àwọn ìpínlẹ̀ marun un ní gúúsù ìwọ̀-oorù Nàìjíríà Lagos, Ogun, Ondo, Oyo àti Osun yóò kojú ẹkún omi yale àgbàrá sọọbù. Kayeefi: Facebook ni Wolii Arole Jesu fi tàn an wọ agbo, orí rẹ̀ ni wọ́n fi s'owó Nítorí ìdí èyí ni BBC Yorùbá ṣe sàlàyé àwọn ọ̀nà ti e lè gbà láti dènà ìṣòro omíyale àgbàrá ya sọọbu. Kíni àwọn ìgbẹ́sẹ̀ láti dènà omíyale àgbàrá ya sọ́ọ́bù Ó ṣe pàtàkì láti mọ pé kò yẹ láti kọ́le si etí ibí ti omí odò ń gbà kọjá tabi kọle si ojú àgbàrá: O wá ṣeéṣe ki ẹlòmiran ti kọ́le si ètí omí, ọ̀nà abáyọ míràn tún ní pé, lásìkò ọ̀gbẹlẹ̀, o ṣe pàtàkì láti mọ ọgbà yii ilé náà ka, bákan náa ní kí a gbìyànjú láti gbin igi ti yóò dúro bi araba lati dí agbàrá lọ́wọ́, láti ma wọle. O ṣe pàtàkì láti máa dágunla si ìkéde àjọ tó n ri sí bí ojú ọjọ́ yóò ṣe rí: Ní ọ̀pọ̀ ìgbà ní àwọn àjọ yìí máa ń kéde bí ojú ojọ́ yóò ṣe ri, òjò ti yóò fa ọmí yale, nígbà ti irú ìpè yìí bá wáye kò yẹ ki ará ìlú keti ọ̀gbọ́in síi, ó ṣe pàtàkì láti maa gbọ rẹdíò, tẹlẹfisọn àti kika ìwé ìròyìn ní gbogbo ìgbà láti mọ nípa àwọn apá ibi ti amíyale yóò ti wáye. Gẹ́gẹ́ bi ọlọ́dani o ti dídandan láti dẹ́kun jíju ìke àti ọ̀rá sí ojú àgbàrá: Ní ọ̀pọ̀ ìgbà àwọn ìgbòkegbòdò ará ìlú náà maa ń dẹ́kun omiyalé àgbàrá ya sọ́ọ́bù, ọ̀pọ̀ àwọn ènìyàn ti wọ́n ba ti gbọ́ kíkù òjò ní wọ́n ti lọ da gbogbo ìdòtí ilé wọ́n sí ojú ibi ti ó yẹ kí àgbàrá gbà, èyí jẹ ọkan lára ǹkan ti ó ń fa ẹkún omi, bákan náà o ye ki ará àdúgbò maa kóra jọpọ̀ láti ṣe ìtóju ojú àgbàrá Ìjọba ní láti gbé ìgbésẹ̀ lóri bí ojú ọjọ sé ń yí: Ọ̀rọ̀ àyí padà ojú ọjọ́ jẹ ǹkan pàtàki tí gbogbo ìjọba gbe lọ́wọ́ ní àgbàyé, èyí jẹ ǹkan ti o yẹ ki ọlọdani náà mọ, àyípada ojú ọjọ́ ló faa ti omi fi kú kọjá ibi tó yẹ, nítori ìdí èyí ọ̀rọ̀ náà kìí ṣe ti ìjọba nìkan bíkoṣe pe àti ará ìlú àtí ìjọba ló yẹ ko saapa láti dẹkun omiyale Ìjọba gbọdọ sẹ àtúnṣe àwọn ojú àgbàrá àti ibi ti omí to ba ń jade lati ojúle kọ̀ọ̀kan yóò maa dari si: Ọ̀pọ̀ àwọn awọn orilẹ̀-èdè lo ti ṣe àwọn ètò yìí nígbà ti wọ́n bá n ṣètò àdúgbò síbẹ, ìjọba orilẹ̀-èdè, pàápàá jùlọ ìjọba ìpínlẹ̀ kìí ṣe àwọn ètò yìí, bí ìjọba bá le ṣe àdínkù yóò ba ẹkun omi yale àgbàrá ya sọọbu.",0,yoruba Awọn ọmọdébìrin yìí ti wà ní àhámọ́ Boko Haram fún ọjọ́ pípẹ́. Ìjàmbá ọkọ̀ ọ̀ún ni a gbọ́ pé ó wáyé nígbà ti awọn obi náà fẹ́ lọ yọjú sí awọn ọmọ wọn tí wọ́n dá sílẹ̀ ní àhámọ́ Boko Haram tí wọ́n wà ní ile ẹ̀kọ́ gíga ti ilẹ̀ Amerika to wà ní Yola. Ní ìlú Chibok ni awọn òbí awọn ọmọ òuń ti gbéra lati lọ sí ìlú Yola lọ yọjú sí àwọn ọmọ wọn. Lágbede méjì ojú ọ̀nà ni ìròyìn sọ pe ọ̀kan lára àwọn awakọ̀ to wa ọkọ̀ oun lọ forísọ ọkọ̀ àjàgbé kan ti wọ́n fi ń sisẹ́ ojú ọ̀nà.,0,yoruba "Gbogbo ẹni tó gun òkè #Arafat lọ́dúnìí, àdúrà ó gbà o. Ẹ káàbọ̀. #salah",0,yoruba RT @user: Iru wahala wo le 'yi bayi iwo olorun. Kilode.,0,yoruba "àkokò, Ọmọ lo ni àṣà yorubá eyti o gbe lori ọ̀run dídì.",0,yoruba "Ohun kan ti ẹbi rẹ mọ ni pe wọn lo gun kẹkẹ lọ sita. Alọ rẹ ni wọn ri, wọn ko ri abọ rẹ fun ọdun mẹfa. Ohun kan ti ẹbi rẹ mọ ni pe wọn lọ gun kẹkẹ lọ sita. Alọ rẹ ni wọn ri, wọn ko ri abọ rẹ fun ọdun mẹfa. Wọn wa a fun ọpọ igba pẹlu igbagbọ pe wọn yoo ri lọjọ kan nitori ẹni to ku ati ẹni to nu a pade lọjọ kan, amọ nigba to ṣe diẹ, wọn gba fun Ọlọrun. Baba Samuel jẹ oniyawo mẹrin, o si bi ọmọ mẹtadinlogun. Botilẹjẹ pe iya Samuel ati baba rẹ ti kọ ara wọn silẹ, Samuel ni ẹgbọn obinrin kan, ti awọn mejeeji jọ fẹran ara wọn daada nigba naa. Samuel ni iya gbe lọwọ yii lọdun diẹ ṣaaju ki wọn o to o jigbe. Ẹgbọn rẹ obinrin yii, Firdausi Okezie, wa nileewe giga fasiti lasiko ti iṣẹlẹ yii waye. Lẹyin ọdun diẹ, o pari ẹkọ rẹ. O si wa iṣẹ aje wa si ilu Eko. Dide to de si Eko, o yipada di ẹlẹsin Kristiẹni. O si bẹrẹ si ni lọ si ijọ Living Faith Chapel, ti a tun mọ si Winners Chapel. Ijọ naa maa n ṣe ipagọ ọlọdọọdun l'oṣu Kejila ọdun. Iru ipade yii ni Firdausi lọ ni ọdun 2000. Titi di asiko naa, ko ti i ri iṣẹ kankan ṣe. Eyi lo mu ki o gba ọkan lara awọn ìsọ ti ijọ naa maa n fun awọn ọmọ ijọ lati fi ta ọja lasiko ti ipagọ ba n lọ lọwọ. Nibi ti kafinta kan ti n ba Firdausi kan pako ti yoo to aṣọ adirẹ to n gba lati ọwọ iya rẹ fun tita, lo ti taju kan, to si ri ọkunrin kan to n tọrọ bara. Gbigbe ti yoo gbe oju soke, o ṣakiyesi pe ọmọkunrin to n mu onibara naa rin jọ aburo rẹ, ti wọn ti n wa fun ọdun pipẹ, t'oun ti aṣọ idọti lọrun. Ariwo to pa nitori idunnu mu ki awọn eniyan o pe le wọn lori, wọn si doola aburo rẹ. Ariwo to pa nitori idunnu mu ki awọn eniyan o pe le wọn lori, wọn si doola aburo rẹ. A ṣe bi wọn ṣe ji Samuel gbe nilu Kano, ilu Eko ni wọn gbe e wa. Ti obinrin kan to ra a lọwọ wọn si fi maa n ṣọfa fun awọn onibara ti yo maa mu kiri. Ẹẹdẹgbẹta Naira ni obinrin naa maa n gba lasiko naa lọwọ onibara kọọkan to ba fẹ lo Samuel. Samuel nikan kọ lo n ṣe iru iṣẹ yii ninu ile ti obinrin naa n gbe. Awọn alajọgbele rẹ kan naa n lo awọn ọmọde fun iṣẹ naa. Samuel nikan kọ lo n ṣe iru iṣẹ yii ninu ile ti obinrin naa n gbe. Awọn alajọgbele rẹ kan naa n lo awọn ọmọde fun iṣẹ naa. Lẹyin ti wọn ri Samuel, ko wulẹ pada si ilu Kano mọ. O n gbe ni ọdọ ẹgbọn rẹ, o si pada sileewe alakọbẹrẹ bo tilẹ jẹ pe o ti dagba ju, ti ọpọ ileewe si kọ ọ. Laarin oṣu mẹta pere, Samuel ti bọ si kilaasi kẹrin lati ikinni. Laarin ọdun kan, o wọ ileewe girama. Samuel ati ẹgbọn rẹ lọjọ ti o n ṣe igbeyawo, lẹyin bi ọdun meji to ri i. Ọdun mẹta pere ni Samuel lo nileewe girama to fi ṣe idanwo JAMB bọ si Fasiti Ahmadu Bello to wa ni Zaria. Contortionist: Mo lè gbé ìfun mi pamọ́ ki n tún se èémí! Ṣugbọn o ṣeni laanu pe iwe ti Samuel mọ daada naa ni yoo fi opin si iwe kika a rẹ. Ọdun kẹrin lo wa nileewe nigba ti ọwọ tẹ ẹ pe o joko ṣe idanwo fun akẹkọọ mi. Wọn si le e kuro nileewe naa. Samuel sọ pe iriri ti oun ni l'oko ẹru lo sọ oun di ẹlẹyinju aanu. Samuel to ti pe ẹni ọgbọn ọdun bayii, n ṣiṣẹ alamojuto ile kikọ. Toma Unu: Ọmọbìnrin tó ń fi ẹsẹ̀ rẹ̀ ya àwọran nítori pe ó ni ìpènija ọpọlọ ''Nigba ti nkan ba dara fun mi tan, mo ni ireti lati tẹsiwaju eto ẹkọ mi. O sọ pe imọ ijinlẹ nipa ẹrọ ayelujara si ni yoo wu oun lati kọ. 'A fẹ́ kí àwọn sẹ́nétọ̀ gba ẹlòmíì láàyè' Samuel ni oun ko kabamọ lori iriri oun ni ahamọ ati pe o jẹ ohun ibanujẹ fun oun. O gbagbọ pe awọn iriri naa lo sọ ọ di oloju aanu, ti kii fi oju kere ẹni to ba nilo iranlọwọ tabi jẹ onibara. Awọn aworan inu itan yii wa lati ọwọ oṣiṣẹ BBC, Manuella Boloni",0,yoruba "Ni Naijiria ati lorilẹede Egypt ni gbogbo awọn ọmọ Naijiria ti n fi idunu han si bi Super Eagles ṣe da sẹria iya fun Bafana Bafana. Kete ti ifẹsẹwọnsẹ naa pari ni ariya ti bẹ sode lorilẹede Egypt laarin awọn ọmọ Naijiria to wa nibẹ. Bakan naa ni ọrọ ikini n jẹyọ lọtun losi latọdọ awọn ọmọ Naijiria lati dupẹ lọwọ ikọ Super Eagles ati lati fi anfani naa sọ ireti wọn. Aarẹ orileede Naijiria Muhammadu Buhari ti pẹlu awọn ọmọ Naijiria lati fi ikini ku orire ranṣẹ si ikọ Super Eagles lori bi wọn ṣe bori ikọ South Africa ninu idije AFCON. Ami ayo si ọkan ni Naijiria fi ṣagba akẹgbẹ wọn lati tẹsiwaju lọ abala to kangun si aṣekagba. Aarẹ Buhari ninu ọrọ to fi sita loju opo Twitter sọ pe ohun iwuri lo jẹ ti ikọ naa si ṣe afihan ifarajin ati ọkan akin eleyi ti a mọ Naijiria si. O ni gbogbo ọmọ Naijiria lo n reti ki wọn gbe ife ẹyẹ AFCON wa si ile. Yatọ si ikini ti aarẹ, awọn ọmọ Naijiria naa n gbe oṣuba kare fun ikọ Super Eagles. Ninu ọrọ wọn, wọn kan sara si agbabọọlu Naijiria Chukwueze to fakọyọ ninu ifẹsẹwọnsẹ naa. Pẹlu abajade yii, Naijiria ti tẹsiwaju lati kopa ninu abala to kangun si aṣekagba idije AFCON 2019. Ọkan ninu Algeria tabi Ivory Coast ni wọn yoo ba pade ninu ifẹsẹwọnsẹ ti yoo waye lọjọ kẹrinla oṣu yii.",0,yoruba Eni bi ahun lo n ri ahun he #yoruba #proverb,0,yoruba "Ẹre naa ma n de ọdọ awọn eeyan to le ni miliọnu mẹrin Awọn ere ọhun ni wọn n ṣẹ pẹlu ajọṣẹpọ ajọ kan ti kii ṣe ti ijọba, ti orukẹ rẹ n jẹ ""WaterAid"" fun ọdun kan ati abọ. Ọmọ ati iya wa lara awọn to n ṣe erer naa Ayaworan kan, Elena Heatherwick lo n kọ itan naa, ti ileesẹ igbohunsafẹfẹ si ma fi sita fun eti igbọ awọn eeyan. Ọdọmọde yii n tẹti si ẹgbọn rẹ to n kopa ninu ere naa lori redio Ilẹ Rwanda lo kọkọ kede ofin konile-o-gbele nilẹ Afrika lẹyin ti arun ọhun rapala wọn orilẹ-ede naa lọjọ kejilelogun, oṣu kẹta ọdun 2020. Awọn oṣere naa ma n ba ara wọn sọrọ ki wọn to bọ soju ọgbagadi Awọn onwoye ọrọ to n lọ ti sọ pe ere ori redio ọhun n ko ipa to pọ ninu didẹkun arun naa nilẹ ọhun. Evode ni yii, to jẹ ọmọ ogun ọdun, rengba rẹ ni lati jẹ gbajumọ oṣere Redio jẹ ọna kan gboogi lati ṣe ikede lorilẹ-ede Rwanda niwọn igba ti eeyan kan ninu mẹrin ko lee kawe nilẹ ọhun. Solongo niyii, ọdọ iya rẹ lo n gbe ni iha Ila-oorun Rwanda Ere naa ma n de ọdọ miliọnu mrin eeyan o kere tan, eyi to jẹ ida mẹta awọn eeyan to wea lorilẹ-ede ọhun. Sandrine niyii, o ni inu oun ma n dun ti oun gba ti n tẹti si ara oun lori redio Emmanuel, ọmọ ọdun mẹtadinlogun Solonge, Emelthe ati Danny n tẹti si ere naa lori redio Wọn da aṣọ bo irinṣẹ ti wọn fi ka ere kalẹ nitori ojo",0,yoruba "Ẹ o pe ki wa ni? Ẹfa, ookan, aarun, 615 ni nọmba tuntun ti ijọba ipinlẹ Ọyọ nipasẹ ajọṣepọ pẹlu ajọ ibaraẹnisọrọ, NCC gbe kalẹ fun araalu lati maa pe lai ni kete ti wọn ba kọlu ipenija abo ninu irinajo wọn. Intersextuality: Dokita ni ká mu èyì tó wù wá nínú jíjẹ́ akọ tàbí abo Gomina ipinlẹ Ọyọ, Ṣeyi Makinde ṣalaye pe nọmba naa ni nọmba fun idaabobo araalu ti wọn yoo ma lo nibẹ. Nigba to n sọ bi nọmba naa yoo ṣe maa ṣiṣẹ, Gomina Seyi Makinde ni awọn olugbe ipinlẹ Ọyọ to ba n dojukọ ipenija aabo bi idigunjale, rogbodiyan, ijamba ina jijo, tabi awọn ijamba miran lee pe fun iranwọ ajọ gbogbo to ba yẹ ni kiakia. Gẹgẹ bi o ṣe ṣalaye, lasiko ti awọn aṣoju ileeṣẹ ibaraẹnisọrọ NCC wa ṣe abẹwo si oun ni ọfiisi gomina to wa ni Agodi nilu Ibadan loṣu Kẹjọ ọdun 2019 ni wọn jiroro lori agbekalẹ nọmba naa.",0,yoruba "Ọjọ kẹẹgbọn, oṣu Karun-n, ọdun 2020 ni wọn pa George Floyd Lẹyin awọn ifẹhonuhan to tẹle iku okunrin naa, oriṣiriṣi awọn atunto ni ile igbimọ aṣofin Amẹrika ti ṣe kí ayipada rere le ba ileeṣẹ ọlọpaa. Ṣugbọn ṣe awọn atunto yìí, idanilẹkọọ ati ìmọ ẹrọ lè mú ayipada rere ba ileeṣẹ ọlọpaa Amẹrika bi? Ni báyìí tí igbẹjọ Derek Chauvin ti wọn fẹsun kan pe o tẹ George Floyd lọrun pa yóò bẹrẹ, a ṣe àgbéyẹ̀wò bi iwọde, ẹrọ ayàwòrán ati imọ ẹrọ ṣe ni ipa sí ninu oju tí àwọn ọlọpaa alawọ funfun fi n wo awọn eeyan dúdú l'Amẹrika. Idanilẹkọọ ojuṣaju Mimu ayipipada ba eto idanilẹkọọ awọn ọlọpaa ni ipa ti yoo ko Idanilẹkọọ yìí jẹ eyiti wọn fi n wo awọn agbofinro nipa ojú tí wọn fi n wo èèyàn kí wọn tó gbé ìgbésẹ̀ ti wọn n gbe. Iwadii ijinlẹ kan ti wọn ṣe nílùú Philadelphia fi hàn pé, awọn ọlọpaa yinbọn lu èèyàn mọkandinlọgbọn ti wọn gbagbọ pe wọn ni ibọn lọwọ, marundinlọgbọn ninu awọn èèyàn náà ló jẹ alawọ dúdú. Iwadii náà fi hàn gbangba pé ọpọ àwọn ọlọpaa lo n ri awọn alawọ dúdú bíi oni jagidijagan. Iwọde waye lati polongo pe ẹmi awọn alawọ dudu ṣe iyebiye Iru idanilẹkọọ lórí ojuṣaju bayii ti wa láwọn ileeṣẹ nla, ṣugbọn ṣe o n so eso rere? Ìwádìí kan ti Ọjọgbọn Robin Engel láti fásitì Cincinnati ṣe nílùú New York fi han pe idanilẹkọ náà kò so eso rere. Ìwádìí miran ti wọn ṣe láwọn ileeṣẹ ọlọpaa lagbegbe New York fi hàn pé ẹkọ naa ko ni ipa kankan lara awọn agbofinro ọhun. Ọjọgbọn Engel ni ""ko si iyatọ kankan ninu bi wọn ṣe n wuwa si."" Ẹ̀rọ ayàwòrán tí wọn n so mọ ara àwọn ọlọpaa Ni bayii, ileeṣẹ ọlọpaa ti n pin ẹrọ ayaworan ti wọn n so mọ ara fun awọn oṣiṣẹ rẹ Ẹrọ náà máa n ya aworan ìṣesí awọn ọlọpaa lẹnu iṣẹ, to fi mọ ohun ti wọn n ri ati ohun ti wọn n so ni gbogbo igba lẹnu iṣẹ. Ọjọgbọn Engel sọ pé àwọn ẹrọ ayàwòrán náà n ṣiṣẹ, ṣugbọn o fi kun pe o ni ipa ninu bi wọn ṣe n ṣe iṣẹ lára àwọn ọlọ́pàá kan, nigba ti ko ni ipa kankan lára awọn ẹlomiran. Ẹwẹ, onimọ nípa ètò iṣiro ni fásitì Amherst, to wa ni Massachusetts, Travis Campbell sọ pé, lẹyìn ifẹhonuhan Black Lives Matter to bẹrẹ lọdun 2014, adinku ti dé bá bi awọn ọlọpaa ṣe n pa awọn eeyan dúdú láwọn agbegbe kan. O ni ìwádìí fi hàn pé adinku dé bá bi awọn ọlọpaa ṣe n pa awọn alawọ dúdú leyin oríṣiríṣi iwọde to n wáyé lórí bí awọn ọlọpaa ṣe n pa awọn alawọ dúdú. Campbell sọ pe iyatọ gedegbe lo wa laarin awọn agbegbe ti awọn eeyan ti n ṣe iwọde lòdì sí ipaniyan awọn eeyan atawọn ibi ti kò sí iwọde tabi ti iwọde wọn kò lamilaaka to. Campbell pari iwadii rẹ pé ohun mẹta lo mu ayipada bá bí àwọn ọlọpaa ṣe n ṣiṣẹ sí l'Amẹrika. Akọkọ ni akitiyan awọn ọlọpaa ọhun lati tu ọmọluabi wọn ṣe. Ìkejì ni bi awọn eeyan ìlú ko ṣe ni ìgbàgbọ nínú àwọn ọlọpaa mọ. Ẹkẹta ni bi awọn adari ileeṣẹ ọlọpaa ko ṣe gbaruku ti iṣẹ náà. Lẹyin naa lo sọ pé afojusun awọn awọn ifẹhonuhan to n wáyé káàkiri l'Amẹrika ni bi awọn ọlọpaa yóò ṣe máa ṣiṣẹ wọn bí ọmọluabi, ṣugbọn àṣejù rẹ lè mú kí adinku dé bá ìgbàgbọ àwọn èèyàn ọhun ninu awọn ọlọpaa.",0,yoruba "gbé lọ yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.",0,yoruba wúlò. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Alàji lo ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.,0,yoruba "Wọ́n wọ́ àwọn àgbàlagbà mẹ́rin wọ̀nyí jáde síta ilée wọn , àwọn ọkùnrin tí ó bòjú sì fi igi lù wọ́n títí tí ẹ̀mí fi bọ́ lára wọn .",0,yoruba "Babaláwo ní tòun ti àwọn ọmọ rẹ̀ l'ó ní láti ṣe ẹbọ náà. Alábahun gbọ́ rírú ẹbọ, ó kó gbogbo mọ̀lẹ́bí rẹ̀ wá fún ètò. #Yoruba #Ajapa",0,yoruba "Ọ̀ọ̀ni bá Buhari sọ̀rọ̀ lórí dídá iṣẹ́ sílẹ̀ fáwọn ọ̀dọ́ Nipade ọhun to waye nile aarẹ, Aso rock nilu Abuja ni Ọọni ti mu agba oludokoowo kan, Sharif Ahmad Bin Zuhir Bin Mohammad Bin Jaber Al Natour sodi lati jiroro lori idokoowo. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ni ọjọ Aje ni Ọọni Adeyẹye Ogunwusi tọwọ bọ iwe adehun pẹ̀lú àjọ kan láti ilẹ̀ Arab ti Sharif Ahmad Bin Zuhir Bin Mohammad Bin Jaber Al Natour n dari láti dá Iléesẹ́ ohun ọ̀gbín àti ọ̀sìn nílẹ̀ Ìfẹ́. Gẹgẹ bii atẹjade kan lati aafin Oodua ṣe sọ, ipade naa yoo da lori ajọṣepọ to lee waye laarin ileeṣẹ naa ati ijọba apapọ fun idaṣẹsilẹ fun awọn ọdọ, idagbasoke ati ironilagbara. Bọde George: Àwọn èèyàn mọ ẹni to yìnbọn pa Adeniyi Aboriṣade Wọ́n rò pé mo ya wèrè ni Saudi lẹ́yìn ikú ọkọ mi 'Mi o fẹẹkan ni mo fẹ dupo aarẹ'",0,yoruba ti wa ni àbá èwe ni nfàn ojú kakaaki.,0,yoruba Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó ṣe pàtàkì. (Item 43),0,yoruba "ọ̀pọ́lọ̀ ni ìbàdandun àtọ́wọ́dá, àwọn oníṣẹ́ ìṣẹ́ ni ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Nitori eyi, ara eni ni nfàn ojú kakaaki.",0,yoruba ìbàdandun láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa aráyé: ti o ní wúlò.,0,yoruba Ṣé o da ara à rẹ lójú bí ọṣẹ? Gba #ibeere mẹ́rindínlógún kí o gba owó ìpè 200 náírà. #Yoruba,0,yoruba "RT @user: @user Bo pe, bo ya esan nbo wa ke fun awon ojelu jegudu jera. E ni gbebu ika laiye, omo won je awon na aje pelu.",0,yoruba wey ti o nuni ti o nuni ti o nuni ti o ṣe pataki.,0,yoruba "APC ni asiko to lati fopin si ijọba PDP ni ipinlẹ Ekiti Ní ibi àyẹyẹ ọ̀hún, ọ̀jọ̀gbọ́n Osinbajo rọ gbogbo àwọn ọmọ bíbí ìpínlẹ̀ Ekìtì láti lé ẹgbẹ́ òṣèlú People's Democratic Party (PDP) kúrò ní ìjọba. Ó ní àsìkò ti tó, láti dá Òmòwé John Kayode Fayemi pada sórí àléfà láti jẹ̀gbádùn ètò ìjọba àwá-ara-wa. Ìgbákejì ààrẹ ní àsìkò ìnirá ti dópin nípínlẹ̀ Ekiti, tí Fayemi bá gbà ìjọba. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọ̀pọ̀ àwọn gómìnà lábẹ́ àsíá ẹgbẹ́ òsèlú APC, aìmọye àwọn àgbàgbà ẹgbẹ́, àti àwọn Minisita ló kọ́wọ̀ọ́rìn pèlú igbákejì ààrẹ. Lara wọn la ti ri asaaju ẹgbẹ APC< Asiwaju Bọla Ahmed Tinubu ati alaga ẹgbẹ oselu APC lorilẹ-ede yii, John Odigie Oyegun. Ẹ̀wẹ̀, kí igbákejì ààrẹ tó kúrò ní Abùjá, lo tí gbàlejò àwọn asojú ilé iṣẹ́ láti orílẹ̀èdè Germany, fún ìjíròrò lórí ètò ọrọ̀ ajé àti okoòwò.",0,yoruba ìdílé. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìwà: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọmọ lo aye àìlẹ̀.,0,yoruba "Bákan náà, apẹja, àwòràwọ̀ àti ẹnikẹ́ni tí ò bá fẹ́ ta àtamátàsé gbọdọ̀ fi fún Òṣóòsì. #Yoruba #Isese",0,yoruba "Dare Adeboye, #PDee àti #NotTodaySatan, I'm not leaving God: Ẹ wo bí Leke Adeboye, àwọn ọ̀dọ́ ìjọ RCCG ṣe gẹ irun wọn láti bú ọlá fún olóògbé Dare Adeboye",0,yoruba "INEC yoo sun miliọnu meje kaadi idibo Alaga ajọ naa ni ipinlẹ Ondo, Ọmọwe Rufus Akẹju lo kọkọ ṣ'alaye ọrọ yii fun awọn oniroyin nilu Akurẹ ki Kọmisọna apapọ fun eto idanilẹkọ ati ipolongo lajọ Inec, Ọgbẹni Deji Shoyebi to fidi rẹ mulẹ fun BBC wi pe igbesẹ yii ti di dandan ki o too di akoko ibo apapọ ti o nbọ. Awọn ẹgbẹ oselu ni ki ajọ INEC o ma se e ni warawara Ọgbẹni Shoyebi ni ajọ Inec ko tii sọ igba kan ni pato ti yoo wa nkan se si awọn kaadi naa. ""A o sọ wi pe a maa sun un nina naa bẹyẹn ṣugbọn o yẹ ki ẹ mọ wi pe a ko lee tọju awọn kaadi yẹn lai wa nkan ti a maa se si wọn. ""Wọn ti n lo ọdun mẹta, ọdun mẹrin lọ lai si nkan ti a maa se si wọn. ""To ba ya ti a ko ba ri awọn to maa gba a, a maa wa nkan se si wọn, bo jẹ pe ka da wọn pada si ibi ti wọn ti ṣe e ki wọn tun wọn mọ fun omiran, sugbọn nkan ti a sọ ni wi pe a ko lee tọju awọn kaadi idibo yii pẹ julọ."" Ọgbẹni Soyebi ni o le ni ọgọta miliọnu kaadi idibo ti wọn ti sita ṣugbọn awọn kaadi bii miliọnu meje miran ni wọn ko tii ri eeyan wa gba. Ninu ọrọ ti wọn awọn ẹgbẹ oṣelu ti sọ wi pe ko si ohun to buru ninu igbesẹ ti ajọ naa fẹ gbe ṣugbọn ki wọn ṣee ni pẹsẹpẹsẹ. Awọn ẹgbẹ oselu nilo lati da awọn ọmọ ẹgbẹ wọn lẹkọ lori pataki gbigba kaadi idibo Kini iha ẹgbẹ oṣelu sii? Igbakeji alukoro apapọ fun ẹgbẹ oselu PDP lorilẹede Naijiria, Ọgbẹni Diran Ọdẹyẹmi, ni irufẹ igbesẹ bẹẹ lee waye lẹyin ti ajọ naa ba ti se ipolongo to kuna lori rẹ. INEC yoo dana sun miliọnu meje kaadi idibo ""Ki wọn maa se ni wiriwiri bayẹn sugbọn bi awọn eeyan ko ba wa gba ni ọjọ ti wọn ba fi si, a fọwọ sii ki wọn jo nitori bi wọn ko ba jo awọn kọlọransi lee lo lati fi seru ibo. ẹni ti oju rẹ o si nibẹ ki wọn maa lọ ha le wọn lọwọ. Ki wọn maa lọ haa le awọn ọmọ kekeeke lọwọ lati se eru ibo."" Kọmisọna apapọ fun eto idanilẹkọ ati ipolongo lajọ Inec, Ọgbẹni Adedeji Shoyebi tun salaye wi pe kudiẹ kudiẹ to n waye lori eto iforukọsilẹ oludibo ti o n lọ lọwọ ko se lẹyin bi awọn ẹrọ iforukọsilẹ to wa ni ikawọ ajọ Inec ko se pọ to nitori aisi owo. Iru awọn iroyin ti ẹ le nifẹ si:",0,yoruba Olùwo se. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba ènìyàn a yi yi ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìwà: ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún gbogbo.,0,yoruba àlùfáà. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo.,0,yoruba RT @user: Iṣẹ́ nlá ni o. Báwo ni wọ́n ṣe máa gbọ́n gbogbo omi kúrò báyìí? #sandy #NYC,0,yoruba "Òfin Ẹgbẹ́ Òṣèlú náà ( rè é níbi pẹ̀lú àtúnṣe tí a gbà ní ìmọ̀ràn ) bákan náà di lílò ní ọdún - un 1992 , ó sì ti rí àtúnṣe ní ọ̀pọ̀ ìgbà bíi àtúnṣe ti ọdún - un 2009 .",0,yoruba "Ṣùgbọ́n lópin ssẹ̀ tó ṣẹ̀ṣẹ̀ kógbá wọlé yìí ni ìná jó dórí kókó, nígbà ti ọ̀kan nínú wọn Wumi Toriola bọ́ si ojú pópó ìkíraẹni Instagram láti sọ̀kò ọ̀rọ̀ ránṣẹ́ si ẹni to n bá jà. Ọ̀pọ̀ àwọn olólufẹ àwọn òṣèré méjèèjì yìí ló tí n fúnra láti àsìkò díẹ̀ sẹyin ṣùgbọ́n ti wọn kò le fi idí ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀ ni pàtó pé ìjà wà láàrín wọn. Tóo bá pá lórí, Mílíìkì sóyà àtàwọn ǹkan mẹ́ta yìí leè mú irun rẹ hù padà! Gbogbo ènìyàn lo mọ pé ọ̀rẹ́ kìí y'ọ̀rẹ́ ni Wumi Toriola àti Seyi Edun to jẹ́ ìyàwó Adeniyi Johnson ṣùgbọ́n lásìkò ayẹyẹ ọjọ́ ìbí Seyi Edun, Awọn kan ni Wumi Toriola kọ lati ki Seyi ku ayẹyẹ ọjọ ìbí àti ìgbà yìí si ni wọn ti n bèrè ǹkan to fa èdè àìyedè láàrin wọn. Bákan náà ni Seyi ko ki Wumi Toriola lọ́jọ́ ibi rẹ̀ gẹ́gẹ́ bi wọ́n ṣe máa n ṣe lojú òpó ìkàsíraẹni Instagram. Ṣùgbọ́n lówúrọ̀ ọjọ́ Ẹti ni Wumi Toriola tún bọ́ sọjú òpó instagram rẹ̀ láti sọ pé, ""Bí èèyàn bá ṣe aburú fún ọ, má rẹ́rin ti kò dénú pẹ̀lú irú ẹni bẹ́ẹ̀ bi o bá gáání wọ́n. Jẹ́ kí ó mọ̀ ibi ti ó dúro si, ko si àpọ́nle kankan nínú ìgbé ayé àgàbàgebè"" Lẹ́yìn náà lo fi ọ̀rọ̀ míràn gba lẹ́yìn pé gbogbo ǹkan ni òun le gbà sùgbọ́n ti ọ̀rọ̀ bá ti kan ti ọmọ òun pàápàá jùlọ to ba ti di ọ̀rọ̀ ìjà òun ko le fara dàá, ""Bí ẹ ba ri ẹnikẹ́nì tí ó ní ìkóròrí sí ọmọdé, apànìyàn ni irú ẹni bẹ́ẹ̀, wọ́n le fún ènìyàn ni iwọ jẹ"" Bótilẹ̀ jẹ́ pé, bí àwọn kan ṣe n yín Wumi Toriola bí o ṣe sọ́rọ́ síta, bẹ́ẹ̀ ni àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ míràn sọ fún pé, kò bá ojúmu tó láti má a pé ọmọlakeji rẹ̀ ni àgàn. Ẹ̀wẹ̀, Seyi Edun nítirẹ sọ lójú òpó tirẹ̀ pé, nínú ohun gbogbo kí a ṣáà maa dúpẹ́ ni, nítrori idí èyí ni ọ̀ps àwọn olúlufẹ́ tirẹ̀ bẹ̀rẹ̀ ni ni pẹ̀tu síi lọ́kàn láti kí eti ikún si ohun gbogbo ti Wumi Toriola ń ṣọ Báyìí ni ọ̀rọ̀ ìyànjú tí àwọn olúlùfẹ́ Seyi náà ṣe lọ Títí di àsìkò yìí, àwọn ọ̀rẹ́ méjì yiìí kò tí sàlàyé ǹkan to fa ìdí ìjà wọn",0,yoruba yì í tún ṣe àwọn iṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni.,0,yoruba pa Alàji lo ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba "Ọ̀jọ̀gbọ́n Gideon Òkédayọ tí wọ́n jí gbé lọ́sẹ̀ tó kọjá kú Alaga ẹgbẹ naa ti ẹka ile iwe giga fasiti imọ ẹrọ ti Ipinlẹ Ondo, Dokita Dipo Akomolafe, lo fọrọ naa sita lọjọ Iṣẹgun nilu Okitipupa Iku alumuntu ojiji ti ko sẹni to yẹ mọ nipa eto aabo Naijiria Ọjọgbọn Gideon Okedayọ to jẹ olukọni ni ile iwe giga fasiti imọ ẹrọ ti Ipinlẹ Ondo, lo padanu ẹmi rẹ ninu igbekun awọn ajinigbe. Ọjọ karun un, oṣu karun un, ọdun yii ni iroyin kan pe wọn n wa ọjọgbọn yii ki wọn to gba ipe pe ọdọ awọn ajinigbe lo ti ha si. Iroyin ti a gbọ ni pe wọn ji ọjọgbọn Okedayọ gbe nigba ti o n lọ si Igarra ni ipinlẹ Edo to jẹ ilu rẹ. Alaga ajọ awọn oṣiṣẹ ni fasiti Ondo yii, Temidayo Temola ṣalaye pe lootọ ni ọrọ yii ṣẹlẹ si ibanujẹ gbogbo awọn oṣiṣẹ fasiti naa. Nigba ti BBC kan si alukoro awọn agbofinro ti ẹjọ wiwa ọjọgbọn yii wa ni akata rẹ, o fidiẹ mulẹ pe lootọ ni ọjọgbọn yii ti doloogbe. Alukoro awọn ọlọpaa ni ipinlé Edo, Chidi Nwabuzo, ni nitootọ ni wọn ti ri oku ọjọgbọn yii loju popo lẹyin ti wọn gbẹmi rẹ. Ọjọgbọn Igbasan to jẹ igbakeji adari ile iwe giga fasiti naa ni ọrọ naa kanilaya nigba ti BBC kan sii. O ni oun ibanujẹ pata ni nitori agboole awọn ọjọgbọn ti padanu ọlọpọlọ pipe pẹlu iku ọjọgbọn yii lasiko yii.",0,yoruba "Lẹyin ọdun mejilelogun, olukọni ikọ agbabọọlu Nàìjíríà tẹ́lẹ̀, Bonfere Jo, ṣẹṣẹ gba kọkọrọ ile ti wọ́n fun un Ṣẹgun Ọdẹgbami ṣalaye fun BBC Yoruba pe, lootọ ni ijọba ṣe ileri ẹbun fun awọn elere idaraya, paapaa julọ ti bọọlu aláfẹsẹgba lọpọlọpọ ọdun sẹyin. Ṣugbọn o ni ninu iwoye oun, pupọ awọn ẹbun wọnyii lo ti de ọwọ awọn elere idaraya bẹẹ. Ni ọjọ Iṣẹgun ni ijọba apapọ nipasẹ minisita fun iṣẹ akanṣe, ipese oun amuṣagbara ati ọrọ ileegbe, Babatunde Faṣọla, fun akọnimọọgba ikọ̀ agbabọọlu 'Dream Team' to gba goolu ni idije Olympics l'ọdun 1996, Bonfere Jo, ni kọkọrọ ile ti ijọba ìgbà naa ṣeleri fun un gẹgẹ bii ẹbun nigba naa. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Amọṣa, ninu ọrọ rẹ, Ọgbẹni Ọdẹgbami ni oniruuru nkan lo ṣokunfa bi ọrọ ṣe lọ pẹlu awọn ẹbun ti wọn fun awọn agbabọọlu to pegede lọdun 1996 pupọ eyi to ni kii ṣe ẹbi ijọba. ""Lori ọrọ Jo Bonfere ti ẹ n sọ yii, mi o fi bẹẹ mọ. Ohun ti mo mọ ni pe pupọ awọn ti ọrọ kan ni wọn ti gba ẹbun ile tiwọn lọwọ ijọba. Mi o mọ idi ti tiẹ fi ri bẹẹ. Oniruuru iṣoro lo koju ipese ẹbun ile naa nigbanaa nitori ọtọọtọ ni ibi ti awọn ti ọrọ kan ti fẹ ki ile wọn wa ki o to di pe olori iṣejọba nigbanaa dagbere faye."" O ni ko si ẹni to ṣe ileri ohunkohun fun awọn agbabọọlu saa rẹ ni ọdun 1980, ṣugbọn gbogbo wọn ni wọn ti gba ẹbun ile ti ijọba igba naa fun wọn. ""Ni ọdun 1977, 1978 ati 1980 ko si ẹni to ṣeleri ohunkohun fun awọn elere idaraya o, ẹbun gbogbo ti wọn fun ikọ naa ni wọn ti gba.""",0,yoruba Awon omo Nijeria ni iluOba bu enu ete ba @user Won paruwo Ole! A Gbe wiri mo omo egbe asofin apapo @user Koda itiju nla ba Dino https://t.co/CtKopYuBqX,0,yoruba "Ṣùgbọ́n, àjọ elétò ìlera ní àgbáyé (WHO) ti bẹ àwọn ọmọdé láti má rí ara wọn bí ẹni tí kò lè ní aarun náà. Dókítà Rosena Allin-khan sọ pé aarun náà kì ṣe fún àwọn àgbàlagbà nìkan, tàbí ẹni tí ó ti ní àìsàn lára tẹ́lẹ̀. Ó sọ èyí lẹ́yìn ti ìròyìn jáde pé ọmọ ọdún méjìdínlógún kan tó ti ní àìsàn lára tẹ́lẹ̀ kú nítorí Coronavirus ni ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì. Òun sì ni ẹni tí ó kéré jùlọ ti aarun náà tí pá ní ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì. Dókítà Allin-khan so pé òun ti ṣe itoju àwọn ọ̀dọ́ tí kò ní ààrùn kankan lára tẹ́lẹ̀ ṣúgbọ́n wọ́n wà níbi tí wọn tí n du ẹ̀mí wọn. Ki wá ní è àwọn ewu bí òjò orí bá ṣe ń gòkè sì? O ti hàn gbangba pé àwọn arúgbó lọ fara kasa nínú aarun yìí julo. Àwọn aṣèwádìí ni Imperial College ni London tí wá isopo to wá láàrín bí ó bá ṣe dàgbà sì àti ìdí ti oo fi dé ilé ìwòsàn tí ó bá ní aarun Coronavirus. Ìwádìí nàá fihàn pé àwọn tó dàgbà ló wọ́pọ̀ jùlọ tí yóò dé ilé ìwòsàn nítorí wọn nílò ìtọ́jú tó péye. Coronavirus: Ǹjẹ́ fífi omi àti iyọ̀ yọnu leè dènà àrùn Coronavirus? Ìwádìí fi hàn nínú àwọn tó ni, ní China àti Italy, àwọn orílẹ̀-èdè méjì tí aarun náà bá fà julọ. Bẹ́ ẹ̀ sì ni tó bá jẹ́ ti kí a gbani wọlé sí ẹ̀ka ìtọ́jú tó lágbára jùlọ, ìdá ọgọ́rùn nínú àwọn tó kú ti lé ní ẹni ọdún márùnlélọ́gọ́ta. Bí ààrùn náà ṣe ń kan ọjọ́ orí. Ní Italy, ida 0. 4% ni àwọn tó ti pe ogójì ọdún tó ti kú , tí ìdà 19% sì jẹ́ àwọn tó ti lé ní ọgọ́rin ọdún. Nígbà tí ìdà 0.7% jẹ́ àwọn tó ti pé ogójì ọdún ti kú ní America. Oludari ilé iṣẹ́ tó ń gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn ní America, Anthony Fauci sọ pé iye ènìyàn tí coronavirus ti pa níbẹ̀ jẹ́ nkan tó n bánilọ́kàn jẹ́, tó sì jẹ́ àwọn àgbàlagbà tó ti ní àìsàn tí wọ́n ń tọ́jú tẹ́lẹ̀. Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele Ṣùgbọ́n, ó sọ pé Coronavirus kìí se ìṣirò Maasi. Ajo WHO náà sọ pé bótilẹ̀ jẹ́ pé ẹ̀rí wà pé àwọn tó ti pé ọgọ́ta ọdún ló ti kú ju àwọn ọmọdé lọ, àwọn ọmọdé naa le kú. Ẹni tó ti ní àìsàn lára tẹ́lẹ̀ Àwọn àìsàn tó ti wà nínú àgọ́ ara tẹ́lẹ̀ náà wà lára nkan tó ń sọ ẹni tí yóò kù ú tàbí yè. Fún àpẹẹrẹ, ẹni tó bá ní ààsàn bí ikọ́'fe (Asthma), bóya ọmọdé tàbí àgbàlagbà. Bákan nàá ni àwọn tó bá ní àìsàn ọlọ́jọ́ pípí lára. Bótilẹ̀ jẹ́ pé àwọn tí ọjọ́ orí wọn kéré le má fi àmì hàn, wọ́n le pín kiri láí mọ̀.",0,yoruba àwọn ìkòkò tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba "Àwọn èròjà tí ń mú egun le koko, tí sì ń fún ni lókun àti agbára tí amọ̀ sí Fítámínì lédè èèbó #Yoruba #asala",0,yoruba Ọ̀RỌ̀ ÌṢÍTÍ WA T'ÒNÍ: Ẹ MÁ JẸ́KÍ OKÙN ẸBÍ TI ỌWỌ́ Ọ WA JÁ! (Our admonition for today: Don't destroy your family ties/relationship) #yoruba #oroisiti #ebi #yorubaadmonition #artsandculture #akomolede #linguistics… https://t.co/UPLBNFsGet,0,yoruba "Irú ìyá àgbà àti àwọn ìyá , gẹ́gẹ́ bíi Ìyá àgbà Saray ti ń ṣakitiyan ìpamọ́ àwọn ìṣe orílẹ̀ wa àti ẹ̀mí - àìrí fún àìní ye ọgọ́rùn - ún ọdún .",0,yoruba Kelechi Iheanacho ẹlẹ́sẹ̀ ayò tún ti dábírà fún Leicester City,0,yoruba "Idris ko ba awọn oniroyin s'ọrọ lẹyin ipade rẹ pẹlu aarẹ Ni bayi, o ni Federal Special Anti Robbery Squad(FSARS) ni SARS yoo maa jẹ. Bakanna lo ni gbogbo ẹka SARS teleri ri to wa labẹ ti bọ si abe FSARS pẹlu iyipada tuntun yi. Eyi nikan kọ, Kọmiṣọna ọlọpàá kan ni yoo maa dari ajọ naa bayii, yoo si maa jẹ abọ fun ẹka ileeṣẹ olopaa ni Abuja to n ri si iwa ọdaran. Sugbọn awọn ọmọ Naijiria ti n se eemọ lori igbese yi. Ni oju opo Twitter ibeere ti awọn eeyan n bere ni pe kini iyato to wa laarin SARS ati FSARS ati wipe ṣebi FSARS lorukọ ti wọn ti n jẹ latilẹ tẹlẹ ri? Lọjọ isẹgun ni agbẹnusọ fún adele Ààrẹ, Laolu Akande, fi ọrọ síta loju opo Twitter pé Adele Aarẹ Yemi Osinbajo ti pasẹ fun ọgá ọlọpaa lati se atunto SARS. Osinbajo so wí pé ọmọ tuntun ti atunto SARS yoo bí gbọdọ máa ṣíṣe lọnà to tọ ati eyi to yẹ. gbọdọ kojú mọ iṣẹ ti wọn gbe kale fun un ti ṣe didẹkun iwa adigunjale àti ìwà ajinigbe tó fí mọ mímú àwọn tí wọn hù ìwà tó jẹ mọ àwọn ẹṣẹ wọn yí. Adele Ààrẹ Osinbajo tẹsíwájú pé o di dandan ki àwọn oṣiṣẹ SARS ni àmì idanimo lara wọn ní gbogbo ìgbà tí wọn bá n ṣíṣe wọn. Ti a kò bá gbàgbé oríṣiríṣi iriri lo tí n waye lati ọdọ ara ìlú nípa ìhùwàsí àwọn oṣiṣẹ SARS Ẹsun iseku pa awọn ọmọ Naijiria nipakupa jẹ ọrọ ti awọn ọmọ Naijiria ko le mẹnu kuro nibẹ lati bii oṣu meloo kan. Tóun tí bí ẹnu ti ṣe n kun wọn,ilé iṣẹ ọlọpa lorílè-èdè Nàìjíríà ni awon kò ri ìdí tí wọn yóò fi kagba Sars wọlé Bo tilẹ jẹ pe awọn yoo gbe igbeṣẹ lati ri pe wọn ṣe atunto ẹka SARS naa. ọ̀gá ọlọ́pàá sọ̀rọ̀ lórí SARS SARS ti bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ láti yọ àwọn ọ̀bàyéjẹ́ kúro Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:",0,yoruba àgbà ri pe jẹ́ pàtàkì wey ti o jare.,0,yoruba bbc news yorùbá | shonekan mọ̀lẹ́bí olórí nàìjíríà nígbà kan rí ní kokoko lara rẹ̀ ẹ́ le,0,yoruba "Lọ̀sẹ̀ yìí ni isẹ̀lẹ̀ míì tún sẹ̀ ní ìlú London tí ọ̀rọ̀ yìí sì ń kọ ìjọba orílẹ̀èdè Nàìjíríà lóminú. Látàrí èyí, olùgbaninímọ̀ràn àgbà fún ààrẹ lórí ọ̀rọ̀ ilẹ̀ òkèrè, Àbíkẹ́ Dábírí-Erewà gba àwọn ọmọ Nàìjíríà nímọ̀ràn láti sọ́ra kí wọ́n sì kó ara wọn níjanu ìwà ipá. Nínú ọ̀rọ̀ kan tí olùrànlọ́wọ́ rẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ ìròyìn Abdur-rahman Balógun sọ ní ọjọ́ ajé ní ìlú Abuja, Àbíkẹ́ ní bí pípa àwọn ọmọ Nàìjíríà lókè òkun se ń peléke síi pàápàá àwọn tó wà ní ìlú London ńdá ìpòruru ọkàn sílẹ̀. Wọ́n fi ìròyìn sọwọ́ wípé ó lé ní àádọ́ta ènìyàn aláwọ̀dúdú pàápàá jùlọ àwọn ọ̀dọ́ tó jẹ́ wípé yálà wọ́n gún lọ́bẹ tàbí yìinbọn bá ní sáà kínní ọdún 2018 ní ìlú London nìkan. Lára àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin ọmọ Nàìjíríà tí wọ́n ti pa báyìí ní ìlú òyìnbó ní sáà kínní ọdún 2018 pàápàá ní ìlú London nìkan ni Olúwadámilọ́lá Ọdẹ́yingbó (ọmọ ọdún méjìdínlógún), Taofeek Làmídí (ọmọ ogún ọdún) àti Harry Uzoka (ọmọ ọdún márùndínlọ́gbọ̀n). Àwọn míì ni Rótìmí Ọ̀sínbàjò (ọmọ ọdún mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n), Fola Odubiyi (ọmọ ọdún méjìdínlógún), Níyì Shode (ọmọ ọdún mẹ́rìnlélógún), Kelvin Odunuyi (ọmọ ọdún mọ́kàndínlógún), Abraham Badru (ọmọ ọdún mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n), Israel Ogunsola (ọmọ ọdún méjìdínlógún) àti àwọn isẹ̀lẹ̀ míì tí wọn kò fi sọwọ́. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:",0,yoruba yi da ti o nuni ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba ojú onà.. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba "Àwọn asofin tí kọ̀ láti jòkó ní ilé lẹ́yìn tí Ààrẹ Buhari pinnu láti wá sàlàyé ètò ìsúná ọdun 2019 fún wọn ní ọ̀sẹ̀ tó ń bọ̀. Ipinnu awọn asofin yii ko sẹyin bii wọn se fẹsun kan minisita fun ọrọ isuna, sẹnetọ Udo Udoma wi pe o bu ẹnu atẹ lu wọn. Iroyin ni minisita naa sọ pe awọn asofin n se segesege nitori wọn kọ lati fun ile isẹ ijọba ni ọjọ ti wọn yoo wa sọ nipa eto isuna fun ọdun 2019. Lẹyin ọpọlọpọ awuyewuye abẹnugan ile asofin, Họnọrabu Yakubu Dogara wa parọwa si awọn asofin wi pe ti minisita naa ba kọ lati tọrọ àforíjì ki o to di Ọjọ Isẹgun, ọsẹ to n bọ ni awọn yoo gbe igbese lori ọrọ naa. Ni Ọjọ Isẹgun ọsẹ yii ni Aarẹ Muhammadu Buhari ni Ọjọru, ọsẹ to n bọ ni oun yoo wa salaye bii eto isuna ọdun 2019 yoo se ri.",0,yoruba iyalẹnu wey ti o nuni ti o nuni ti o lẹ.,0,yoruba "Èyí kò rí bí ajàfẹ́tọ̀ọ́ AL náà ti ṣe wí , kò sí ohun tó jọ ọ́ , kò sí àṣẹ tí ó ní kí wọ́n tà tàbí wó ilé tí à ń sọ̀rọ̀ọ rẹ̀ yìí .",0,yoruba òní.. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìwà: ti o ní wúlò fún gbogbo.,0,yoruba "Àgbàlagbà bẹ́ sílẹ̀ láti orí àjà kárùn-ún ní University College Hospital nilu Ibadan Ìròyìn fi tó wà létí pé ọkùnrin náà bẹ́ silẹ láti orí òkè alaja márùn-ún nínú ilé ìwòsàn náà. Agbenuso fún àjọ ọlọ́pàá ni Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Ayodeji Bọbade,tó bá akoroyin BBC Yoruba sọ̀rọ̀ fìdí ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Orí òkè tí ọkùnrin náà ti bẹ́ sílẹ̀, bàtà rẹ̀, ìwé àkọsílẹ̀ ikú àti owo rẹ̀ ni wọn rí Bàtà ti olóògbé bọ sílẹ̀ Ayẹwo fi hàn pé ọkùnrin náà kò ìwé ikú sapo kí ó tó yọ́ gùn orí òkè tó ti bẹ́ sì ìsàlẹ̀.",0,yoruba "àkerekere, Baàlè ri Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba RT @user: Ife la'koja ofin #TweetYoruba,0,yoruba iṣẹ́ ṣẹlẹ ni Lagos ti gbogbo eniyan sọ o dara. (2011),0,yoruba "@user Ẹkú ọjọ́ ìbí o! Àṣèyí ṣàmọ́dún. Àkàlàmàgbò kìí p'ọdún jẹ. Bẹ́ẹ̀ni iná táa dá fún igún, ẹyẹ míì la fi nsunjẹ. Ẹ̀ẹ́ dàgbà darúgbó o!",0,yoruba 8.Eré ọmọdé wo ni a ti ń ká ọwọ́ báyìí? #ibeere #Yoruba https://t.co/OTselcUmM6,0,yoruba Ọ̀pọ̀ ní ẹnì kan tí ò sí nínú ikọ̀ọ wa fún #worldcup yóò fa ìfàsẹ́yìn fún wa. Ṣé òtítọ́ lèyí? @user #Idanoripapa http://t.co/TRQ4vtw1ZL,0,yoruba òun tí a ní nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ àti ìbi tí wọn wà.,0,yoruba @user Mo nife ee #yoruba,0,yoruba "Rọra ṣe o, rọra ṣe. Ọmọ ẹ̀mí rọra ma ṣe ... """""""" @user gbe orin tuntun - Iṣẹ́ Òru #Vigil jáde http://t.co/NkfJ5xjfzg""""""""",0,yoruba kí èèbó tóó dé onírúurú iṣẹ́ ni àwọn bàbá wa ńṣe tí wọ́n fi gbe ìgbe ayé rere,0,yoruba pa Ọba lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ àti ìbi tí wọn wà.,0,yoruba "Àrà kengé! Egbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà sàn N5,000 láti rà agbábọ́ọ̀lù tó n gbowó julọ Idi ni pe atamatase ti ẹ n wo yi ni agbabọọlu ti wọn n san owo julọ fun ni ilu rẹ. Bẹẹni, ko si ẹni to n gba owo to to Ibrahim Salisu Iriyos ni Gano, ijọba ibilẹ Dawakin Kudu ni ipinlẹ Kano, ninu awọn agbabọọlu to wa nibẹ. Koda, ni akọsilẹ ere bọọlu lorile-ede Naijiria, oun ni akọkọ agbabọọlu ti wọn yoo san owo tabua fun ni ilu rẹ. Ẹ fẹ mọ iye to gba abi, lalai deena pẹnu, Ibrahim Salisu Iriyos gba ẹgbẹrun marun un Naira gẹgẹ bi agbabọọlu ti o gba owo julọ fun ẹgbẹ Super Stars. Lọwọ ẹgbẹ Aston Villa Gano ni Super Stars ti ra Salisu Iriyos lati ipele liigi keji ni iye owo ẹgbẹrun marun un. Atamataṣe naa to jẹ goolu pupọ fẹgbẹ rẹ fifẹ han si pe oun fẹ ṣoju ẹgbẹ to wa ni ipele ikini. Koda, o dara pọ mọ ikọ Super Stars lasiko tawọn akẹgbẹ rẹ n sinmi, ti o si mu ki wọn mọ wi pe ẹlẹsẹ ayo ni Salisu. Idin Gano ni orukọ alaga ẹgbẹ Gano, oun si lo lewaju idunadura pẹlu akọnimọọgba Aston Villa Abba Alasan Super Stars ti wọn fi gba lati san owo naa fun Salisu.",0,yoruba Bi omode o ba ba itan a ba aroba. Aroba ni baba itan.. #yoruba #Proverbs #Nigeria https://t.co/CmrHRinrTs,0,yoruba wúlò. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ẹkọ́: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba "Ìlẹ̀ Ọ̀yọ́ jẹ́ ilẹ̀ agbègbè tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba tipa tikuuku oluwa mu mi lo se rere oya lets go happy easter everybody,0,yoruba "tí Ọmọ fè lọ, Nitori eyi, ara eni lo ni ìgbà mi owó àkokò, Ìyá lo aye àìlẹ̀.",0,yoruba "kún jú, àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó ga.",0,yoruba "Sidiz sisọ loju ọrọ yii nigba to n ba BBC sọrọ lasiko ifẹhọnu han wọn ni olu ileese Fidelity Bank to wa ni ipinlẹ Eko. O sọ wi pe lẹyin ifẹhọnu han awọn lori aisan owo ajẹmọnu wọn ni ọdun to kọja, ni wọn yọ awọn ni isẹ bi ẹni yọ jiga, laisan owo ajẹmọnu wọn. Osisẹ ile ifowopamọsi naa wa rọ adari agba ileese naa, lati yẹ ọrọ yi wo, nitori iya n jẹ awọn ọmọ wọn, ati ẹbi ati ara wọn. Ọsẹ to kọja ni awọn osisẹ ile ifowopamọsi, Fidelity Bank se ifẹhọnu han lori aisan owo osu wọn fun osu mẹwa bayii. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Banki Fidelity naa fesi lori ifẹhonu han awọn osisẹ yii Wayi o, Adari eto ibanisọrọ fun ileesẹ Fidelity Bank, Charles Aigbe, nigba to n fesi si ẹsun naa, salaye pe awọn osisẹ to n fẹhọnu han naa, kii se osisẹ awọn, ati wi pe awọn ko jẹ osisẹ awọn kankan ni owo osu. Charles fikun wi pe, awọn yoo gbẹ ẹsun naa lọ si ile ẹjọ ki ọrọ naa ba lee ni ọna abayọ to ba ofin mu.",0,yoruba olùparapọ̀ ri pe nilo ayẹwo wey ti o ní wúlò.,0,yoruba ìgbín ò lè sáré bí ajá ìyẹn ò ní kó máà de ibi tó ńlọ the snail cannot run as fast as the dog tha,0,yoruba yii nípa àbá èwe lo je ti ibile.,0,yoruba àkóbì asin. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba Ki ni itumo Ewuro ni Oyinbo? See answer at: https://t.co/TbZi7d3nMc #yoruba #english #nigeria #usa #uk #lagos #abuja #vegetables #plants,0,yoruba se joko. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ài: ti o ní wúlò.,0,yoruba "RT @user: Esu Dance Staff (Ogo Elegbara), Yoruba, 1825 https://t.co/yiZea9O1F3 #africanart #yoruba https://t.co/IlM9OVkH4n",0,yoruba 'Se idagbasoke Alaafia' #Yoruba #BuildPeace https://t.co/xzfYXDxnL3,0,yoruba "O ni bo tilẹ jẹ wi pe awọn ileeṣẹ agbofinro sa ipa wọn, sibẹ, omi pọ ju ọka lọ nitori ọkan lara awọn adari ẹya Yoruba, Reuben Faṣọranti naa padanu ọmọ rẹ sinu laasigbo to n ba ilẹ Yoruba finra ọhun. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Fayẹmi tẹsiwaju wi pe, eyii lo ta awọn gomina ilẹ Yoruba nidi kan lati pe ipade pajawiri lori eto aabo ilẹ Yoruba ni bii oṣu mẹfa sẹyin, abajade apero naa si ni Amọtẹkun ti wọn n ṣiṣọ loju ẹ lonii. O ni Amọtẹkun ko waye lati rọpo awọn ileeṣẹ aabo to n bẹ nilẹ tẹlẹ, ṣugbọn yoo ṣiṣẹ papọ pẹlu awọn ẹṣọ aabo to ku, ki eto naa le kẹsẹjari. O ṣe afikun ọrọ wi pe, gbogbo awọn aṣoju Amọtẹkun ni yoo maa ṣe amojuto awọn agbegbe kọọkan pẹlu oye ede ati aṣa awọn agbegbe naa. Fayẹmi ṣe alaye wi pe, Amọtẹkun ipinlẹ kọọkan ni yoo maa mojuto ipinlẹ ti wọn pin wọn si lai rekọja lọ si ipinlẹ mii, ayafi ti iṣẹlẹ pajawiri ba waye. Igbakẹji gomina Ipinlẹ Ọṣun, Gboyega Alabi to soju gomina Gboyega Oyetola nibi akanṣe eto naa ni, agbekalẹ Amọtẹkun jẹ ojuṣe awọn gomina nitori ikawọ wọn ni aabo ẹmi ati dukia awọn eeyan ilu wa. O dupẹ lọwọ ileeṣẹ ologun ati awọn agbofinro to ku, fun bi wọn ṣe ji giri si ojuṣe wọn lasiko ti ipenija eto bẹrẹ ni ẹkun iwọ oorun Naijiria. O wa parọwa si awọn aṣoju Amọtẹkun lati ṣiṣẹ wọn pẹlu otitọ inu pẹlu alaye wi pe, ijọba ipinlẹ Ọṣun ti ya ikorita Ọlajokun silẹ ni opopona maroṣẹ Gbọngan, ti yoo maa jẹ olu ileeṣẹ Amọtẹkun nipinlẹ Ọṣun. Ninu ọrọ ti ẹ, gomina ipinlẹ Ondo ti o tun jẹ alaga agbarijọpọ awọn gomina ilẹ Yoruba, Rotimi Akeredolu ni ifilọlẹ Amọtẹkun jẹ nnkan ayọ fun gbogbo awọn gomina ẹkun iwọ oorun guusu Naijiria. O ni eto aabo ilẹ Yoruba ṣe pataki si awọn gomina naa, eyi lo si ṣe atiwaye ifilọlẹ Amọtẹkun. Akeredolu ni ko si ipinlẹ kankan ti o bọriyọ lọwọ awọn ipenija eto aabo lorilẹede yii, eyii lo si mu ki awọn ọmọ orilẹede yii to n bẹ loke okun maa bẹru lati wa si ilẹ baba wọn. Gomina ipinlẹ Ondo tẹsiwaju wi pe, agbekalẹ Amọtẹkun yoo mu opin de ba wahala awọn adigunjale, darandaran ati ijinigbe. O ni awọn gomina ilẹ Oodua ko ni tẹti ninu ojuṣe wọn titi ti ipenija eto aabo yoo fi di ohun igbagbe ni ẹkun iwọ oorun guusu Naijiria, eyii lo si mu ki gbogbo awọn gomina naa fi orikori lati ṣe ifilọlẹ Amọtẹkun. Lẹyin eyi ni gomina ipinlẹ Ondo ti o tun jẹ alaga awọn gomina ilẹ Yoruba, Rotimi Akeredolu ti ṣiṣọ loju awọn ọkọ iwọde fun Amọtẹkun. O ṣe alaye wi pe alupupu bii ọgọrun mii tun wa kaakiri awọn ipinlẹ to n bẹ ni iwọoorun guusu fun iwọde Amọtẹkun. Àsìkò tó fún ilẹ̀ Yorùbá láti dẹ́rù ba ẹ̀rù fúnra rẹ̀ pẹ̀lú Amotekun - Seyi Makinde Lẹ́yin o rẹyin, eto ifilọlẹ Amotekun to yẹ ko ti bẹrẹ lati aago mẹsan aarọ, ti gberasọ bayii, tawọn eeyan jankan-jankan, to fi mọ awọn gomina mẹfẹẹfa nilẹ Yoruba, si ti de sibi eto naa. Bakan naa ni awọ̀n oriade nilẹ́ Yoruba bii Ọ́ọni tilu Ile Ifẹ, Ọba Adeyẹye Ẹnitan Ogunwusi, Olugbọn tile Igbọn ti peju sibi ayẹyẹ naa. Ninu ọrọ ikini kaabọ rẹ, olugbalejo pataki nibi ayẹyẹ ifilọlẹ ọhun, gomina Ṣeyi Makinde ti ipinlẹ Ọyọ ni, asiko ti to fun ilẹ Yooba lati dẹruba ẹru gangan funra rẹ. Makinde tẹsiwaju pe agbẹkale Amọtẹkun waye fun igbaye-gbadun ati eto aabo to nipọn fun gbogbo ọmọ Oodua. O ni gbogbo gomina lo bura lati bọwọ fun ofin nipa ṣiṣe agbekale eto aabo ti yoo rẹsẹwalẹ fun gbogbo awọn araalu. Gomina ipinlẹ Ọyọ fikun pe akanṣe eto yii si jẹ imuṣẹ ileri ti awọn gomina ṣe lasiko iburawọle, pẹlu alaye pe inu oun dun lati jẹ olukopa ninu agbekalẹ eto ti yoo fẹ oju eto aabo ati igbayegbadun awọn eeyan ilu. O tẹsiwaju wi pe, ipinlẹ Ọyọ tun ti gba oye tuntun gẹgẹ bii ipinlẹ ti agbekalẹ eto aabo ẹlẹkunjẹkun akọkọ iru ẹ ti gbinaya. Kí ló ń fa ìdádúró nípa ìfilọ́lẹ̀ 'Amotekun' tó yẹ kò wáyé lónìí? Ifilọlẹ eto aabo alajumọse ti awọn gomina ẹkun iwọ oorun guusu Naijiria se agbatẹru rẹ, ti wọn pe ni ""Amọtẹkun"" ti gbinaya bayii.Agbekalẹ naa waye lati bomirin eto aabo nilẹ Yoruba, paapaa julọ lori ikọlu awọn darandaran to n gogo lẹnu lọọlọ yii.Gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akereolu ti o jẹ alaga awọn gomina ilẹ Yoruba ni ireti wa wi pe yoo ṣi'ṣọ loju eto naa, ti yoo waye lọọfisi gomina nilu Ibadan. Ireti si wa pe gomina Seyi Makinde ni yoo jẹ olugbalejo nibi ayẹyẹ naa. Akọroyin BBC Yoruba to wa nibi ifilọlẹ eto aabo naa fi to wa leti pe, aago mẹsan ni eto naa yẹ ko bẹrẹ, ti wọn si n reti awọn alejo pataki lọwọlọwọ. Awọn ẹṣọ aabo igberiko ati diẹ lara awọn alejo ti wọn fi iwe pe nikan lo wa nikalẹ, ti wọn si ti gbe awọn ọkọ isẹ ti wọn fẹ pin fun awọn osisẹ alaabo kalẹ. Bẹẹ ba gbagbe, ana Ọjọru ni ileeṣẹ aarẹ kesi awọn gomina mẹfẹẹfa to n bẹ nilẹ Yoruba lati wa wi tẹnu wọn lori agbẹkalẹ eto aabo Amọtẹkun naa, amọ titi di akoko yii, a ko tii mọ ohun ti wọn ba bọ lati ileesẹ aarẹ. Iroyin kan to n ja rainrain labẹlẹ ni wi pe, o ṣeeṣe ki ileeṣẹ aarẹ pagidina agbekalẹ eto aabo Amọtẹkun lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria. Ohun mii ti awọn eeyan tun un sọ ni wi pe o ṣeeṣe ki ileeṣẹ aarẹ maa bẹru wi pe, ilẹ Yoruba ti fẹ ya ara wọn kuro ni Naijiria nipasẹ agbekalẹ naa. Àrìnfẹsẹ̀sí - Ìbéèrè ni a bèrè lọ́wọ́ àwọn èèyàn, ika òṣì ni wọ́n ń ta dànù Bi isẹlẹ naa ba se n lọ, a maa mu wa fun yin.",0,yoruba "Oyetola sọrọ yii lasiko to gbalejo awọn agbaagba ẹgbẹ oṣelu SDP to wa ki i ni ile ijoba nilu Osogbo. Oyetọla ni aikun oju iwọn eto idibo orilẹede Naijiria lori yiyan awọn oludije lo fun iru awọn eeyan bi Adeleke lanfani lati dije tako oun. Ẹ jẹ ki a wo bi o ṣe sọọ gan ni ẹkunrẹrẹ: ""Ọpọ igba ti mo ba joko ti mo si ronu lọ sori pe iru Adeleke, to jẹ pe ijo jijo nikan lo ti jafafa, ni mo n ba dije du ipo gomina, ara mi a si bu maṣọ, oju ara mi a si gba mi ti. Ajalu nla nii ba jẹ fun ipinlẹ wa ka ni ọna miran lọrọ yii ba yọ ni."" Barrister ló sọ mí di èèyàn ńlá - Ayinla Kollington Supreme Court : Oyetola fẹ̀yìn Adeleke janlẹ̀ nílé ẹjọ́ tó ga jù lọ! Yinka Ayefele: Oṣù àwọn ìbẹ́ta mi kò pé ní kò jẹ́ kí n kọ́kọ́ kéde ìbí wọn Amoṣa ki ni Sẹnetọ Ademola Adeleke to jẹ oludije ẹgbẹ oṣelu PDP lasiko idibo naa gbọ eyi si, o ni wọn ko gbe ẹnu toun naa fun alagbafọ. Oun pẹlu wa fi gbolohun diẹ ṣọwọ si Gomina Oyetọla pe oun dupẹ toun o pe oun jẹ onijo, ṣugbọn ijo jijo kii ṣe aisan. Koda o tun tẹsiwaju, O ni o san fun oun lati jẹ onijo ki oun si fi ays inu oun han ju ki oun maa ""po ẹkọ ibinujẹ ati wahala faraalu nipa lilu aṣuwọn owo ilu ni ponpo."" Adeleke ni ọpọlọpọ ere lo n bẹ ninu ijo jijo. Nigba ti yoo parí ọrọ rẹ, Sẹnetọ Adeleke ni...""ijo jijo san ju ka lu owo ilu ni ponpo lọ"" Adeleke fọhùn, 'èmi ni gómìnà tí wọ́n dìbò yàn' O wa ranṣẹ ọrọ si Oyetọla pe, ""Jẹ ki n ran Oyetọla leti pe iwe rẹ gẹgẹ bii olori awọn oṣiṣẹ fun Rauf Arẹgbẹṣọla fihan gbangba peko kun oju iwọn gẹgẹ bii alakoso, ṣugbọn o jafafa ninu ka lu owo ilu ni ponpo."" Ọrọ yii ti n ja ranyinranyin laarin awọn ololufẹ igun mejeeji at'awọn onwoye. Bi awọn kan ṣe n wi pe o yẹ ki awon mejeeji o ṣọra pẹlu ọrọ wọn gẹgẹ bíi opomulero ni ipinlẹ naa l'awọn kan n jiyan lori ọrọ mejeeji.",0,yoruba "Aworan CCTV ṣafihan asiko tawọn eeyan n wọ alakoso abule naa nilẹ Bẹẹ lọrọ ri nigba ti bata alakoso ilu kan ni Mexico ro kanla kanla titi tawọn ara ilu rẹ si da sẹria olorombo fun un latọwọ ara wọn. A gbọ pe wọn so o mọ ọkọ ti wọn si wọ ọ nilẹ tuurutu lori titi laarin abule wọn. Eeeyan mejila lawọn agbofinro ti mu lori iṣẹlẹ yii tawọn ọlọpaa si doola ẹmi alakoso abule naa Jorge Luis Escandón Hernández. Igba 'keji ree ti awọn ara ilu yoo doju ija kọ alakoso naa ti wọn si ni ki o mu ileri rẹ ti o ṣe nipa titun oju ọna wọn kan to ti bajẹ ṣe. Koda awọn ọlọpaa ti fi awọn agbofinro mii ranṣẹ si abule naa ni ipinlẹ Chiapas. Lọpọ igba lawọn alakoso ati awọn oloṣelu ma n koju ikọlu lati ọwọ awọn janduku tori pe wọn kọ lati faaye silẹ fun wọn lati ṣẹ iṣẹ aburu wọn. Ṣugbọn ko wọpọ ki awọn ara ilu maa doju ija kọ awọn alaokoso ti ko ba mu ileri wọn ṣẹ. Ọgbẹni Escandón ni oun yoo pe awọn to ji i gbe naa lẹjọ lori ẹsun ijinigbe ati igbiyanju lati gbẹmi oun. Fọnran fidio tawọn eeyan ya lati ṣafihan alakoso ilu naa bi awọn eeyan kan ṣe wọ ọ jade lati inu ọfiisi rẹ ti wọn si ju u sẹyin ọkọ. Fidio naa re e. Fidio miiran ti ẹrọ ayaworan CCTV ka ṣafihan ibi ti wọn ti so o mọ ọkọ ti wọn si n wọ ọ kiri oju ọna Santa Rita to wa lara agbegbe Las Margaritas. Ọgọrọ awọn ọlọpaa lo gbiyanju lati da ọkọ naa duro ki wọn baa le doola ẹmi alakoso ọhun. Awọn eeyan pupọ lo fara pa ninu ikọlu to waye laarin awọn ọlọpaa ati awọn to ji alakoso naa gbe. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ninu iṣẹlẹ kan to waye ni nnkan bi oṣu mẹrin sẹyin, awọn eeyan kan ya bo ọfiisi alakoso naa amọ wọn o ba a nibẹ. Ṣaaju ki wọn to dibo to gbe ọgbẹni Escandón wọlẹ ni wọn mu oun gaan alara tori pe wọn lọ n ba awọn alatako rẹ kan wọ iya ija. Wọn pada tu u silẹ tori pe awọn agbofinro lawọn ko ri ẹri aridaju pe o kopa ninu ikọlu naa.",0,yoruba "A kò ṣègbékalẹ̀ bọ́tìnì %s, kò lè ki aṣàfilọ̀lẹ̀",0,yoruba lọ yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba "ọba lálai. Nitori eyi, ara eni lo je ti ibile.",0,yoruba a ní láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó tó gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ àti ìbi tí wọn wà.,0,yoruba "Olùwo mú. Nitori eyi, ara eni lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìwà: ti o nuni ti o lẹ.",0,yoruba "ni ìgbà mi owó àkokò, Alàji lo ojú odò.",0,yoruba Èkó yii nípa ọ̀ṣun ìlú lo je ti ibile.,0,yoruba "tó kún jú, àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ẹkọ́: ti o nuni ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó tìkẹ́ gblọ yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú.",0,yoruba aaro ati ale,0,yoruba "Bí - ó - ti - wù - kí - ó - rí , Ohùn Àgbáyé kò rí àyè sí àwọn túwíìtì tí ó sọ ìgbésẹ̀ ìpolongo Hashim ní ìjà fún ẹ̀tọ́ LGBTQ .",0,yoruba tí èyàn bá dúdú riri wọn a máa wípé ó dúdú bíi kóró eso wo,0,yoruba Mo kí gbogbo mùsùlùmí jákè jádò àgbáyé kú ọdún Iléyá o. Ẹ̀mí a ṣọ̀pọ̀ rẹ̀ láyé. #salah,0,yoruba odù ifá wo nìyí | | | | | | | |,0,yoruba owo ṣẹlẹ ni Ibadan ti gbogbo eniyan sọ o ṣe pataki. (1995),0,yoruba "@user: @user Ayarabiasa wulo fun omo’le iwe pupo fun iwadi nkan to’nlo ni aye ati gbogbo imo tuntun. #IAFEE""""""""",0,yoruba "E Ku ise takuntakun Oga @user, kindly follow back. #Yoruba",0,yoruba "ni ìbàdandun àtọ́wọ́dá, àwọn oníṣẹ́ ìṣẹ́ ni a ní láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó tìkẹ́ gbé mú.",0,yoruba Ọkan tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba Àwòrán : Àwòrán tí wọ́n yà nínú fídíò kan láti ọwọ́ọ United Nations Web TV .,0,yoruba dara gan wey ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó wáyé..,0,yoruba aku ori ire o ara omo obasanjo adeboye tawon boko haramu yinbon lu ti ya o,0,yoruba "Isẹlẹ yii n waye lẹyin ti ọkan lara awọn osisẹ ajọ to n se idanwo si ile ẹkọ giga fasiti ni Naijiria, JAMB ti kede faye gbọ pe ejo mi miliọnu mẹrindinlogoji Naira Ọrọ yii waye nigba ti awọn ọlọpaa mẹta kan to n jẹri fun olupẹjọ ninu ẹjọ ti wọn pe awọn obinrin mẹrin kan ti wọn fi ẹsun kan pe wọn n ko ẹẹdẹgbẹsan o le mẹwaa idi ewe oogun oloro igbo ti wọn n pe ni 'Bhang' lọna ti ko ba ofin mu lati ilu Migori si Ukunda ni Kwale. Awọn ọlọpaa mẹta ọhun ni Ken Olonde, Patrick Baya ati Sajẹnti Hamisi Kombo ti wọn fi ofin mu awọn afurasi obinrin naa. Bi a ko ba ni gbagbe, ni orilẹ-ede Naijiria naa lo ti ṣẹlẹ ri ti ọkan lara awọn osisẹ ajọ to n se idanwo si ile ẹkọ giga fasiti nibẹ, JAMB ti kede faye gbọ pe ejo mi miliọnu mẹrindinlogoji Naira owo ajọ JAMB to wa ni ipamọ ọfiisi naa ni ipinlẹ Benue lorilẹ-ede Naijiria. Nigba ti o n fi ọrọ wa wọn lẹnuwo, agbẹjọro fun ọkan lara awọn olujẹjọ naa, Abdul Aminga ke si awọn ọlọpaa naa lati salaye ohun to sokunfa bi awọn idi oogun oloro naa se dinku si ẹẹdẹgbẹsan o le mẹwaa. O fẹ jọ bi ẹnipe awọn ẹranko ni awọn eeyan n fi ẹsun kọ lọrun bayii Awọn ọlọpaa naa ni eku lo ya bo agọ ọlọpaa awọn to si jẹ awọn idi ewe oogun oloro naa ti wọn n pe ni 'Bhang' Amọsa, kayeefi ọrọ naa ni wi pe eku to jẹ idi oogun oloro to wa ninu apoti ko da iho lu tabi jẹ ibikibi lara apoti ti wọn ko o si. Bakan naa ni wọn tun sọọ ko awọn ọlọpaa naa loju pe ọtọ ni iye owo ti wọn n ta egboogi oloro naa nigboro, ọtọ ni iye ti awọn ọlọpaa yii kọ silẹ sinu iwe ofin ni agọ wọn. Bi ọwọ awọn ọlọpaa ṣe tẹ awọn afurasi naa ti orukọ wọn njẹ Pauline Moraa, Elizabeth Atieno, Nancy Auma ati Mercy Achieng nitosi ileto kan ti orukọ rẹ n jẹ Banga lagbegbe Mbunguni ni wọn ti fọwọ ofin mu wọn Ṣé ẹ̀yin lè ṣe jú àwọn tó f'àmì sí Awọlumatẹ? .",0,yoruba èkó aṣà. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó ṣe pàtàkì.,0,yoruba "Nibi ipade ajọ amuṣẹya ni awọn ipinlẹ naa ni wọn ti buwọlu abdofin naa, ti yoo wa lo si ile igbimo asofin ibilẹ nibi ti wọn yoo ti jiroro lori rẹ. Ipade naa to waye ni ilu Ibadan ni wọn ti jiroro lori ohun ti abadofin naa da le lori ati ohun ti wọn gba laaye fun ikọ naa. Kí lo tíì rí nípa Amotekun? Ẹ sùnmọ́bí, ẹ wo gbankọgbì! Kọmisọnna fun eto idajọ ati agbẹjọro agba ni ipinlẹ naa sọ wi pe gomina ipinlẹ ogun sa ipa rẹ lati mu ki eto naa gberu si. O ni awọn fi aaye gbawọn lati da duro,bakan naa ni awọn fayegba ibaṣepo to dan mọran laarin ẹka naa ati ẹka eleto aabo to ku ni ipinlẹ mẹfa ni iwọ oorun Naijiria. Kọmisọnna fun eto idajọ ati olootu naa sọ wi pe o da awọn loju pe awọn asofin yoo ri daju pe abadofin naa kẹsẹjari, ki gomina naa le fowosi laipẹ. Ni ipinlẹ Ogun, awọn igbimọ amuṣẹya naa gbe abadofin naa kalẹ lati le wa ọna abayọ so eto aabo to mẹhẹ,ti awọn igbimọ amuṣẹya naa si pa ohun pọ fẹnu ire pe e. Bakan naa ni awọn igbimọ amuṣẹya naa ni ibaṣepọ to danmọran ti wa laarin awọn olootu ijọba mẹfa naa, ti wọn si jọ panupọ lori isoro naa. Osu Kini, ọdun 2020 ni ipinlẹ mẹfa ni ẹkun iwọ orun Naijiria fowosowọpo lati da eto aabo awarawa silẹ , amọ wọn nilo ofin lati gbe duro daadaa. Na òṣìṣẹ́ Amotekun, ko san ₦250,000 owó ìjìyà, ko sì tún fi ẹ̀wọ̀n oṣù kan jura Ìkede ti jáde pe ẹnikẹni to ba na tabi kọju ija si osisẹ ikọ Àmọ̀tẹ́kùn lẹ́nu iṣẹ́, yóò fi ẹ̀wọ̀n osù kan jura àti ko san ẹgbẹ̀rún lọna igba naira ati abọ. Bakan náà, wọ́n ko le fi òfin de ọmọṣẹ Amotẹkun fún òhun kohun to ba ṣe lásìkò tó ba wà lẹ́nu iṣẹ́. Àṣegbé ni ohunkóhun tí òṣìṣẹ́ aláàbò náà bá ṣe lẹ́nu iṣẹ́ Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Eyi ni ni ọkàn lára ẹsẹ ofin to wà ninu àbádofin to de isọwọ sisẹ ikọ Amotekun nipinlẹ Ekiti, (Ekiti State Security Agency Bill) ti ọdun 2020, èyi to ti wà niwaju ile igbimọ aṣòfin bayii. Gẹ́gẹ́ bi abala kẹrindinlogoji abadofin náà ṣe sọ, ""ẹnikẹni to ba gbiyanju lati di Amọtẹkun lọ́wọ́ láti ṣe ojuṣe wọ́n, lù u tàbi pa a lára lọnà àitọ lẹ́nu iṣẹ́, ti ṣẹ lábẹ́ òfin, yóò si fi ẹwọ̀n àti ẹgbẹrun lọ́na igba àti ààbọ̀ naira jura. Ọjọ kẹsan an Oṣu Kinni ọdun yii ni awọn gomina ipinlẹ mẹfa lati ilẹ Yoruba ṣe ifilọlẹ ikọ Amọtẹkun nilu Ibadan Awọn Gomina ìhà Guusu-Iwọ-òòrun to ku náà ti fi abádòfin wọ́n, siwáju ilé ìgbàmọ àsòfin ìpínlẹ̀ koowa wọ́n. Bakan náà ni òfin tun sọ pé, olori ilé iṣẹ́ Amotẹkun gbọdọ jẹ́ oṣìṣẹ́ fẹ̀yìnti lẹ́nu iṣẹ́ ologun tabi agbofinro. Osogbo Photographer: O gbọdọ ni ìmọ iṣẹ náà, o kere tan ọdun mẹwàá, ti abadofin náà si kan kọmisona ọlọpàá ipinlẹ náà àti adele ilé iṣẹ́ ọmọogun. Abadofin náà tun fààye gba ìdásílẹ̀ àjọ Amọtẹkun, ti ko si gbọdun din ni sáà ọdun mẹrin.",0,yoruba "RT @user: Bi mo baji ng o ru""""""""""""""""@user: Àdúrà l'ẹbọ mi.""""""""""""""""",0,yoruba Ìforúkọsílẹ̀ àti ìyẹrúkọ wò ṣì ń lọ geere #Isolo #ibo2015 #Nigeria2015Elections http://t.co/ZR5GfybFGQ,0,yoruba "se lọ. Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba Èyí ni òun tí a ní nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó wáyé..,0,yoruba "Ìwà ìkórííra n pọ̀si ní orílẹ̀èdè South Africa Ọmọ ilẹ̀ Nàíjììrà kan tí ó fi orílẹ̀èdè náà ṣe ibùgbé, Clement Nwaogu ló ti pàdánù ẹ̀mí rẹ̀ lẹ́yìn tí àwọn ọmọ ilẹ̀ náà jóo níná láàyè. Alukoro ẹgbẹ́ àwọn ọmọ ilẹ̀ Nàíjììrà tí wọ́n ngbé orílẹ̀èdè South Africa Habib Miller sọ ọ́ di mímọ̀ pé ọmọkùnrin náà di olóògbé látàrí ìwà àífẹ́rí ẹ̀yà mìíràn tó gbòde kan nílẹ̀ náà. Ìwà pípa àlejò gbòdekan ní orílẹ̀èdè South Africa Ó sàlàyé pé ọmọkùnrin náà tí ó jẹ́ ọmọbíbí ìlú Njikoka ní ìpínlẹ̀ Anambra lùgbàdì ikú òjijì ní ìlú Rustenburg. Miller fikún ọ̀rọ̀ rẹ̀ pé olóògbé náà jẹ́ onísòwó asọ àga ìjókò nígbà tí ó wà láyé. Ìwà ìkórííra n pọ̀si ní orílẹ̀èdè South Africa Àwọn tí ìsẹ̀lẹ̀ náà sojú wọn sọ pé Nwaogu rawọ́ ẹ̀bẹ̀ s'áwọn ọlọ́pàá sùgbọ́n wọ́n kọ etí ikún síi. Àkọsílẹ̀ fihàn pé ọgọ́fà dín méjì ọmọ ilẹ̀ Nàíjììrà ló ti pàdánù ẹ̀mí wọn ní orílẹ̀èdè South Africa láti ọdún 2016 sí àkókó yìí.",0,yoruba Àkójú ọ̀rọ̀ yi kún fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde sí ara ilẹ̀. (Item 133),0,yoruba wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọmọ lo ni àṣà yorubá eyti o gbe lori iwa rere.,0,yoruba "Ẹgbẹ́ Afenifere ilẹ̀ Yorùbá ti ṣàlàyé ẹni tí wọ́n máa ṣe àtìlẹyìn fún níbi ètò ìdìbò ọdún tó ń bọ̀. Nígbà tí iléeṣẹ́ BBC News Yorùbá kàn sí ẹgbẹ́ Afenifere láti mọ ìpinnu wọn gangan lórí ìròyìn tó ń jà ràìnràìn káàkiri wí pé olùdíje sípò Ààrẹ lábẹ́ ẹgbẹ́ òṣèlú Labour Party, Peter Obi ni olórí ẹgbẹ́ náà fẹ́ tì lẹ́yìn níbi ètò ìdìbò tó ń bọ̀. Agbẹnusọ Afenifere, Jare Ajayi sọ fún BBC Yorùbá pé kí àwọn tó le yan ẹnìkan ṣojú tàbí ṣe àtìléyìn fún olùdíje kankan, àwọn gbọ́dọ̀ mọ ohun tí ẹni náà ní fún àwọn ọmọ orílẹèdè̀ Nàìjíríà. Ajayi ní ohun tí àwọn ti ń jà fún gẹ́gẹ́ bí ẹgbẹ́ láti bí ọjọ́ mẹ́ta ni bí àyípadà ọ̀tun ṣe ma bá Nàìjíríà, fún ìdí èyí olùdíje tó bá le ṣe ìlérí irú àyípadà bẹ́ẹ̀ fún àwọn ni ẹgbẹ́ ma tẹ̀lé. Ó ní ó pọn dandan kí àwọn ṣe ìpádé pẹ̀lú gbogbo àwọn olùdíje láti jọ fi ẹnu jóná lórí ohun tí wọ́n ma ṣe lórí àtúntò Nàìjíríà kí àwọn tó mọ́ ẹni tí àwọn ma gbé àtìlẹyìn àwọn fún. Ó tẹpẹlẹ mọ ọ́ wí pé ohun tó jẹ ẹgbẹ́ Afenifere lógún jùlọ ni bí àtúntò yóò ṣe bá Nàìjíríà, tí agbára yóò sì pín káàkiri ẹsẹ̀ kùkú, tí tọmọdé tàgbà ma lè jẹ́ mùdùn-múndùn ìjọba àwaarawa. Ajayi sọ síwájú pé nígbà tí àwọn bá ṣe ìpádé pẹ̀lú àwọn olùdíje kọ̀ọ̀kan, èyí tó bá le ṣèlérí àwọn nǹkan wọ̀nyí fún àwọn ni ẹgbẹ́ máa tẹ̀lé gẹ́gẹ́ bí olùdíje sípò Ààrẹ. “Ìdásílẹ̀ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀, bí wọ́n ṣe máa pín Nàìjíríà sí ẹlẹ́kùnjẹkùn ṣe pàtàkì, tí gbogbo nǹkan ma ma lọ bó ṣe yẹ ko lọ.” “Tó jẹ́ wí pé gbogbo àwọn nǹkan ọrọ̀ àti àlùmọ́nì tí Ọlọ́run fi sí ilẹ̀ kálukú àwọn tó ni í ló ma kọ́kọ́ jẹ àǹfàní rẹ̀ ná ni a ma gbé síwájú àwọn tó ń díje.” “Ẹní tó bá wá le fihàn wá pé ètò ti òun ní nípa àwọn nǹkan wọ̀nyìí, nípa iná, omi, ẹ̀kọ́, àláfíà àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ ni a ma wá jíròrò lórí ẹ̀ wí pé ibi tí à ń lọ nìyí.” Nígbà tó ń sọ̀rọ̀ nípa ìròyìn tó wà lórí ayélujára Twitter adarí ẹgbẹ́ Afenifere pé Tinubu ma tẹ̀síwájú pẹ̀lú àwọn ìpèníjà tí ìṣèjọba Ààrẹ Buhari kojú, Ajayi ní ojú òpó náà kìí ṣe ti bàbá Adebanjo. Ajayi fìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé bí ó tilẹ̀ jẹ́ wí pé lóòótọ́ ni adarí àwọn ń ṣe àtìlẹyìn fún Peter Obi, ṣùgbọ́n kìí ṣe nítorí ìdí tó wà lórí àtẹ̀jáde Twitter náà. Nínú àtẹ̀jáde kan tí Jare Ajayi fi ṣọwọ́ sí BBC Yorùbá ní ìdí tí bàbá Adebanjo ní àwọn fi ń tẹ̀lé Obi kò kọjá ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn àti àlàkalẹ̀ ìwé òfin Nàìjíríà. Bákan náà ló là á mọ́lẹ̀ pé bàbá Adebanjo kò ní ojú òpó kankan lórí ayélujára nítorí náà kí àwọn ṣọ́ra láti máa gbé ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀ lórúkọ bàbá. Ṣáájú láti kọ́kọ́ mú ìròyìn kan tó gba orí ayélujára kan èyí táwọn oníròyìn bẹ̀rẹ̀ sí ní gbé pé Ààrẹ ẹgbẹ́ Afenifere ilẹ̀ Yorùbá, Pa Ayo Adebanjo ti ṣàlàyé ìdí tí kò ṣe fẹ́ kí Asiwaju Bola Ahmed Tinubu di Ààrẹ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà. Pa Adebanjo ló ti ń ṣe àtìlẹyìn fún olùdíje ẹgbẹ́ ò’sèlú Labour Party, Peter Obi. Nínú àtẹ̀jáde kan tí a rí lórí Twitter tó ní orúkọ Bàbá Adebanjo ní ọjọ́ Ẹtì, ọjọ́ Àbámẹ́ta, oṣù Keje, ọdún 2022, ó ní Tinubu maa tẹ̀síwájú àìkún ojú òṣùwọ̀n ààrẹ Muhammadu Buhari. Adebanjo náà tún ní gbogbo àwọn ìpèníjà tó kún ìṣèjọba ààrẹ Muhammadu Buhari náà ni Tinubu náà ma tẹ̀síwájú nípa rẹ̀ ní èyí tí kò sí ní so èso rere fún Nàìjíríà. Adebanjo ní àwọn mọ Peter Obi dada wí pé kò ní já àwọn ọmọ orílẹ̀ èdè lulẹ̀. Ó ní kí àwọn ènìyàn gbé ti ẹlẹ́yàmẹ̀yà tì sí ẹgbẹ́ kan wí pé Obi ló le tú ọkọ̀ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà dé èbúté ògo. Bàbá Adebanjo ní báyìí, òun ti bẹ̀rẹ̀ ṣíṣe ìpolongo fún Peter Obi káàkiri Nàìjíríà, kí àwọn ènìyàn sì ṣe àtìlẹyìn fún òun láti SỌ Obi di Ààrẹ Nàìjíríà lọ́dún 2023. Ó fi kun pé ó dá òun lójú wí pé Peter Obi ma ṣe dada tó bá dé ipò Ààrẹ ju Tinubu lọ. Ó tẹ̀síwájú wí pé òun kò ní ìfọkàntán nínú Bola Tinubu àti pé ó tẹ́ òun lọ́rùn kí Obi ṣe ààrẹ ju Tinubu lọ. “Nígbà tó jẹ́ wí pé gbogbo ìgbà ni à ń pè fún dọ́gba-n-dọ́gba, mo rò wí pé àsìkò ti tó kí àwọn ẹ̀yà Igbo ṣe Ààrẹ Nàìjíríà, fún ìdí èyí, Peter Obi ni mò ń ṣe àtìlẹyìn fún. Ṣaájú àkókò yìí ni ẹgbẹ́ Afenifere ti ń bèèrè fún ṣíṣe àtúngbéyẹ̀wò ìwé òfin Nàìjíríà. Bẹ́ẹ̀ náà ni wọ́n tún pè fún àtúntò Nàìjíríà gbogbo ìpèníjà tó ń bá orílẹ̀ èdè Nàìjíríà fínra.",0,yoruba "Ṣe àlàyé òwe yìí : à ti gbé 'yàwó kò tóó pọ́n, owó ọbẹ̀ l'ó ṣòro. #ibeere #Yoruba #Owe",0,yoruba naa ní ègé olóótọ fún àwọn ìkòkò tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa òkè:.,0,yoruba Iṣọ́ẹ̀ ìṣẹ́ ni a ní láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba "Èdè Yorùbá ò gbọdọ parún - Toyosi Ogunseye Èrèdí ìpolongo àti àbẹ̀wò sí ilé iṣẹ́ ìròyìn Suncity Fm ní agbègbè Bana ìpínlẹ̀ Ondo ní láti rii dájú pé àṣà, iṣẹ̀ṣe àtí èdè Yorùbá ò parun. Alákoso àgbà tó ń sojú iwọ̀ọ-orun ile Afirika Toyosi Ogunṣeye ní ìdásilẹ̀ BBC news Yoruba kò ṣẹ̀yìn àti fẹ́ná sí èdè àti àṣà Yorùbá tó ń jó àjórẹ̀yìn lójoojúmọ́ pàápàá jùlọ láàrin àwọn ọ̀dọ́ òde òní. BBC Yorùba sàbẹwo sí ilé iṣẹ́ Suncity BBC Yorùba sàbẹwo sí ilé iṣẹ́ Suncity Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'BBC Yoruba gan gan lara' Ayẹyẹ ifilọlẹ ileeṣẹ BBC Yoruba BBC ṣe'filọlẹ Yoruba, Igbo ati Pidgin Yemi Alade Promo Toyosi ní pàtàkì ìfọwọsowọ́pọ̀ tí BBC yoruba ń fẹ láàrin Suncity Radio ilé iṣẹ́ méjèèjì ní láti máá ṣe àgbélárugẹ fún àwọn ẹka ìroyin nínú ètò ọrọ̀ àjé, ètò ìlera, ètò òṣèlú, ìdárayá, àwọn ìwádìí ìjìnlẹ̀ àti onírúúru ìròyìn tí BBC maa ńgbejade Lórí ètò kan náà tí ọ̀gá àgbà BBC Yorùba pẹ̀lú tí kopa, arábìnrin Adedayọ Owolabi rọ àwọn obi àti alágbàtọ lati kọ àwọn àṣà tó ń ṣe ìpalára fún èdè Yorùba sílẹ̀, pàápàá jùlọ nípa sisọ ọmọ ni orukọ tí kìí ṣe ti èdè Yorùbá àti sísọ èdè gẹ̀ẹ́sì sí ọmọ ní gbogbo ìgbà. Iko BBC Yoruba tuntun Toyosi fi kún ọ̀rọ̀ rẹ̀ pé BBC Yorùba ń lo ẹ̀rọ alagbéká gẹ́gẹ́ bí ibi ìgbóhùn sáfẹ́fẹ́ rẹ̀ nítorí pé ó jẹ ibi ti àwọn ọ̀dọ́ pọ̀ sí jùlọ láti maa mọ bo ṣe ń lọ lágbàyé facebook/bbcnewsyoruba, Instagram/ bbcnewsyoruba àti www.bbc.com/yoruba.",0,yoruba mú. Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.,0,yoruba "Olukọ kan nipa itan ni Fasiti Adekunle Ajasin, to wa ni Akungba-Akoko, nipinlẹ Ondo, Ọmọwe Simon Odion Ehiabhi wa lara awọn onwoye ọrọ yii lasiko to n ba BBC sọrọ. Ehiabhi woye pe iṣoro akọkọ ti Naijiria ni ni pe, gbogbo awọn to ti n dari ijọba lati ọdun 1960 ko du ipo lati tun ilu ṣe, ṣugbọn n ṣe ni ọpọ ninu wọn du ipo, lati tun apo ara wọn ṣe. O ni lara awọn nnkan to fa ogun abẹle naa ni awọn adari Naijiria ṣi n ṣe laye ode oni, eyi to tumọ si pe wọn ko kẹkọọ kankan lara ogun abẹle ọhun. Gẹgẹ bo ṣe sọ, o ni ijọba apapọ ti ko gbogbo awọn iwe itan to le ṣalaye ẹkunrẹrẹ nipa ogun abẹle naa pamọ. BIAFRA at 50: Ìhàlẹ̀ ológun ni Gowon ni ká kọ́kọ́ fi bẹ̀rẹ̀- Aladejẹbi O ni ""ko si opitan kankan nilẹ yii to le sọ pe oun ti foju ganni awọn iwe to le sọ ẹkunrẹrẹ bi ogun ọhun ṣe waye."" ""Fun apẹrẹ, gbogbo awọn atẹjiṣẹ laarin ọgagun Ojukwu, Gowon, Aburi atawọn eeyan miran bẹẹ bẹẹ lọ ni ijọba ti ko pamọ, ti a ko ba ri awọn iwe wọnyii, awọn ọmọ aye ode oni ko le kẹkọọ nipa ogun naa."" Olukọ ọhun sọ pe, eyi ti mu ko ṣoro fun ọpọ ọmọ Naijiria lati mọ pe, kii ṣe gbogbo ede aiyede ni rogbodiyan le yanju. Ọmọwe naa tẹsiwaju pe, ẹkọ miran ti Naijiria kuna lati kọ lara ogun abẹlẹ naa ni pe, awọn eeyan ti kuna lati maa kọ awọn ọmọ wọn nipa itan orilẹ-ede Naijiria. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ehiabhi ni, ""to ba jẹ pe a n kọ awọn ọmọ wa nipa itan orilẹ-ede wọn ni, a ti maa kọ wọn nipa irẹpọ laarin oniruru ẹya ati pe iyatọ to wa laarin awọn ẹya naa kii ṣe ohun to buru, ṣugbọn yoo tun bọ jẹ ki a lagbara si ni."" Ọmọwe Ehiabhi tun sọ siwaju si pe bi ijọba Naijiria ṣe n ta ẹya igbo nu ṣegbẹ kan lẹyin ogun abẹlẹ naa ko bojumu to nitori awọn eeyan n ri bii igba ti ibadọrẹ wa laarin ẹya Hausa ati Yoruba, ṣugbọn wọn yọ Igbo sẹyin. Ado Ekiti Blind Couple: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú Ehiabhi pari ọrọ rẹ pe, Naijiria ko ni ijọba ṣugbọn awọn alagbara kan lo kan n ṣe ijọba orilẹ-ede naa bo ṣe wọn, fun anfani ara awọn atawọn ẹbi wọn. Lẹyin naa lo ni ọna kan gboogi ti itẹsiwaju fi le de ba Naijiria ni atunto ni kiakia.",0,yoruba "FRSC gba awọn awakọ niyanju lati gba popona Lokoja ti wọn ba n lo si olu ilu Naijiria, Abuja. Agbẹnusọ fun ajọ to n risi ọrọ oju popo, Bisi Kazeem nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ fikun un wi pe ki awọn awakọ o sọra lati gba ọna naa. Ninu ọrọ rẹ, Kazeem ni looto ni isẹlẹ naa waye ni ipinlẹ Niger, lẹyin ti ojo rọ. Ọ̀rọ̀ fún àwọn tó ń lo ike rọ́bà O gba awọn awakọ niyanju lati gba opopona Lokoja ti wọn ba n lo si olu ilu Naijiria, Abuja. Iroyin fi lede wi pe ọna Mokwa si Jebba ni ọpọlọpọ eniyan ma n gba lọ si Ilorin ati si Abuja.",0,yoruba fun ipilẹ̀ ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba "Bẹẹ ba gbagbe, Adebayọ Alao Akala, ti ẹgbẹ oselu ADP nipinlẹ Ọyọ, ti yẹba bii oludije fun ẹgbẹ oselu naa, to si to sẹyin oludije fẹgbẹ oselu APC, Adebayọ Adelabu. Bakan naa si lawọn oludije latinu ẹgbẹ oselu SDP, ZLP, NPM ati bẹẹ bẹẹ lọ to sẹyin oludije fẹgbẹ oselu PDP, Seyi Makinde. Bakan naa si lọrọ sori lawọn ipinlẹ yoku bii Rivers, Kano, Kwara ati Eko. Nigba to n dahun ibeere lori boya igbesẹ naa lee nipa lori eto idibo to n bọ, oṣiṣẹ alarina fun ajọ INEC nipinlẹ Eko, Ọgbẹni Femi Akinbiyi sọ pe, niwọn igba ti ẹgbẹ oṣelu ko ba ti yi orukọ rẹ pada, awọn ọmọlẹyin rẹ le dibo fẹgbẹ to ba wu wọn. Ọgbẹni Akinbiyi fikun ọrọ rẹ pe, tawọn ẹgbẹ oṣelu ba ko ara wọn jọ pọ lati jẹ ọkan, ni ọrọ kan ajọ INEC. O ni wọn ni lati fi orukọ tuntun ti wọn fẹ jẹ ranṣẹ pẹlu awọn oloye tuntun ninu ẹgbẹ. Idibo gomina ni ipinlẹ Oyo Lori bi gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ ri Otunba Adebayo Alao-Akala to jẹ oludije si ipo gomina fẹgbẹ ADP tẹlẹ ṣe kede atilẹyin fun oludije APC Oloye Adebayo Adelabu Penkelemesi, o ni Akala lanfani labẹ ofin idibo lati ṣe bẹẹ.",0,yoruba "Alága Ìgbìmọ̀ Àtìlẹ́yìn Òmìnira ti orílẹ̀ - èdè náà , Khafra Khambon , gbà .",0,yoruba ọba tí kìí sùn ọba tó jẹ́ pé bó ti wù ú ní í ṣolá ẹ̀,0,yoruba "tún ṣe àwọn iṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Nitori eyi, ara eni lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..",0,yoruba "ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "#iroyin, #yoruba, Awon kan ti pinnu lati da omi alaafia ipinle Osun ru lodun yii, sugbon… https://t.co/edLIaRseBG",0,yoruba Ṣe o fẹ́ pa ápúlẹ́ẹ̀tì náà jẹ kúrò nínú àtòpọ̀ rẹ?,0,yoruba "Egbé, Kánàkò àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ t'ó jẹ́ṣẹ́ ọpọlọ àwọn baba wa ńkọ́! A ní kí ní ń jẹ́ sáẹ́nsì? Oògùn ni yẹn àbí kì í ṣe science. #Kiwontode",0,yoruba Ìròyìn tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìṣẹ̀: ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó wáyé..,0,yoruba iṣẹ́ tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìwà: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó wáyé..,0,yoruba "Sandra ra ìfọn trumpet fún #Fela, ó fún-un níwèé ìtàn, ó la ojú rẹ̀ sí àìmọ̀, kódà wọ́n jọ kọrin 'orí nísàlẹ̀' #Upsidedown ni. #Abamieda",0,yoruba "Mo ti di pèrègún etídò, tó bá dàmọ́dùn, mà á báwọn ṣàmọ́dún. Gúnnugún kì í kú ní rèwerèwe. Ẹsẹ̀ mẹ́ta ni ti àgbó."""""""" #Iwure #OdunTitun2018",0,yoruba òkè là ń lọ lágbára olúwa kò ní séwu,0,yoruba "The saying that's used in not writing kids' importance/efforts off: Ọwọ́ ọmọdé/èwe ò tó pẹpẹ; Ti àgbàlagbà ò wọ akèrègbè (a kid's hand isn't high enough to reach the altar; the elder's hand can't enter a gourd) ... Is gotten from a verse in Odù Ifá, ÌWÒRÌ MÉJÌ",0,yoruba "Áṣámú lọ, àwẹ̀ tẹ̀le. Ẹ̀yin oláàwẹ̀ Ràmàdáǹ, ẹ kú òǹgbẹ o.",0,yoruba "Nibayii ti opin ọsẹ wọle de, ẹ jẹ ka pa ara wa lẹ́rin, ka si kọgbọn nipasẹ awọn ọkanojọkan aworan , eyi to wa lati ilẹ Afirika.",0,yoruba "Gbèsè tí Buhari ń jẹ bójúmu, isẹ ìdàgbàsókè ló fi ń ṣe - Agbẹnusọ fún ilé aṣòfin àgbà",0,yoruba Toò. Wákàtí mẹ́rẹ̀rínlélógún kíní ọdún ti ṣojú wa. Ọlọ́run fún wa ní ore ọ̀fẹ́ láti rí ìyókù náà o. Àti jù bẹ́ẹ̀ lọ. #2013,0,yoruba #LayajoOjoOni ni odun 1854 ni awon omo egbe Oselu WHIG ko ara won jo lati da egbe oselu Republican sile ni Ilu Wisconsin ni ile Amerika,0,yoruba 7.Wọ́n á ní “àtẹ̀ yún àtẹ̀ wá ni àtẹlẹsẹ̀ ń tẹ ekùrọ́ ojú ọ̀nà”. Kí ni ìtúmọ̀ yún nínú “àtẹ̀ yún”? #ibeere#Yoruba,0,yoruba ẹ jẹ́ a jọ ṣé kó ba dára fún wa pọ̀ igi kan ò dágbó ṣe làwọn àgbà wí ìdùnnú á ṣubú layọ̀ bí ẹ bá dìbò fún mi ní,0,yoruba ẹkọ́ ṣẹlẹ ni Eko ti gbogbo eniyan sọ o dara. (2023),0,yoruba "ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Bàbá lo ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba Ẹ kú ìrọ̀lẹ́ o ẹyin sànmọ̀rí! Ẹ jẹ́ ká bi ara wa láwọn #ibeere mélòó kan kí a la ara wa lọ́yẹ̀. Ṣé ó yá! #Yoruba,0,yoruba """Ohun tí yóò ṣẹlẹ̀ rèé bí Tinubu ṣe padà dé láti pàwọn ọ̀tá lẹ́nu mọ́""",0,yoruba tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọmọ lo ojú odò.,0,yoruba ti Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba ṣe iyalẹnu wey ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó ga jù.,0,yoruba o dara. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò.,0,yoruba ìlú.. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gblọ yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba òní nípa ìwé orisirisi ni nfàn ojú kakaaki.,0,yoruba oni ni ayajø øjø ede abinibi wa jakejado agbanlaaye ømø oduduwa ni mi ti a tun pe ni opøndandan fun mi lati fi ede abinibi mi kø awøn ømø mi bi awøn obi mi ti fi kø emi naa,0,yoruba Toò. Ó wuni ká jẹran pẹ́ lẹ́nu.... Àrìnká tòní dádúró sí bẹ̀un ná. Ìyókù tún di ìrọ̀lẹ́. K'Ọ́lọ́run ṣọ́ wa.,0,yoruba àgbà ri pe lẹ ìkòkò wey ti o dara.,0,yoruba ".@user @user Mo ṣe bí èèyàn """"""""""""""""""""""""""""""""Ọlọ́run"""""""""""""""""""""""""""""""" ni @user, à ṣé è, bojú bojú ni. Ẹ̀yìn ń kí òṣìṣẹ́ tí ò gb'owó oṣù kú àyájọ́ ọjọ́ òṣìṣẹ́. Èké ni yín!",0,yoruba "Ibeere ti gbogbo ara adugbo to lọ ibi iṣẹlẹ naa ni pe ta lo pa wọn. Oun to jẹ kayefi ni bi wọn gbe ori awọn ọkunrin mẹta naa, ti wọn si náà duro ni ẹgbẹ awọn oku naa. Ibeere ti gbogbo aye fi lẹnu ni wipe, ta lo pa awọn ọkunrin mẹta yii? Awọn ara adugbo kan ni awọn lero wipe ikọlu awọn ọmọ ẹlẹgbẹ okunkun lo fa iku awọn oloogbe naa. Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Ìfipálówó: Bàbá ọmọ tí wọn gé lórí ní òun rán an láti l gbowó lẹ́nu ATM ni Nigba ti akọroyin BBC Yoruba kan si agbenusọ ileeṣẹ ọlọpaa ni Ipinlẹ Eko, Bala Elkana, o sọ wipe iwadi n lọ lọwọ lori bi awọn ọkunrin mẹta naa ṣe ku. Ko ti i si ẹni to mọ orukọ awọn oloogbe naa tabi ibi ti wọn ti wa. Elkana ni awọn oun ti iwadii yoo fi han ree. Ṣe ni awọn ara adugbo naa n fi aworan awọn oku naa sori atagba Twitter ti gbogbo ero si n lọ pe wo awọn oku ati ori naa ki awọn ọlọpaa to gbee lọ.",0,yoruba Sin ► hide/conceal; (ó sín owó sóké àjà - he concealed money on top of the ceiling) #InYoruba,0,yoruba òní.. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó ga jù.,0,yoruba "Àbí ẹ ya àwòrán #eclipse? Ẹ ṣáwòó, kò fi bẹ́ẹ̀ hàn lágbègbèe tèmi. #Nigeria #Lagos",0,yoruba """Ọjọ 1K, 3K tàbí iṣẹ́ ọ̀fẹ́, bí mo ṣe bẹ̀rẹ̀ nìyẹ́n àmọ́ lónìí..."" Ẹ ko ni lati gbe oju soke lati mọ pe oṣere Lalude, Alapini, Odunlade Adekola ati bẹẹ bẹẹ lọ lo n sọrọ loju agbo tẹẹ lọ. Amọ nigba tẹ o ba fi sun mọ iwaju, niṣe lẹ o la ẹnu silẹ tẹ o si bọ oju yin walẹ lati rii pe ṣe lootọ kii ṣe awọn ti ẹ n gbọ ohun wọn gangan lo n sọrọ. Onimọ nipa oriṣiriṣi nkan ni Ojo Sheu ti ọpọlọpọ mọ si General Olak ni ilu Ibadan ati kaakiri Naijiria paapaa nipa igbe aye ati isọrọ si awọn gbajugbaja oṣere fiimu. Ẹ̀nìkan sọ fún mi pé iṣẹ́ ìdọ̀tí ni màá ṣe láti là, ni mo ṣe ń ta ìwé lójú pópó - Wikipedia Lafup, Adẹ́rìínpòṣónú tó kọ́kọ́ jáwó lórí ẹ̀fẹ̀ n'Ibadan Wọ́n fi májèlé sínú gbogbo òúnjẹ́ ti mo rà sílé, ohun tí mo sọ fún ẹni náà rèé - Paramount Komedy Ètò 'Mr & Mrs kògbérégbè' tí ṣàkọ́bá fún mí gẹ́gẹ́ bí ọkọ nínú ìgbéyàwó - Mr Kogberegbe Ibi tí àwọn àwàdà Okunnu ti bẹ̀rẹ̀ rèé Lilo ohun rẹ lati sọrọ gẹlẹ bi awọn oṣere yii ni nkan to n pawo wọle fun General Olak bayii. Ko lee fi ọkan pe meji rara bi ẹ ba ni ko yi si ohun eeyan mẹrin lọtọọtọ. Adẹrinpoṣonu yii ja gbangba pẹlu ara ọtọ ọna ti o n gba ṣe ẹfẹ rẹ yii nipa sinsin ohun awọn oṣere jẹ ti ẹ o si ro pe awọn gangan lo n sọrọ bi ẹ ko ba gboju soke wo ẹni naa. BBC Yoruba ni ifọrọwanilẹnuwo pẹlu adẹrinpoṣonu ẹlẹbun pupọ yii to si ṣalaye bo ṣe bẹrẹ owo kan ṣoṣo to fi n bọ ara rẹ yii. 'Tí kìí bá ṣe pé mo rọ lẹ́sẹ̀, àwọn èèyàn sì kọ̀ láti gbé mi lọ ilé ẹ̀kọ́, ó yẹ kí ń ti dí ""Lawyer"" àmọ́...' Kunle Adeyanju tí ó gun alùpùpù láti London ti balẹ̀ bìbà sí Nàìjíríà",0,yoruba ó ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó ṣe pàtàkì.,0,yoruba emi mo bi won se n gbenusi i omoge onidodo,0,yoruba "Àwọn Asòfin Naijiria fẹ́ràn gbígba owó ẹ̀bùrú Alaga ajọ to ń rísí ètò ìdìbò Nàìjíríà (INEC) tẹlẹri, Ọjọgbọn Attahiru Jega, ni ọ̀nà àbáyọ ni ki a dẹ́kun rìbá gbígbà ni Naijiria. Attahiru Jega ti fi ẹsun kan awọn Ile Igbimọ Asofin lorilẹ-ede Naijiria pe wọn fẹran lati ma a gba owo ni ọna ẹburu lati le se isẹ wọn. Jega sọ ọrọ yii nibi to ti n se idanilẹkọọ lori ayajọ Ọjọ Iṣejọba Tiwantiwa (Democracy Day) t'ọdun yii ni Abuja lorilẹ-ede Naijiria. Nigeria vs DR Congo: Eagles gbá ọ̀mì pẹ̀lú Leopard ní Pọtá Orilẹ-ede Naijiria wa lara orilẹ-ede marun un lati ile Afrika ti yoo kopa ni Russia 2018 Ìkọ agbaboolu Super Eagles orílè-èdè Nàìjíríà ati akẹgbẹ wọn láti orílè-èdè DR Congo ti gba àmì ayò kọọkan nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọlọrẹsọrẹ Ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà wà lára ipalemo ìkọ Super Eagles ṣaaju ìdíje ife ẹyẹ àgbáyé to n bò lónà ní Russia. E ka ekunrere re ni bii Awọn nkan miran ti ẹ ni lati mọ loni Gbọ iroyin iṣẹju kan BBC Fidio wa fun toni Aliu Sodiq mú ìbẹ̀rù kúrò lọ́kàn àwọn ènìyàn nípà ìrírí mọ́ṣúàrì. 'Obìnrin tí kó ba fẹ́ òṣìṣẹ́ Mọ́ṣúárì, ìpinu rẹ̀ mẹ́hẹ'",0,yoruba we visit the eulogy of ìyẹ̀rúọ̀kín ọlọ́fàmọjọ̀ the people of ọ̀ffà gather here and enjoy your fathers eulogy ilé ìyẹ̀rúọ̀kín ọlọ́fàmọjọ̀ ni a dárí sí ní wáyìí ẹ̀yin ọmọ ọ̀ffà ẹ sún mọ́ bí fún oríkì baba yín by,0,yoruba "Biden ni Donald Trump gbọdọ fun oun ni aye lori bi yoo ṣe gbe ipo silẹ ni ọdun to n bọ lai si idẹna kankan. O ni oun nilo ki Aarẹ Trump fi ipo silẹ ki awọn le gbogun ti arun Coronavirus to n gbẹmi awọn eniyan lọgọọrọ. ''O ṣeni laanu pe titi di asiko yii aarẹ Trump ṣi kọ lati gba wi pe oun kọ lo wọle gẹgẹ bi aarẹ lorilẹede naa'' Aibikita aarẹ Trump yii yoo jasi iku ọpọlọpọ awọn eniyan to n koju arun Coronavirus lọwọ'' Ti a ko ba gbagbe, aarẹ Donald Trump ti lọ si ileẹjọ lati tako awọn esi idibo to jade ni awọn ipinlẹ jankan-jankan lorilẹede naa. Kini ileẹjọ n sọ nipa ẹjọ ti aarẹ Trump n pe lori esi idibo to gbe Joe Biden wole? Ajọ to n risi ọrọ idibo nipinlẹ Wisconsin ti ni awọn ikọ ipolongo aarẹ Trump yoo san iye owo to to miliọnu mẹjọ dọla ilẹ okeere lati tun ibo ka nipinlẹ naa. Joe Biden lo bori ni Wisconsin pẹlu ibo to lẹ ni 20,000 ju ti aarẹ Trump lọ. Ipinlẹ Georgia yoo tun idibo ka lati agbegbe kan si omiran Amọ, ikọ eleto idibo ni Georgia ti ni awọn ti ri ibo 2,600 ti wọn ko ka mọ esi idibo naa, ti won si ṣetan lati tun ibo ka. Ọkan lara awọn oṣiṣẹ eleto idibo naa ni awọn kan kuna lati ka ibo naa nitori aimọ iṣẹ ṣe wọn. Bakan naa ni ipinlẹ Gorgia yoo ma ka idibo naa lati agbegbe kan si omiran nitori ida 0.3% to wa laarin aarẹ Donald Trump ati Joe Biden. Donald Trump ní Joe Biden wọlé ìbò ààrẹ Amẹrika ṣùgbọ́n... Aarẹ Donald Trump ti sọ pe alatako rẹ tii ṣe oludije ẹgbẹ oṣelu Democrat, Joe Biden wọle. Ṣugbọn to wa nibẹ ni wo pe Trump to jẹ oludije ẹgbẹ oṣelu Rupublican ni Biden wọle ibo aarẹ nitori wọn ṣe eeru ninu eto idibo naa. Loju opo Twitter rẹ lo ti fi ọrọ yii lede lọjọ Aiku, ọjọ kẹẹdogun oṣu kọkanla ọdun 2020 yii. ''Ko si awọn oluṣọ ibo tabi awọn onwoye nibi eto idibo naa, ileeṣẹ ti ko lorukọ to dara, Dominion lo tun wa ṣe agbatẹru eto idibo ọhun to fi mọ ayederu ileeṣẹ iroyin,'' Trump lo sọ bẹẹ. Aarẹ ni gbogbo kudiẹ kudiẹ to ṣẹlẹ lalẹ ọjọ eto idibo ṣẹlẹ ki ẹgbẹ Democrat le jale ibo ni. O ni wọn jale ibo naa ko si ẹni to ko kawọn mọ bẹ, Trump ṣalaye pe awọn to dibo pẹlu ẹrọ ifọrọranṣẹ iyẹn Mail-in pa ni lẹrin. Loju awọn ileeṣẹ iroyin ayederu ni Biden ti wọle ibo aarẹ Amẹrika. ''Emi ko gba pe o wọle. Ọna si jin lori ọrọ ibo yii. Eeru ni Biden fi wọlẹ,'' Trump lo sọko ọrọ yii. Trump ni o da oun loju pe oun yoo pada wọle ibo aarẹ ilẹ Amẹrika. Ìdí rèé tí Donald Trump ṣe fìdí rẹmi nínú ìbò ààrẹ Amẹrika Donald Trump sọrọ pẹlu igboya ṣaaju ibo aarẹ orilẹede Amẹrika ọdun 2020 pe oun yoo wọle lẹẹkeji gẹgẹ bi aarẹ ilẹ Amẹrika. Ṣugbọn ọrọ bẹyin yọ lẹyin ti oludije ẹgbẹ oṣelu Democrat, Joe Biden fẹyin rẹ gbolẹ ninu eto idibo naa. Amọ ki lo ṣe okunfa ijakulẹ Trump ninu eto idibo tawọn ọmọ ilẹ Amẹrika ti tu yaaya ta yaaya jade dibo? Trump ni ibo to le ni aadọrin miliọnu eyi to jẹ eleyi to pọ julọ sikeji ninu itan oṣelu orilẹede Amẹrika. Ṣugbọn o fidi rẹmi, eyi to jẹ ko di aarẹ Amẹrika ẹlẹẹkẹrin to kuna lati wọle saa keji. Awọn onwoye nipa ọrọ oṣelu sọ pe Trump wọle ibo aarẹ lọdun 2016 nitori o sọ ọrisiiriṣii ọrọ ti ko baku gbe. Ṣugbọn awọn onwoye naa sọ pe Trump kun a ninu ibo aarẹ ọdun 2020 nitori awọn ọrọ alufansa to n sọ naa. Ọpọ to dibo fun Trump lọdun mẹrin sẹyin lo yi ọkan wọn pada nitori ihuwasi rẹ. Ọpọ ọmọ ilẹ Amẹrika lo koro oju si bi Trump ṣe n sọrọ ko bakungbe ni gbogbo igba. Ọgọọrọ awọn to n gbe igberiko lorilẹede Amẹrika ni ko gba ti Trump mọ rara. Ọpọ awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu Republican gan an to jẹ ẹgbẹ oṣelu Trump papaajulọ awọn to kawe gan an ko nifẹsi si bi o ṣe n sọrọ sawọn ẹya mii yatọ si awọn alawọ funfun l'Amẹrika. Wọn o fẹran bi koṣe bawọn alawọ funfun wi nigba ti wọn ba ṣe aṣemọṣe. Bakan naa ni inu wọn ko dun pẹlu bi Trump ṣe di ọrẹ awọn olori apaṣẹ waa bii Vladimir Putin. Ohun kan to daju ni pe awọn ọmọ ilẹ Amẹrika ko le gbagbe Trump laelae gẹgẹ bi ilẹ naa.. US Election 2020: Ṣé èsì ìdìbò Ààrẹ Amẹrika yóò jáde lálẹ́ ọjọ́ ìdìbò? Ọpọ awọn oludibo nilẹ Amẹrika ni yoo maa retin esi ibo ti wọn di lọjọ ti idibo naa ba waye, ṣugbọn ibeere ti ọpọ eeyan maa n bereni pe igba wo gan ni esi na yo jade? Idibo nipasẹ ileeṣẹ ifiweranṣẹ Lọdun 2016, miliọnu mẹtalelọgbọn awọn ọmọ ilẹ Amẹrika lo di ibo wọn nipasẹ awọn ileeṣẹ ifiweranṣẹ. Nitori ajakalẹ arun Coronavirus lọdun yii, miliọnu mejilelọgọrin eeyan lo ti fi erongba wọn lede lati dibo nipase awọn ileeṣẹ ifiweranṣẹ. Ṣugbọn ọpọ ileeṣẹ ifiweranṣe ni ko tii bẹrẹ iṣẹ ni kikun nitori ajakalẹ arun naa. Fun apẹẹrẹ, ni ipinlẹ Michigan, nnkan bii miliọnu mẹta eeyan lo ṣeṣe ko dibo nipasẹ ileeṣẹ ifiweranṣẹ, ṣugbọn wọn ko ni bẹrẹ si ni ka ibo naa titi di ọjọ ibo gangan, to n tumọ si pe yoo to ọjọ diẹ si akoko naa ki wọ to ka ibo ọhun tan. Lọwọ yii obitibiti iwe ti awọn eeyan fi ranṣẹ ni ko tii tẹ awọn ti wọn fi ranṣẹ si lọwọ nitori ajakalẹ arun Coronavirus. Iwadii nipa eto idibo to to waye sẹyin fi han pe, iye awọn ọmọ ẹgbẹ Democrat to n dibo nipasẹ ileeṣẹ ifiweranṣẹ pọ ju ti Republican lọ. Bẹẹ ni wọn ni o ṣeṣe ki pupọ ninu awọn ọmọ ẹgbẹ Republican ti yoo dibo lojukoju pọ ju ti Democrat lọ. Iṣoro keji ti idibo Amẹrika maa ń ní ni ipẹjọ Nigba ti ko ba si alafo to lamilaaka laarin esi awọn oludije, o ṣeṣe ki ipẹjọ wa lori awọn ibo ti wọn ko ka, eyii to le fa ki esi ibo naa falẹ. Idi kan pataki ti wọn kii fi ka awọn ibo kan ni bi iwe idibo naa ba pẹ de lati ọdọ awọn ileeṣẹ ifiweranṣẹ. Ni ọdun yii ti wọn sọ pe o ṣeṣe ki awọn iwe idibo ti yoo wa lati ọwọ awọn ileeṣẹ ifiweranṣẹ pọ ju ti tẹlẹ lọ, wọn ti sọ pe o ṣeṣe ki iwe idibo ti wọn ko ni ka pọ ju ti atẹyinwa. Njẹ o ṣeṣe ki esi idibo jade lalẹ ọjọ idibo? Bẹẹni. Awọn onimọ nipa eto idibo naa ti sọ pe o ṣeṣe ki esi ibo waye lalẹ ọjọ idibo, ki awọn eeyan si mọ ẹni to jaweolubori lọjọ kan naa. Ki ẹnikẹni ninu awọn oludije memeji to lee pegede ninu idibo ọhun, o ni lati rekọja ibo 270 ti awọn ""electoral college"" yoo di. Njẹ awọn ileeṣẹ tẹlifiṣọn Amẹrika lagbara lati kede esi ibo lalẹ ọjọ kan naa? Ayẹwo awọn idibo to ti kọja fi han pe awọn ileeṣẹ tẹlifiṣọn Amẹrika ti kede esi ibo ri, bo tilẹ jẹ pe ajọ to n ri si eto idibo naa ṣi n ka ibo ọhun lọwọ. Bo tilẹ jẹ pe ọpọ eeyan ni yoo joko ti ẹrọ amohunmaworan lalẹ ọjọ idibo ti a n sọrọ rẹ yii, o ku sọwọ suura awọn ileeṣẹ amohunmaworan lati ṣe iṣẹ wọn bo ṣe yẹ.",0,yoruba Àkójú ọ̀rọ̀ yi kún fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde sí ara ilẹ̀. (Item 9),0,yoruba "ìgbà mi owó àkokò, Ọmọ lo ni ìgbà mi owó àkokò, Ọba ri Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba àkàrà tú sépo,0,yoruba wá lẹ̀ẹ̀ní nípa òkè: ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa àwọn ènìyàn: ti o dara.,0,yoruba Ẹ lọ apply ní https://t.co/F6rxmpDs8F https://t.co/QtA6Q5rKee,0,yoruba "Niger Delta Avengers: Buhari fèsì pé gbogbo ohun tí NDA ń bèèrè fún, ni òun ti ṣe",0,yoruba "kún jú, àwọn ènìyàn ni ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn.",0,yoruba "#iroyin, #yoruba, O ga o! Ambode fowo osi juwe ile fun Deji Tinubu: Gomina ipinle Eko… https://t.co/Su3RKiCI3H",0,yoruba a kọ eḳọ nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà.,0,yoruba "Awọn asofin ṣi n ba iṣẹ lọ ni ile aṣofin lalai si iranlọwọ awọn oṣiṣẹ ile aṣofin Lọsẹ to kọja ni wọn leri lati da iṣẹ gbogbo duro lori bi awọn alaṣẹ ile aṣofin naa ko ti ṣe san owo oṣu wọn. Iroyin to tẹwa lọwọ so pe niṣe ni awọn oṣiṣẹ naa yan iṣẹ lodi ni ile asofin ohun lọjọ aje tii ṣe ọjọ kẹtadinlogun oṣu kejila ọdun 2018. Awọn oṣìṣẹ́ fẹ̀hónú hàn níle ìgbìmọ̀ Aṣofin Saaju ni wọn ti gbe awọn ìgbésẹ̀ kan to fi mọ bi wọn ti ṣe ṣe iwọ́de ìfẹ̀hónú hàn láti dí ìgbòkègbòdò ilé ìgbìmọ̀ àsṣòfin lọ́wọ́ lọjọ́ kerin àti ọjọ́ kẹjọ oṣù kejila, ọdún 2018. Iyanṣẹlodi ko da iṣẹ duro Tóhun tí iyanṣẹlodi náà, àwọn aṣòfin tí kéde orúkọ àwọn ọmọ àjọ tí yóò mójú tó ètò gbogbo nílé aṣòfin Nàìjíríà. Ikede orukọ awọn ọmọ ajọ naa ti Aarẹ ile asofin Bukola Saraki kede ni wọn fi sita loju opo Twitter ile asofin lọjọ aje kannaa ti awọn oṣiṣẹ ohun da iṣẹ silẹ. Ara iredi iyansẹlodi awọn oṣiṣẹ ile asofin ni wi pe awọn ko ri ẹtọ awọn gba nipaṣẹ owo osu ati ajẹmọnu ti o tọ si awọn . Igbagbo wọn si ni wi pe iyanṣẹlodi naa yoo ṣe idiwọ fun iṣẹ awọn asofin eleyi ti yoo mu ki ọrọ naa ni iyanju. 'Tayọ̀tayọ̀ ni mó fẹ́ ṣiṣẹ́ pẹ̀lú INEC ki ìdìbò 2019 lé dára' Ko ti daju boya awọn alaṣẹ yoo wa wọrọkọ fi ṣada lori ọrọ to wa nile yi ṣugbọn bi nnkan ti ṣe n lọ yi,o le ṣe akoba fun iṣakoso eto gbogbo nile asofin paapa julọ aba isuna ti Aarẹ Buhari fẹ gbe wa si iwaju ile asofin lọjọru. Alápinni: Kò sí ẹni to fẹ́ kọ́kọ́ kọ́ iṣẹ́ òṣèré bíi ti àtẹ̀yìnwá",0,yoruba Àṣìṣe IO ńlá %d (%s) lórí ìṣàfihàn '%s'.,0,yoruba "tí Ọba fè joko, Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba "Yàtọ̀ sí èyí, ènìyàn bii ọgbọ̀n ló wá ní ẹsẹ̀ kan ayé ẹsẹ̀ kan ọ̀rún ni onírúurú ilé ìwòsàn ní ìjọba ìbílẹ̀ Ikeduru àti Mbatoli ìpínlẹ̀ náà báyìí nítori wọ́n fa èèfi ẹ̀rọ amúna wá símú. Ìròyìn sọ pé Favour àti Ifeanyi ṣe ìgbéyàwó ìlànà ìbílẹ̀ ní agbolé Uzoegbu Umuomumu Mbieri ní ìjọba ìbílẹ̀ Mbatoli ní ọjọ́ àìkú, ìjàmbá ọ̀hún ṣẹ̀ lẹ́yìn ti ọkọ àti ìyàwó parí gbogbo ètò tí wọn sí kúrò ṣùgbọ́n ti àwọn ẹbi tí ọ̀nà wọ́n jìn pinu láti dúro sùn ní agbolé náà. Lásìkò tí Ezuruke tó jẹ́ olóri ìlú náà ń ṣàlàyè ìṣẹ̀lẹ̀ abúrú ọ̀hún o ní ó hàn gbangba pé èèfí gẹnẹretọ̀ tó ń ṣiṣẹ́ títí di ààrọ ọjọ ajé ní nígbà ti wọ́n fi tipátipá ṣí ìlẹ̀kùn, àwọn kan ti jẹ́ ọlọrun nípè. ""Mo mọ̀ pé kí ṣe ọ̀rọ̀ májèlé oúnjẹ, bíkò ṣe èèfi gẹnẹrátọ̀ ló pá wọ́n , èèfi náà ń kì mọ́ èèyàn láyà, àwọn obi ìyawó wà láàyé sùgbọ́n enìkeji tó jẹ ìbejì fún ìyàwó àti àwọn abúrò rẹ̀ ló bá ìṣẹ̀lẹ̀ náà lọ. Kọmísọ́nà ọlọ́pàá ní ìpínlẹ̀ Imo Rabiu Ladodo tó fi ìdí ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀ ṣàlàyé pé àwọ́n ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí ní pẹrẹwu lóri ọ̀rọ̀ náà. Ladodo ní "" ẹ̀rọ amúná wá náà sì wà ní títàn sílẹ̀ nínú yàrá ìdána títí ilẹ̀ fi mọ tí ilẹkun àti fèrèsé ti àwọn alejo sùn si wà ni títì pa.",0,yoruba "Aworan yi la fi ṣe akawe iya to padanu awọn ọmọ rẹ Awọn ọmọ naa ti wọn jẹ ọmọ ọdun meji ni a gbọ pe wọn ku si inu omi adagun ti wọn ṣe lọjọ si inu ile wọn to wa ni ilu Mbala. Gẹgẹ bi iwe iroyin Vision Newspaper ṣe jabọ, Roman Kato ati Raiding Wasswa n ṣere ninu ọgba ile wọn ni lasiko ti iṣẹlẹ aburu yii waye. Awọn ọmọ ọdọ meji ti wọn n tọju awọn ọmọ naa lawọn agbofinro ti mu lati wadi ọrọ lẹnu wọn. Alukoro ọlọpaa nilu Kampala, Patrick Onyango sọ fun awọn akọroyin pe baba ati iya awọn ọmọ naa ko si nile nigba ti iṣẹlẹ yi ṣẹ. Ìfipábánilòpọ̀: Abiamọ bú sẹ́kún nígbà tí ọkùnrin kan fi tipá bá ọmọ méjì lòpọ̀ Ìjàmbá Ibadan: Abiyamọ tó pọn ọmọ sẹ́yìn kú tọmọ-tọmọ Wọn ni o ṣeeṣe ki o jẹ pe ọkan ninu awọn ibeji naa lo kọkọ jabọ sinu omi ti ikeji rẹ naa si ja sodo nigba ti o n gbiyanju lati doola rẹ. Awọn eeyan ti n ba mọlẹbi Minisita naa kẹdun iku awọn ọmọ rẹ loju opo Twitter",0,yoruba Ọkan tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú.,0,yoruba wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba kakaaki. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba ènìyàn yì í tún ṣe àwọn iṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "Ènìyàn 89 ló ti lùgbàdì COVID - 19 ní Greece , láìsí ẹni tó kù .",0,yoruba "Ajọ eto ilera lagbaye WHO ti kede orilẹede Naijria gẹgẹ bii orilẹede ti ọpọ awọn eeyan ti lugbadi aisan iba ju lagbaye pẹlu orilẹede Democratic of Congo. WHO, ninu atẹjade rẹ to fi lede nipa aisan iba fun ọdun 2021, ni Naijiria ati Congo ni aisan iba naa ti ba awọn eeyan finra ju lagbaye. Atẹjade naa ni Naijiria ni ida Mọkanlelọgbọn eeyan lagbaye ti wọn ku nipa sẹ aisan iba, DRC ni ida mẹtala (13) lagbaye, ti awọn orilẹ-ede meji miiran ti o tẹle e lẹyin Niger Republic ni ida mẹrin (4) ati Tanzania, ida Mẹrin ninu ida Ọgọrun. Nigba to boju wo ipa  ti aisan COVID-19 ko lagbaye lọdun 2021, ajo naa sọ pe iye awọn ti aisan iba ti wọn ni pọ ju bo ṣe yẹ lọ. Ninu akọsilẹ miiran, awọn to lugbadi aisan iba jẹ miliọnu mẹtadinlaadọtalenigba ti awọn to baa lọ si le ni ẹgbẹrun Mẹsan lọdun 2021. Eyi ṣafihan ilọsoke ninu awọn to lugbadi aisan iba ti o jẹ miliọnu meji ti idinku  si ba awọn ti wọn ba aisan naa lọ nigbati aisan COVID-19 bẹrẹ  ni ọdun 2021 sì Millionu Mẹfa. Ninu abọ iwadii ti ajọ ọhun, ida Mẹrindinlọgọrun lo pade iku nipasẹ aisan iba ninu orilẹede mọkandinlọgbọn kari aye. Awọn orilẹede mẹrin ni o ko  idaji gbogbo awọn tiku pa nipasẹ aisan iba ni agbaye  lọdun 2021: Nigeria (31%), Democratic Republic of Congo (13%), Niger (4%), ati United Republic of Tanzania (4%).  ” \n\nAjo WHO lọdun 2021, pin awọn apo to ni ogun Ẹfon lara laarin ọdun yii eleyi ti o to miliọnu Mejidinlaadoje niye.",0,yoruba Olùwo lọ. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó ṣe pàtàkì.,0,yoruba "mú, Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba "ó pa Bàbá lo ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba O ti gbọ́ wípé a máa ń gbé orí ọba Ìbíní wá Ifẹ̀ ńgbàkan! Kí lo rò wípé wọ́n ń fi orí bẹ́ẹ̀ ṣe? #OjoAbaKuLanDiEre #Yoruba #Benin,0,yoruba "ní èyí tí ó jẹ́ kí iye àwọn tó ní ààrùn Corona jẹ́ mẹ́tàléláàdọ́rinléníẹgbẹ̀rin ( 873 ) , nigba ti awọn eniyan bi mẹ́tàdínnígba ( 197 ) ti gba iwosan , ti awọn eniyan márùndínlọ́gbọ̀n ( 25 ) ṣi ti jẹ Ọlọ́run nípè .",0,yoruba tún àwọn ọ̀rọ̀ wọ̀nyí kọ ní ìlànà àkọtọ́ èdè yorùbá ọdúnun aiyé ọ̀ttà oshòdì,0,yoruba "Ọmú mímun fún ọmọ́ ṣíṣe kọjáa kí ọpọlọ ọmọ́ jí pépé, àìsàn tàbí aàrùn kò ní ṣọmọ, ọmọ ò ní kú ní kékeré. #efomoloyan #WBW2016",0,yoruba RT @user: Ogùn(Medicine) ogùn(Charm) Ogun(War) ogùn (State) ogùn(God of iron) ogun(Stab) Ogun(Twenty) ogùn(Sweat) Ogùn(Property) HIT li…,0,yoruba ọkunrin a yi yi ti o pẹ jú nìlọ̀ ni ọ̀nà tí ẹ̀ọ́ kan máa ń gbé ìyẹ̀ alẹ́.,0,yoruba "Olùwo se. Nitori eyi, ara eni lo ni ìgbà mi owó àkokò, Ọba lo ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba irú pálapàla wo lèyí ó ka ohun tí mo kọ lédè yorùbá o wá ń fèsì ní gẹ̀ẹ́sì kí lo sọ ohun tí o kọ ò yé mi,0,yoruba be ni o baba opelope awon obi wa,0,yoruba Yollywood Round up: Àpótí òní páálí láwọn àlejò yóò fí wọlé síbi àpéjẹ̀ ọjọ́ọ́bí Bobrisky,0,yoruba Ìbàdandun ni ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn. (Item 114),0,yoruba ÌWÓ ODÍDẸRẸ́ Where are the ÌWÓ people on this street? Come and listen to your EULOGY 😀. Ẹ̀yin ọmọ ÌWÓ orí àdúgbò yìí dá? Ẹ wá gbọ́ oríkì yin 😀 By/láti ọwọ́ @user https://t.co/wWeitjme9F,0,yoruba joko. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ài: ti o lẹ.,0,yoruba ògúnnágbòngbò ni àwọn yorùbá ń pè é àyálòèdè ni áálọ́ọ̀mù ni wọ́n fi máa ń ní pé ògúnnágbòngbò tí í dátọ́ lẹ́nu ìgbín,0,yoruba Ọba mú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa òkè: ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba Èkó yii nípa ara eni ni nfàn ojú kakaaki. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba "Àfẹ́ẹ̀rí kan ò ju k'á rí igbó ńlá kan bọ́ sí lọ; ẹbọ kan kò ju ọ̀pọ̀ ènìyàn lọ; """"""""""""""""Òrìṣá gbé mi lé àtète"""""""""""""""" kan ò ju orí ẹṣin lọ. #EsinOro🐎 #Yoruba",0,yoruba "Àwọn ìpèníjà òṣèlú tí ó ń kojú wọn ní Hong Kong lẹ́yìn Àkójọpọ̀ Ẹgbẹ́ Alábùradà ; 2014 Umbrella Movement kò ṣe àjòjì sí Chemi Lhamo , ṣùgbọ́n ó bá àwọn ará Hong Kong kẹ́dùn , ó pẹ̀tù sí wọn lọ́kàn pé kò kí wọ́n máà ṣe juwọ́ sílẹ̀ :",0,yoruba Lorileede South Africa ni idije fawọn ọjẹwẹwẹ ti ọjọ ori wọn ko ju ọdun mọkandilogun lọ naa ti o ti gbera sọ lọjọ kọkanlelogun oṣu kini ti n waye. Balogun Ikọ naa lasiko to n ba BBC sọrọ ni idunnu ati ayọ lọ jẹ fun awọn pe awọn ṣe aṣeyọri latyi kopa ninu idije naa bi o tilẹ je pe awọn eniyan ko fi taratara gba ti ere idaraya ọhun. Naijiria yoo ma a koju ikọ Australia ninu ipele akọkọ fun idije agbaye naa. Peter Aho to ṣẹṣẹ pe ẹni ọdun mẹrindinlogun lo gba bọọlu wọnu awọn ti wọn fi bori ifẹsẹwọnsẹ ti wọn fi jawe olubori patapata. Awọn ọmọ ikọ Agbabọọlu Cricket Naijiria ni awọn sa ipa awọn ki awọn le jẹ iwuri fun ikọ ojẹwẹwẹ to n bọ lọna. Wọn fi kun pe awọn ni igbagbọ pe awọn eniyan yoo bẹrẹ si ni fẹran lati ma a wo ẹrẹ bọọlu Cricket naa bi wọn ti ṣẹ fẹran ẹrẹ bọọlu afẹsẹgba.,0,yoruba "Ọmọ ìlú lórí ayélujára , Ayobami kéde pé ìgbésẹ̀ NCDC falẹ̀ .",0,yoruba "Ilumọọka elege ara ni agbabọọlu ọmọbibi orilẹede Argentina, Maradona jẹ, koda awọn eeyan kan gbagbọ pe oun ni agbabọọlu to dantọ julọ ninu iwe itan. Maradona wa lati idile ti wọn ko ṣaaba rọwọ fi họri, o si goke agba di agbaọjẹ agbabọọlu kaakiri agbaaye. Maradona gba ami ẹyẹ pẹlu oriṣiiriṣii ẹgbẹ agbabọọlu lorilẹede Argentina, Italy ati Spain. Eyi ti ọpọ eeyan ko le gbagbe laelae ni idije ife ẹyẹ agbaye eyi ti Maradona gba pẹlu orilẹede rẹ lọdun 1986. Lara awọn abawọn ti awọn eeyan ṣaaba maa n tọka si ni mimu oogun oloro ati ọti lile nigba to n gbabọọlu. Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ Ohun mẹwaa pataki to yẹ ki o mọ ree nipa Diego Maradona 1. Maradona gbarada nigba to gba ami ẹyẹ liigi ọjẹwẹwẹ Argentina pẹlu ẹgbẹ agbabọọlu Boca Juniors lọdun 1982. 2. Lọdun 1984, Maradona fi ikọ agbabọọlu Boca Juniors silẹ lọ si Napoli lorilẹede Italy. Oun lo ṣagbatẹru bi Napoli ṣe gba ami ẹyẹ Serie A ti wọn gba lọdun 1987 ati 1990, ami ẹyẹ Serie A meji pere ti wọn gba ninu itan wọn. Diego Maradona gba ife ẹyẹ agbaye ọdun 1986 3. Maradona nikan ni balogun ẹgbẹ agbabọọlu to ṣoju orilẹede rẹ fun akoko to pọ julọ. Igba mẹrindinlogun ọtọtọ ni Maradona ṣoju Argentina ninu idije ife ẹyẹ agbaye. 4. Ọmọ ọdun mẹẹdogun ni Maradona wa nigba to bẹrẹ si ni maa gbabọọlu lẹyin to darapọ mọ ẹgbẹ agbabọọlu Boca Juniors logunjọ oṣu kẹwaa ọdun 1979. 5. Ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu keji ọdun 1977 ni Maradona bẹrẹ si ni ṣoju orilẹede Argentina. Maradona lagbabọọlu ti o pegede julọ nidije agbaye ọdun 1986 Ọmọ ọdun mẹrindinlogun lo wa nigba naa, orilẹede Hungary ni Argentina koju lọjọ naa. 6. Ẹgbẹ agbabọọlu Argentinos Juniors ti fi orukọ Maradona sọ papa iṣere wọn, Estadio Diego Armando Maradona ni papa isẹre naa n jẹ bayii. 7. Lọdun 1996, Maradona sọ pe ''mo ti loogun oloro, mo si n loogun oloro, mo si maa loogun lọ laelae.'' Kí lo mọ̀ nípa ìbẹta kan ṣoṣo tí Alaafin Oyo bí? Wọ́n pé ọdún méjìlá báyìí Kílódé tí Ọọni Ife, Oba Ogunwusi kò fi gbọdọ̀ rí ọmọ rẹ̀ tuntun ti Olorì Naomi bí títí di bíi ẹ̀yìn oṣù mẹ́fà? Ilé ẹjọ́ dájọ́ ẹgba mẹ́ẹ̀dóògún fún ọ̀daràn tó jí Iphone ní Kaduna Wo dókítà ọmọ Nàìjíríà tí àgbáyé ń wárí fún nítorí abẹ́rẹ́ àjẹsára COVID-19 Wo ọkùnrin ẹni ọdún 55 tí wọ́n ká agbárí èèyàn mẹ́rin, àti àwọn ẹ̀yà ara mìí mọ́ lọ́wọ́ ní Ogun Ìyàwó wọ sòkòtò fún ayẹyẹ ìgbéyéwò rẹ̀, ní wáhálà bá bẹ́ sílẹ̀ 8. Lọdun 2000, ajọ to n ṣagbatẹru ere bọọlu lagbaaye, FIFA fi ẹbun agbabọọlu to dantọ julọ ninu iwe itan fun Maradona ati Pele orilẹede Brazil. 9. Maradona sọ fun ra rẹ pe Dalma ati Giannina ni ojulowo ọmọ oun nigba ti awọn yoku jẹ aṣiṣe atipe tori owo oun loun fi bi awọn ọmọ yoku. 10. Wọn sọ ẹlẹsẹ ayo Diego Costa to jẹ ọmọbibi orilẹede Brazil to n ṣoju Spain lorukọ Maradona. Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ̀ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí",0,yoruba bíojíojími tún bẹ̀rẹ̀ lọ́la ẹ̀yin tèmi tèmi a kú àjọyọ̀ ọjọ́ òmìnira àtòórọ̀ o ó dáàárọ̀ ọ̀,0,yoruba "fè joko, Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó wáyé..",0,yoruba "Àwọn ọmọ bíbí orílẹ̀ - èdè Nàìjíríà fi orí ẹ̀rọ - alátagbà sọ ohun tí ó ń gbé wọn ní ọkàn , bẹ́ẹ̀ náà ni wọ́n lò ó fi yọ ìjọba lẹ́nu láti pa èròńgbàa rẹ̀ tì àti fún ìfẹ̀hónúhàn :",0,yoruba "Alukoro ileeṣẹ Ọlọpaa ipinlẹ Eko, DSP Elkana Bala ti ṣapejuwe iṣẹlẹ naa gẹgẹ bi iku ojiji ti ko si wa lasan. O ni nkan bii ago kan oru ku iṣẹju mẹẹdogun lọjọ Aiku lo ṣẹlẹ. Iroyin sọ pe oloogbe naa lọ gba yara ni ile itura naa, Graceland Brothel to wa ni agbegbe Moshalasi ni Ejigbo lẹyin ti oun ati ọmọ alaṣẹwo kan jọ leri ẹgbẹrun lọna aadọta naira. Davy ati Amaka jọ leri lati mọ ẹni ti yoo kọkọ dawọọ lẹ ninu awọn mejeji. Bi alaṣẹwo naa ṣe ni olomi lo maa rẹ, ni arakunrin naa fesi pe ""jẹ ka da a le e"". Àwọn ọkùnrin tó wà nínú ayé wa gbúdọ̀ bọ̀wọ̀ fún wa - Adarí FIN Báwo lọ̀rọ̀ ṣe bẹ̀rẹ̀? Ọrẹ oloogbe Davy to ba awọn akọroyin sọ̀rọ̀ lori ipo ti o wa fi hande pe ọ̀rọ̀ yii bẹrẹ nigba ti oloogbe ti leri to fọwọ sọya niwaju awọn ọrẹ rẹ pe oun le lo wakati meji lori obinrin lai simi. Bi wọn ṣe n ba ọrọ naa lọ, kan lara awọn ọrẹ rẹ ni lae ko le ba Amaka mọ oloṣo dan an wo tori wọn ṣe apejuwe rẹ gẹgẹ bi ẹni ti wọn gba lọga ninu ibalopọ. Wọn ni Amaka ti ba awọn ọdọkunrin kan kẹsẹ bọ ṣokoto kan to si jawe olubori. Ṣugbọn o dori akayin o, ni akara ba tu sepo. Davy ko goke naa pada bọ o, ori ẹlẹẹkeje lẹmi ti bọ. 'Inu mi bàjẹ́ nígbà tí mo bí i, odidi oṣù mẹ́ta, mi ò lè gbàdúrà s'Ọ́lọ́run'",0,yoruba ọkunrin ri pe ṣe iyalẹnu wey ti o nuni ti o tẹ.,0,yoruba "àkokò, Ìyá ri Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba ìṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba airijina ni ai ri abuke okere ti eniyan ba rin daadaa yo ri eja to yaro,0,yoruba "Ọmọ t'ó ní t'óun bá dàgbà, orí ẹyẹlé l'òun ó máa fi mu ẹ̀kọ; orí ẹyẹlé ò ní í jẹ́ k'ó d'àgbà. #EsinOro #Yoruba",0,yoruba "AWORAN: Alaafin ilu O·yoô, O·ba Lamidi Adeyemi, ti wa di akoda fun Aare Jonathan ori ade fi Oyo sile lati pade Ebele http://t.co/lauyFY1LMX",0,yoruba Ọmọ jayéjayé tó mọ ayé ń jẹ ni mí èmi kìí ṣe oníjìbìtì – Dbanj,0,yoruba gbe ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọmọ lo se.,0,yoruba "agbègbè tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba Ní ọ̀rọ̀ọ Prem Chand :,0,yoruba ẹ sì ní mùsùlùmí ni àwọn aráa ibí yìí ààwẹ̀ sì wà ńta fa,0,yoruba A kò rí áíkànnù,0,yoruba ilera ṣẹlẹ ni Lagos ti gbogbo eniyan sọ o ṣe pataki. (2022),0,yoruba "Idibo sipo gomina yoo waye ni ọjọ kẹwaa, oṣu Kẹwaa, ọdun 2020. Diẹ lara ohun ti wọn sọ ni yii; Oluwarotimi Akeredolu Iṣẹ pọ niwaju mi ti maa ṣe siwaju nigba tara ilu ba tun dibo yan mi ni eekeji, tori mo ṣẹṣẹ n mu ẹyẹ bọ lapo ni. Oludije fun ẹgbẹ oselu APC, tii sun ṣe gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu lo sísọ loju ọrọ yii lọjọ Isẹgun lasiko to n kopa lori akanse eto lori BBC Yoruba pẹlu awọn Oludije gomina miran nipinlẹ naa, ti akori rẹ n jẹ itakurọsọ pẹlu awọn Oludije nipinlẹ Ondo. Gomina Rotimi Akeredolu fi ogun rẹ gbari pe eto ilera nipinlẹ Ondo ti lọ soke lati igba toun ti de ipo gomina. O ni lasiko to n dahun ibeere lori itakurọsọ BBC Yoruba ni ko si ijọba to ti kọja lọ nipinlẹ naa, to gbe eto lárugẹ to ijọba toun. Akeredolu tesiwaju pé ""mo ti safikun awọn ilu to n jẹ anfaani eto itọju tiya-tomo taa mọ si Mother and Child ti ijọba Olusegun Mimiko fi lélẹ̀. Mo ti ṣe afikun ilu marun miran kun ilu meji to n jẹ anfaani eto itọju tiya-tomo, ti inu ọpọ eeyan si dun sì. ""Akeredolu tun fikun pe oun ti gba ọpọlọpọ awọn dokita si ẹnu isẹ eyi to tun mu kí eto ilera nipinlẹ Ondo túbọ̀ ru gọgọ sì. Akeredolu ni oun yoo tun dabira siwaju si nidi atunse ọna, agbega ile ẹkọ ati ipese awọn ohun eelo amayederun lorisirisi. ""Tí ẹ bá fún mi láyé lẹ́ẹ̀kan síi, máa dá bírà."" Ìlú Ondo ló ń gba owó ìná jùlọ ju àwọn ìlú míràn lọ Gomina Rotimi Akeredolu ti sísọ loju rẹ pe owo ti ijọba oun n na silu Ondo kọja iye ti wọn n na silu miran nipinlẹ naa lọ. Gomina Akeredolu, ẹni to kede pe ile ẹkọ fasiti to wa nilu naa n gba obitibiti owo lapo ijọba. O fikun pe ọpọlọpọ gbese ni ijọba to kọja lọ nipinlẹ naa fi silẹ fun òun, gbogbo rẹ̀ si lawọn n gbọ bukata le lori. Bakan naa lo ni ijọba oun ti n mu iṣẹ ṣe lati satunse awọn opopona to ti dẹnu kọlẹ nilu naa. Owó ilé ẹ̀kọ́ Fáṣítì Ìpínlẹ̀ Ondo ló kéré jùlọ ní Nàìjíríà Gomina Rotimi Akeredolu ti kede pe owo ile ẹkọ fasiti ipinlẹ Ondo lo kere julọ ni Naijiria. Akeredolu, lasiko to n dahun ibeere lori boya afikun yoo wa lori owo ile ẹkọ fasiti ipinlẹ naa to wa nilu Akungba Akoko. Akeredolu ni ijọba oun ti ṣe adinku si owo ile ẹkọ fasiti naa lẹyin ti awọn akẹkọọ fasiti naa ṣe iwadi kaakiri ẹkun ìwọ oorun Naijiria lati mọ fasiti to n sanwo ile ẹkọ to kere julọ. Akeredolu ni awọn akẹkọọ fasiti ipinle naa to wa ni Akungba, ti fara mọ owo ile ẹkọ tuntun naa. O wa gba wọn nimoran lati mase jẹ káwọn oloselu si wọn lọna. Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lóri BBC Yoruba Gomina Ipinlẹ Ondo ti kede pe oun ti pari gbogbo iṣẹ akanse ti oun ba nilẹ, lai pa ikankan ti.. Akeredolu, ẹni to fi ọwọ idaniloju naa sọya lori eto itakurọsọ BBC Yoruba tun ni oun yoo tesiwaju lati pari awọn isẹ ti oun n ṣe lọwọ, tara ilu ba fi dibo yan oun pada. N kò ní jẹ òṣìṣẹ́ ni owó oṣù, tí mo bá wọlé gómìnà ní èkejì Gomina Akeredolu ti kede pe oun ti mu ileri oun ṣẹ lati mase jẹ awọn osisẹ ni owo oṣù.Akeredolu, ni owo osu to fẹ pari yii ni ijọba oun jẹ awọn oṣiṣẹ ipinlẹ naa, ti oun yoo si san.Bakan naa lo fikun pe awọn oṣiṣẹ naa ti gba owo ajemonu ìsinmi lẹ́nu isẹ, ti oun ko si ni jẹ oṣiṣẹ ni owo osu rara, bi wọn ba dibo fun oun sipo gomina ni eekeji. Akanda ẹ̀dá 35 ni mo gbà sẹnu iṣẹ́, màá sì ṣe jù bẹ́ẹ̀ lọ Gomina Ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu ti salaye pe oun ti yan àwọn olóṣèlú sípò igbimo olùdarí Ileesẹ ìjọba dáadáa. Bakan naa lo ni ti oun ba pada sípò, oun yoo túbọ̀ yan oloselu sẹnu isẹ si. Nigba to tun n dahun ibeere lori itọju awọn akanda ẹda, Akeredolu ni oun kii ta awọn akanda ẹda nu rara. ""Ijọba mi lo kọ́kọ́ sedasile Igbimọ oludari fáwọn akanda ẹda, koda mo yan amugbalegbe fun ara mi nitori ọ̀rọ̀ wọn."" Gomina ipinlẹ Ondo tun salaye pe ijọba oun gba akanda ẹda marundinlogoji sẹnu isẹ, ti oun yoo si ṣe ju bẹẹ lọ fun wọn, ti oun ba pada sipo ni ẹkeji. Agbára àwọn bàbá ìsàlẹ̀ ti ń lọ sílẹ ní Nàìjíríà, Ọlọ́run ni bàbá ìsàlẹ̀ mi Gomina Ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu ti ni ilana bi oun ṣe di gomina ti safihan pe oun ko ni gbagbọ rara ninu agbara baba isalẹ. Akeredolu, lasiko to n foju laifi wo amulo baba isalẹ to fojuhan ni Edo, tun fikun pe o foju han gbangba ninu idibo naa pe agbara awọn baba isalẹ ti n lọ silẹ ni Naijiria. Gomina Ipinlẹ Ondo tun fọwọ sọya pe oun ko ni baba isalẹ kankan, Ọlọrun ni baba isalẹ oun. O wa gboriyin fun àjọ eleto idibo lori isẹ takuntakun to ṣe lori eto idibo ni Edo. Nigba to n kadi ọrọ rẹ nilẹ, Akeredolu wa rọ awọn araalu lati wo ọpọlọpọ àṣeyọrí oun ni saa akọkọ, lati dibo fun oun ni ẹkeji nitori oun yoo ṣe bẹbẹ siwaju si. Eyitayo Jegede Àwọn iṣẹ́ mi ko ní ní àlébù kankan Eyitayo Jegede to jẹ oludije ipo gomina ni ipinlẹ Ondo labẹ asia ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party, PDP fesi si idahun awọn eeyan pe iṣẹ akanṣe ti awọn fẹ dawọle yoo fun tagba tọdọ ni iṣẹ. Jẹgẹdẹ ni ọrọ abo n kọ ẹgbẹ oun lominu torinaa ""a maa kọ agọ ọlọpaa, bareke awọn sọja sawọn ilu ti wọn ti n ji eeyan gbe. O tun ni o yẹ ki ofin ipinlẹ jọju, iṣejọba oun yoo si fi ontẹ luu nipa biba awọn lọba lọba ṣiṣẹ. O ni ọrọ abo kii ṣe iṣẹ ọlọpaa nikan. A ó ran àwọn àgbẹ lọ́wọ́ ní Ondo oludije ipo gomina ni ipinlẹ Ondo labẹ asia ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party, PDP, Eyitayo Jegede ni ọrọ awọn agbẹ ko ṣee fọwọ rọ sẹyin ni ipinlẹ Ondo torinaa oun yoo ṣeranwọ fun wọn. Jegede ni agbẹ lo to ida to le ni aadọrin awọn ara Ondo nitorinaa iṣejọba oun yoo ran awọn agbẹ lọwọ lorii eso fun irugbin atawọn nkan to le ṣe moriya fun wọn. SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike Iṣẹ́ tí kò ní àlébù la ó ṣé fún Ondo tẹ́ẹ bá fún mi láyè Araale kan bere pe lọdun mejọ ti Eyitayo Jegede fi ṣiṣẹ gẹgẹ bi agbẹjọro agba ipinlẹ Ondo labẹ iṣejọba Olusegun Mimiko, ki ni iṣẹ apẹrẹ rere to ṣe tawọn le wo mọ ọ lara lati dibo yan an lọtẹ yii. Eyitayo ni lootọ ni oun wa lara ikọ aṣofin Mimoko nigba naa lọhun ti iṣẹ ire awọn ko si parẹ. O ṣalaye pe awa ko gba iṣẹ akanṣe jọ fun awọn ẹbi wa ṣugbọn a pin in ko kan taraale tara oko to tọ si ni. Jegede ni ki wọn ranti gbogbo iranwọ ti awọn ṣe lẹka eto ẹkọ to fi rọ awọn ọmọ ileewe lọrun ti wọn ko si ri alebu kankan lara rẹ. To fi mọ iranwọ lẹka ilera ati ọna titunṣe ni Jegede tẹnumọ to si ni bi wọn ba fun oun laye, wọn o ni ri alebu ninu iṣẹ oun gẹgẹ bii gomina. A ó sanwó ìdánwo aṣewọlé ìwé gíga fásitì fawọn àkàndá Oun ti Eyitayo Jegede ni iṣejọba oun yoo ṣe fun awọn akanda ẹda ni wipe ileewe awọn akanda yoo ri iranlọwọ lọdọ ijọba oun paapaa lori irinṣẹ ti wọn fi n kawe. O tun ni ọpọ wọn lo fẹ wọ ileewe giga bii fasiti ṣugbọn ti ko si owo, ""iṣejọba mi yoo ran wọn lọwọ"". Eyitayo ni awọn akanda to fẹ ṣe ere idaraya naa yoo ri iranwọ. Àwọn ọ̀dọ́ wa yóò màa ríṣẹ́ láì san owó orí Araale kan bere pe ki ni Eyitayo Jegede yoo ṣe nipa ọrọ aje ipinlẹ Ondo. Eyitayo Jegede ni lootọ Covid 19 n ṣọṣẹ lagbaye lọwọ lọwọ, amọ ""lagbara Ọlọrun, a o pese iṣẹ ọwọ pupọ fawọn ọdọ"". O ni awọn olokoowo kekeke, ""o yẹ ki ijọba ran wọn lọwọ kawọn naa le gba eeyan siṣẹ, ki ijọba si ko awọn oniṣẹ aladani wa si Ondo lai san owo ori"". Gbogbo eyi lo ni iṣejọba oun yoo ṣe bi wọn ba dibo fun oun. Mi ò nígbàgbọ́ nínú agbára bàbá ìsàlẹ̀ Jegede ti ni ko sohun kankan to n jẹ baba isalẹ ninu oṣelu. O ni o yẹ ki wọn maa dibo ni alafia ni ki esi si jade bi wọn ba ṣe n ṣe idibo tan. Jegede kasẹ ọrọ rẹ nilẹ pe ""ni ti idibo to n bọ lọna yii, a o ni fi ọmọ ṣe"". Dotun Ojon Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, Oludije yi sọ pe nkan ti oun maa se yatọ ti oun ba jawe olu bori ni ọrọ idaari (leadership) O ni eto idari doju kọ ibi kan da apa kan si ni ipinlẹ Ondo. O sọ pe kii se pe ipinlẹ Ondo ko ni alumọni tabi awọn to kawe daada sugbọn eto idari ku diẹ kaato. O ni awọn fẹ ki awọn ara ilu jẹ adojukọ gboogi awọn to n dari eto ijọba. Nitorin naa o fẹ ki awọn eeyan ipinlẹ Ondo ni adari daada. O ni oye oun ni ipinlẹ Ondo ni lo lasiko yi lati le lọ si ibi giga yatọ si ti tẹlẹ. 'Ti o ba jẹ iriri lọba lootọ o yẹ ki ipinlẹ Ondo ti dagba ju bayi lọ' Oludije ẹgbẹ YPP ti sọ idi ti o se yẹ ki wọn fun awọn ọdọ lanfaani lati se ijọba. O fesi yi ni idahun si ibeere ti eeyan kan fi sọwọ si lori itakurọsọ BBC Yoruba. O sọ pe lootọ iriri se pataki sugbọn o yẹ ki awọn ọdọ ni anfaani lati se ijọba nitori lawọn orileede to ti gun oke agba, awọn ọdọ lo n dari eto. Nkan ti a n ja fun lori baba isale ni eto oṣelu pada wa sẹlẹ ninu eto idibo Edo Oludije ẹgbẹ oselu YPP ti sọ pe ọgbọn ti INEC lo lati fi saseyọri ninu eto idibo Edo jẹ eleyi to bọgbọn mu. Dotun Ajon ni iru nkan bayi ni awọn ọmọ ẹgbẹ oselu YPP ti n pariwo lọjọ to ti pẹ. Ni idahun si ibeere lori igbagbọ ninu agbara baba isalẹ ninu oselu Naijiria o ni awọn oloseelu to saaju ni wọn ni igbagbọ ninu baba isalẹ. Ni ti tawọn ọdọ ode oni, o sọ pe awọn paapa julọ ninu ẹgbẹ YPP awọn ko niigbagbọ ninu baba isalẹ. O kadi ọrọ rẹ ni ikẹyin pe ki awọn ara ilu Ondo yi ọna ti wọn n tọ saaju pada ki nkan baa le yatọ ni Ondo. Adekunle Adeleye Nínú ọrọ tirẹ, Adekunle Adeleye salaya pé gbogbo awọn iṣ ti oun ti ṣe kalẹ nilu Oyinbo, asiko ree lati ko ere rẹ. Adeleye ni ọkan pataki lara nkan ti oun yoo ṣe ni láti mu aabo ilu ati Ounjẹ rọrun fun ara ilu, nitori ọna yii nikan ni ilu fi le tuba ko tunṣẹ Adeleye ni o se pataki lati gbaruku ti isẹ ti eniyan ba ba nílé O fi kun un pe eto Mother and Child ti Mimiko ti se seyin ati awọn opopona ti gomina Akeredolu n se.",0,yoruba eḳọ nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba "Aarẹ ile asofin agba nigba kan ri, Sẹnetọ Iyorchia Ayu ni wọn yan bayii gẹgẹ bi alaga tuntun fun apapọ ẹgbẹ oṣelu PDP bayii. Fun asiko diẹ ni ariyanjiyan ti n waye lori ta gan ni yoo dari ẹgbẹ oṣelu PDP wọ inu saa idibo loriṣiriṣi to n bọ lọna ti yoo si ṣide fun eto idibo apapọ ọdun 2023. Orukọ Sẹnetọ Ayu jade lẹyin ipade ọlọpọ wakati laarin awọn ọmọ igbimọ ẹgbẹ oṣelu naa lẹkun ariwa orilẹede Naijiria, eleyi to waye nile ijọba ipinlẹ Bauchi to wa nilu Abuja. Igbimọ iṣakoso apapọ ẹgbẹ oṣelu PDP ti pin ipo alaga ẹgbẹ oṣelu naa fun iha ariwa.",0,yoruba "Lori ikanni opo Twitter rẹ̀, Aarẹ Buhari sọ pe oun kan bẹ 'Eko Atlantic City' wo ni, dipo lilọ sibẹ lati ṣii. End of Twitter post, 1 Aarẹ Buhari sọ eleyi lẹyin igba ti gomina ipinlẹ Eko, Akinwumi Ambọde, sọ pe Aarẹ Buhari lọ ṣi 'Eko Atlantic City' lori ikanni opo Twitter rẹ. Sugbọn oti yọ ọrọ naa kuro nibẹ. Lati ọdun 2013 ni, Aarẹ tẹlẹri, Goodluck Jonathan, ati Aarẹ Amerika tẹlẹri, Bill Clinton ati gomina ipinlẹ Eko nigba naa, Babatunde Raji Fashola ti ṣii igboro 'Eko Atlantic City' ọhun.",0,yoruba "Ifẹsẹwọnsẹ aṣekagba jẹ eleyi ti ọpọ maa n foju sọna fun ninu idije Afcon to maa n waye nilẹ Afrika. Ti ọdun yii ko yatọ si tatẹyinwa. Koda oju awọn ololufẹ ere bọọlu n bẹ lọna nitori awọn ikọ meji to rapala de aṣekagba yii, ina piti ni wọn. Egypt ati Senegal ni yoo dijọ waako lọjọ Aiku lati mọ ẹni ti wọn yoo de lade Ọba ere bọọlu ni Afrika. Ni bayi, wọn ti gba ifẹsẹwọnsẹ mọkanlelaadọta ninu idije Afcon Cameroon 2021, ti papa iṣere Paul Biya to wa ni Olembe yoo si gbalejo asekagba naa. Ẹ jẹ ki a se agbeyẹwo awọn ikọ mejeeji ati iru aṣeyọri ti wọn ti ni ṣẹyin ṣaaju ifẹsẹwọnsẹ yii. Odu ni Egypt nibi ka maa gba ife ẹyẹ Afcon: Ni meni meji, ba ba ni ka maa ka, Egypt ti gba ife ẹyẹ Afcon ni igba meje ọtọọtọ. Ninu akọsilẹ, ko si orileede miran ni Afrika to sunmọ wọn tabi to gba ife ẹyẹ yii ju wọn lọ. Ọdun 2010 ni wọn gba ife ẹyẹ naa kẹyin pẹlu bi wọn ti ṣe fagba han Black Stars Ghana pẹlu goolu kan sodo ninu aṣekagba. Ninu ifẹsẹwọnsẹ ti wọn gba lati le fi kopa ninu idije Afcon, ta mọ si ''qualifiers'' ami ayo mejila ni wọn ko jọ ninu ifẹsẹwọnsẹ mẹfaa. Wọn lewaju isọri Keje lati le fi kopa ninu idije Afcon 2021. Nigba ti wọn de idije naa, Naijiria da wọn lagbo sina pẹlu goolu kan sodo ninu ifẹsẹwọnsẹ akọkọ isọri kẹrin. Ifidirẹmi yii dabi ẹni pe wọn ko ni tẹsiwaju ṣugbọn wọn gbọnra nu, ti wọn si gbiyanju titi ti wọn fi de aṣekagba. Senegal naa ko kẹrẹ, o ni atamátàsé ati adẹ̀yìnmú gidi: Orileede Senegal le ma gborukọ lori bi ti Egypt ṣugbọn awọn naa kii se aimọ lawujọ awọn orilẹede agbabọọlu ni Afrika. Ninu ifẹsẹwọnsẹ mejila ti wọn gba lera wọn, wọn ko fidi rẹmi ninu wọn. Wọn jawe olubori ninu mẹsan, wọn si gba ọmi ninu mẹta. Goolu mẹrinlelogun ni wọn ti jẹ lati oṣu Keje ọdun to kọja ninu awọn ifẹsẹwọnsẹ ti wọn kopa ninu rẹ, ti goolu mẹfa pere si wọle si awọn wọn. Bi a ba ni ka sọ nipa ikọ to ni atamatase ati awọn adẹyinmu ti ko kẹrẹ rara, Senegal jẹ ikọ to duro wamu wamu. Lọdun yii ohun to wa lọkan wọn ni bi wọn yoo se ṣaseyọri ninu aṣekagba. Lọdun 2002, Cameroon lo fidi wọn rẹmi ninu aṣekagba nipa pẹnariti, ti Algeria naa si gbewuro soju wọn ni Egypt pẹlu goolu kan sodo. Ninu irinajo wọn de aṣekagba lọdun yii, wọn ko jẹ goolu pupọ ni ipele kini ṣugbọn wọn tẹsiwajulati leke isọri keji. Igba ti wọn de abala komẹsẹoyọ ni wọn bẹrẹ si ni pitu. Goolu meji ni wọn fi da bantẹ iya fun Cape Verde lati ọwọ Sadio Mane ati Ahmadou Bamba Dieng. Equitorial Guinea naa gba igbaju ati igbamu lọwọ wọn pẹlu goolu mẹta sookan. Nigba ti Burkina Faso koju wọn ni abala to kangun si aṣekagba, goolu mẹta sookan lawọn naa fi gbara. Nkan to ku bayi ni ki wọn koju Egypt ni aṣekagba. Boya wọn yoo gba ife yẹ Afcon ni igba akọkọ ninu itan orileede wọn. Bo ti lẹ jẹ wi pe orileede meji ni yoo koju ara wọn, orukọ awọn agbabọọlu mejeeji yii, Sadio Mane ati Mo Salah lawọn eeyan n ran lẹnu. Idi ni pe awọn mejeeji jijọ n ṣe ọrọ aje pẹlu ẹgbẹ agbagbọọlu Liverpool nilẹ Gẹẹsi ni. Atamatase lawọn mejeeji, ti wọn si ti jijọ gba ami ẹyẹ agbabọọlu to pegede julọ ni Afrika. Ti Senegal yoo ba bori Egypt, Sadio Mane yoo ni ipa ribiribi lati ko nipa didoju ija kọ awọn adilemu Egypt. Amọ Salah naa ko ni gbẹni wa nitori pe oun naa yoo ja fita fita lati se bii ọkunrin. Ipade wa di ori papa nirọlẹ oni lati mọ irin ti yoo tẹ fun ekeji laarin ikọ Egypt ati Senegal, Sadio Mane ati Mo Salah, ẹ ku oju lọna.",0,yoruba "Niṣe lori ayelujara gbona giri giri lẹyin ti ọgọọrọ eeyan n gba ọrọ naa bi ẹni n gba igba ọti lori Twitter ati Facebook lọjọ Satide. Iroyin kan lo kọkọ sọ pe minisita ọrọ ilẹ okeere, Geoffrey Onyeama ṣalaye pe Aarẹ orilẹede Benin, Patrice Talon sọ erongba rẹ pe awọn ṣetan lati di ipinlẹ kẹtadinlogoji ni Naijiria. Amọ, awọn Naijiria sọ ti inu wọn lori Twitter ati Facebook lori ọrọ naa. Ọpọ eeyan lo sọ pe kaka ki kiniun ṣe akapo ẹkun, ki onikaluku maa ṣe ọdẹ tiẹ lọọtọọ. Wọn ni ọrọ Naijiria gan an ti too gbọ, wọn sọ pe ki orilẹede Benin wa laye rẹ. Sẹnẹtọ Shehu Sani atawọn ọmọ Najiria mii faramọ pe ki Benin Republic darapọ mọ Naijiria. Ṣugbọn Sani ṣe ikilọ pe ẹnikẹni ko gbọdọ tumọ ohun to n ṣẹlẹ lọwọlọwọ ni Naijiria lede Faranse fun awọn eeyan Benin. Ẹka ileeṣẹ ijọba orilẹede Naijiria to n ri si ọrọ ilẹ okeere ti fesi pe ko si ohun to jọ bẹẹ pe Benin Republic fẹ di ipinlẹ kẹtadinlogoji ni Naijiria. Ninu atẹjade to fi sita loju opo Twitter rẹ, ilẹẹṣẹ ijọba naa ni orilẹede Naijiria ko ni erongba lati sọ Benin di ọkan lara ipinlẹ ni Naijiria. Ijọba sọ ninu atẹjade ọhun pe awọn kan lo ṣi ọrọ ti minisita ọrọ ilẹ okeere sọ gbọ. Atẹjade ọhun ṣalaye pe ohun ti Ọgbẹni Onyeama sọ ni pe Aarẹ Muhammadu Buhari ati aarẹ Benin fẹ ki ajọṣepọ to wa laarin Naijiria ati Benin tun dan mọran sii.",0,yoruba "ko ko ko la n rọfa aditi. Wi fun Twita. Dandan ni ki wọn gbọ,tulasi si ni ki wọn gba, tori oun ti a wi fun ọgbọ lọgbọ n gbọ #TwitterYoruba",0,yoruba "OJUMO IRE, Ayo ati Alafiya! Sii Ebi, Ore, Ara Ati Ojulumo Gbogbo. Kii Iku Maa Paa OSU ... Kii A Lee Rii Ohun Mu Kaa ODUN ...! Kii OLORUN Alanu Maa Fii Iso RE Soo Wa ...Kii A Lee Maa Dupe, Nii Igba Gbogbo! ... Fun Ore Ati Aanu RE Nii Ori Gbogbo Wa ...! #Yoruba. #OKAY.",0,yoruba "Ina ti jo dori koko bayii fun akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal, Unai Emery. Ọgọrọ awọn ololufẹ Arsenal ni wọn yabo oju opo ayelujara papaajulọ Twitter, nibi ti wọn ti sọ pe ki Emery kọwọ fipo rẹ silẹ tabi ki Arsenal juwe ile fun un. Agidi ni Arsenal fi gba ọmọ alayo meji si meji pẹlu ikọ agbabọọlu Southampton lopin ọsẹ to kọja ninu idije Premier League. Lẹyin ifẹsẹwọnsẹ naa lawọn ẹgbẹ alatilẹyin Arsenal kan sọ fun awọn alaṣẹ ikọ Arsenal pe ki wọm fọwọ osi juwe ile fun Emery. Ipo kẹjọ ni Arsenal wa bayii lori tabili idije Premier League eleyi to jẹ ki ọpọ alatilẹyin Arsenal maa kọminu. Ẹgbẹ naa ṣalaye pe awọn eeyan bi ọgọrun un mẹfa lo ti kọwọ bọwe pe ki Emery dagbere fun Arsenal. Bakan naa lọpọ eeyan loju opo Twitter n sọ pe o ti to asiko fun Emery lati fipo rẹ silẹ. Ọpọ lo n sọ pe kawọn alaṣẹ Arsenal gba Massimiliano Allegri tabi Mauricio Pochettino lati rọpo Emery gẹgẹ bi akọnimọọgba Arsenal.",0,yoruba dé sí ìbàdandun láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa àwọn ènìyàn: ti o pẹ jú nìlọ̀ ni ọ̀nà tí ẹ̀ọ́ kan máa ń gbé ìyẹ̀ alẹ́.,0,yoruba "Oogun ayederu ma n ṣakoba fun aggọ ara ni Ọga ajọ NAFDAC, Ọjọgbọn Moji Adeyẹye ṣalaye pe ede oyinbo ati Faranse lo wa lara oogun ọhun ti orukọ n jẹ Dukoral. Ọjọgbọn Adeyẹye fikun ọrọ rẹ pe ajọ to n ri si ọrọ ilera lagbaaye, WHO ti ko bi ẹgbẹrun lọna mẹjọ paali ayederu oogun ọhun nilẹ. Okùnrin SARS náà sọ pé òun máa pa èèyàn síbi ni- Aladugbo O ṣapejuwe bi paali ti oogun naa ninu rẹ bayii: 1. Orukọ oogun naa- Dukoral Oral Cholera Vaccine/ Vaccin Oral contre le Cholera 2. Nọmba paali rẹ- KV8262B1 3. Ọjọ ti yoo bajẹ- 2020-04 4. Ile iṣẹ to ṣe e- Valneva Canada Inc. Ọga ajọ NAFDAC ṣalaye pe ile iṣẹ to ṣe ojulowo oogun aarun onigbameji naa ni Valneva Sweden AB, ti awọn eeyan mọ si Crucell Sweden AB tẹlẹ. O fikun un pe ajọ NAFDAC ko fi ontẹ lu oogun kọlẹra Dukoral lorilẹ-ede Naijiria. Bakan naa lo rọ awọn eeyan lati ko ayederu oogun kọlẹra ti wọn ba ri lọ si ile iṣẹ ajọ NAFDAC to ba wa ni tosi.",0,yoruba RT @user: #Yoruba Ilẹ̀ ati Odù - obinrin ni wọn. @user @user https://t.co/0KEnRMtoo9,0,yoruba "📣 New Podcast! """"""""""""""""AWON ASA ATI OOSA ILE YORUBA 2"""""""""""""""" on @user #asa #orisa #yoruba https://t.co/gD0gvxdYNg",0,yoruba RT @user: @user adupe o alaafia ni a wa e ku ijo meta o,0,yoruba Mo gbósuba fun ìwà akínkanjú àti òótọ́ yín sí orílẹ̀ èdè yìí nípa gbígbógun ti ìtànkálẹ̀ ààrùn COVD - 19 tó jẹ́ ìpèníjà ní ìran wa yìí .,0,yoruba "Laipẹ yii ni awọn ajinigbe ṣekupa alaga ẹgbẹ awọn ọmọlẹyin Kristi ni iha Guusu Naijiria. Eyi ati ọpọlọpọ awọn ọmọ Naijira to n la ijinigbe ati iṣekupani kọja lo mu ki ẹgbẹ ọmọlẹyin Kristi lapapọ lorilede Naijira kede iwọde yii. Ijọ Redeem, Chapel of Life, Abuja Ijọ Reedeem, Ọgba Eko Pasitọ ijọ Redeem, Enoch Adejare Adeboye nibi isin idupẹ oṣu keji ọdun eyi to waye ni iya ijọ Redeem to wa ni Ebute Meta, ipinlẹ Eko sọ wi pe ""gbogbo ẹni ti wọn pa lorilẹede Naijiria yala Kristẹni tabi Musulumi gbudọ ṣe pataki si wa"". Prophecy 2020: Adeboye àti Ayọdele sọ nípa ọjọ́ ìwájú 2020 Ijọ Redeem, King's Court, Eko Lẹyin ti Adeboye le adura fun aabo, ipamọ ati alafia fun orilẹede Naijiria ninu isin naa tan lo mẹnu ba ọrọ awọn ti wọn n ṣekupa lorilẹede yii. Latari eyi oni ẹgbẹ CAN ti kede pe ki gbogbo Kristẹni ṣe iwọde lodi si i eyi to pe ni ""irin adura(prayer walk)"". Ninu iwọde ọhun, Pasitọ Adeboye lo ṣaaju awọn ọmọ ijọ rẹ pẹlu patako ti wọn gbe lọwọ pẹlu akọle to sọ wi pe ""Gbogbo kan se iyebiye si Ọlọrun"". Ijọ Redeem, Chapel of Life Area 1, Abuja Ijọ Redeem, Jesus House Parish, Eko",0,yoruba "nípa òkè: ti o nuni ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "RT @user: """"""""""""""""@user: @user ó parí. #Achebe #Soyinka"""""""""""""""" Bi a ko ba gbagbe oro ana, a ko ni r'eni ba s'ere! E je ka g ...",0,yoruba òní.. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa òkè: ti o ní wúlò.,0,yoruba ikán parapọ̀ ikán mọlé ọwọ̀ parapọ̀ di òṣùṣù ọwọ̀ àláàmù parapọ̀ wọ́n fi ọwọ́ ti ògiri ọ̀kanòjọ̀kan èyíòjọèyí àti oríṣìiríṣìi irúfẹ́ àkójọpọ̀ igi tí ó kún fọ́fọ́ sínú aginjù ni ó parapọ̀ di igbó èyí fi múlẹ̀ wí pé igi kan kì í dágbó ṣe,0,yoruba "Ọ̀pọ̀lọpọ̀ Ọmọ - adúláwọ̀ ń sá kúrò nílùú nítorí ebi àti rògbòdìyàn , láti wábi forípamọ́síeek , didi ogúnlémidébí tàbí didi agbélùú ní Àréwá Amẹ́ríkà tàbí ní Éróòpù .",0,yoruba Wá ọ̀rọ̀ tàbí àpólà ní ojú-ìwé náà,0,yoruba "aláìì dé sí ìbàdandun láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Yinka Ayefele: Ìrọ́ ni pé ń kò le ṣe bíi ọkùnrin, mò ń ta pútú dàadáa",0,yoruba "Eniyan gbokere niyi """"""""""""""""@user: Isumo ni la ng mo ise eni.""""""""""""""""",0,yoruba pe ṣe iyalẹnu wey ti o nuni ti o nuni ti o ní wúlò.,0,yoruba "Àrẹ̀mọ Aláàfin #Sango ni #Jakuta, àwọn èèyàn ò fẹ́ràn rẹ̀, iná otẹ̀ tí wọ́n dì mọ́ ọ le, ojoojúmọ́ ni wọ́n fẹ́ pa á. #OdiMeji",0,yoruba ìdílé eléégún ni ògògó táíwò hassan ti wá ẹbí ni wọlé ṣóyínká àti fẹlá kútì ǹjẹ́ o lè sọ ìyàtọ̀ ìdílé àti ẹbí,0,yoruba Ìbàdandun ni ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn. (Item 36),0,yoruba Èsì tí ọ̀pẹ̀lẹ̀ bá mú bọ̀ iṣẹ́ tí a rán an ni Odù Ifá. Odù tuntun sì ní í yọ lọ́dọọdún. #Kojoda #Okudu #YorubaNewYear #AjodunOrunmila,0,yoruba "Alàji lo ni ìgbà mi owó àkokò, Ìyá lo tun se lọ.",0,yoruba "RT @user: #TweetinYoruba oruko mi ni Muyiwa Omotoye, onimo nipa epo robi ati nkan alumoni ile ni mi.",0,yoruba a kọ eḳọ nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó ga.,0,yoruba eḳọ nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ìyá lo lọ.,0,yoruba Àtòjọ àwọn ìṣàmúlò-ètò àìmọ̀,0,yoruba "Ganduje fikun pe ẹru ko ba oun rara, nitori oun mọ pe ẹni to ba wu Ọlọrun l'oun gbe agbara fun. ""Idaniloju wa fun mi nipa atundi ibo yii nitori pe ati ṣe atunṣe si awọn aṣiṣe ti a ṣe lọsẹ meji sẹyin, ṣugbọn mo ti ṣetan lati gba kadara ti n ba kuna, maa si ki ẹni to ba jawe olubori ku oriire nitori mo gbagbọ pe ẹni ti Ọlọrun ba fẹ l'oun gbe agbara fun."" Bawo ni igbaradi ṣe n lọ fun atundi ibo naa? Ajọ eleto idibo INEC nipinlẹ Kano sọ pe oun ti gbaradi fun atundi ibo naa. Alaga ajọ naa, Ọjọgbọn Shehu Risqua sọ fun awọn akọroyin pe ibudo idibo ọrinlerugba din ẹyọkan ni idibo naa yoo ti waye. Bakan naa ni Ọjọgbọn Shehu fikun pe awọn yoo pin awọn eroja idibo lọjọ Ẹti, ati wi pe awọn kọmisana ajọ INEC mẹta mi i lati ipinlẹ Ogun, Kebbi ati Zamfara yoo wa si ipinlẹ Kano lati ran an lọwọ̀ ninu iṣẹ naa. Amọ ṣa, awọn kan to wa nilu Kano n binu pe ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ naa fi atẹjade sita pe ko ni i si lilọ bibọ lati aago mẹfa idaji si mẹfa irọlẹ ọjọ Abamẹta. Ireti awọn eniyan ni pe awọn agbegbe ti idibo yoo ti waye nikan lo yẹ ki wọn o ti pa iru aṣẹ bẹ. Ipinlẹ Kano jẹ ọkan lara awọn ipinlẹ ti atundi ibo gomina yoo ti waye lọjọ Abamẹta. Awọn ipinlẹ to ku ni Sokoto, Benue, Adamawa ati Plateau.",0,yoruba ♪♪ #Nigeria yìí ti gbogbo wa ni ... ♪♪ #SunnyAde #ANewNigeria @user,0,yoruba tún ṣe àwọn iṣẹ́ tí ó tó gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ àti ìbi tí wọn wà.,0,yoruba "Ní igba mi owó àkokò, Ọmọ lo aye àìlẹ̀.",0,yoruba "Ẹ ti rí'bi wọ́n gbé ń jó ijó kan báyìí tí oníjó yóò máa jan ẹsẹ̀ mọ́lẹ̀ láìmoye ìgbà, bẹ́ẹ̀ náà ni á máa ṣ'apá pẹ́lẹ́ngẹ́. #worldmusic #Orin",0,yoruba nígbà tí àwọn tó kàwé gboyè rẹpẹtẹ wà nílú ò ríṣẹ́ tó ní láárí ṣe,0,yoruba "Lọ́sàn-án ganrín-ganrín òní, n ó máa bu omi ẹ̀rọ̀ sí ohun tó le nípa ọ̀pá Ọ̀rànmíyàn. Ẹ máa bá mi bọ̀. #Oranyan #AlayeOro #Yoruba",0,yoruba "@user: @user ogbeni yobamoodua e ti tumo oruko mi fini fini. E ti gbaa ju.""""""""Mo-rí-ohun-kẹ́ :)",0,yoruba wá lẹ̀ẹ̀ní nípa aráyé: ti o nuni ti o nuni ti o nuni ti o nuni ti o lẹ.,0,yoruba "VAT di 7.5% láti 5% lẹ́yìn tí ààrẹ Buhari buwọ́lu àbá ètò ìnáwó Aba ọhun ati aba iṣuna ọdun 2020 ni ile aṣofin gbe lọ siwaju aarẹ papọ ki ọdun 2019 to pari. End of Twitter post, 1 Amọ, Buhari buwọlu aba eto inawo lẹyin ọjọ mẹtadinlọgbọn to ti kọkọ buwọlu eto iṣuna ọdun 2020. Buhari sọ loju opo Twitter rẹ pe o jẹ idunnu fun oun lati buwọlu aba eto inawo nitori aba naa yoo ṣatunṣe ọrọ owo ori. Aarẹ ni aba yii to ti di ofin ni yoo jẹ ki ilana owo ori sisan ni Naijiria wa ni ibamu pẹlu gbogbo agbaye. Aarẹ Buhari ni eyi nigba akọkọ ti aba eto inawo yoo tẹle aba eto iṣuna lati rii pe gbogbo eto lọ bo to yẹ lati igba ti orilẹede Naijiria ti pada si ijọba awarawa lọdun 1999. Ofin yii yoo tun mu ayipada ba owo ori epo rọbi, ibode, owo ori ọja tariifu, owo ori ile iṣẹ ati owo ori awọn araalu lapaapọ. Pẹlu ofin ti aarẹ Buhari buwọlu yii, awọn ile iṣẹ ti ere wọn ko ba to miliọnu mẹẹdọgbọn ko ni maa san owo ori lori ere ti wọn ba jẹ mọ. Ifa Priest: ọdún mọ́kànlá ni mo fi ṣe iṣẹ́ agbejọ́rọ̀ kí n tó gbọ́ràn si Ifá lẹ́nu Bakan naa, owo ori tawọn ile iṣẹ ifowopamọ maa n yọ tẹlẹ lori ẹgbẹrun un kan naira yoo bẹrẹ lati ẹgbẹrun un mẹwaa naira bayii. Eduardo: Mo ń jí mọ́tò pẹ̀lú àwọn ọ̀rẹ́ mi nítorí pé mo fẹ́ di 'Big boy'",0,yoruba aku ara fẹra ku ẹni rere to lọ o dunmi debipe mio le jẹun ẹnu mi òsí,0,yoruba "Eso ni elegede Pumpkin ni Oyinbo npee""""""""""""""""@user: @user kini elegede atipe kini Oyinbo n pe e?""""""""""""""""",0,yoruba "òní.. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba RT @user: E karo ooooooooo. A ji bi! Ire ni fun wa ni opin ose yin o @user #TweetinYoruba,0,yoruba "What fun memories do you have of this iron bed, growing up? Let's hear them 😁 Kíni àwọn ohun tí ibùsùn onírin yìí mú u yín rántí? Ẹ jẹ́ kí a gbọ́ 😁 https://t.co/p7aqlsDBQm",0,yoruba "Kí ìbọn tó gòkè, ọfà tí a ti ẹnu rẹ̀ bọ ewé-iná, idà jọ̀mọ́, àdá ògbó, ọkọ̀ àti kùmọ̀ ni à ń kó r’ojú ogun. #AareOnaKakanfo",0,yoruba RSF to Burundi sí ipò 160 nínú orílẹ̀èdè 180 fún òmìnira oníròyìn — ó fi 15 láti 2015 .,0,yoruba "Àdánwò abẹ́rẹ́ àjẹsára Coronavirus ti AstraZeneca àti Fásitì Oxford ń ṣe lọ́wọ́, ni wọ́n ti dáwọ́ rẹ̀ dúró náà. Ìdí ni pé ọ̀kan lára olùkópa nínú ètò ìdánwò náà ni UK ṣe ṣàìsàn, tí o jọ bi ẹni pé ó jẹyọ lati ara abẹ́rẹ́ ti wọ́n fún -un. AstraZeneca ṣe àfíwé bí wọn 'se dá ìlò abẹ́rẹ́ náà dúró yìí gẹ́gẹ́ bi ǹkan tó tọ́ , tò sì máa ń wáye ni gbogbo ìgbà, pàápàá jùlọ tí àìsàn ti kò ṣee ṣe àpèjúwé rẹ̀ bá ṣelẹ̀. Gbogbo àbájáde abẹ́rẹ́ àjẹsára náà ní àmójútó wà fún ní gbogbo àgbáyé. AstraZeneca-Oxford ní abẹ́rẹ́ àjẹsára to dára jùlọ, nínú gbogbo àwọn n gbiyanju láti ṣe abẹ́rẹ́ àjẹ́sára jákèjádò àgbáyé. Ipele àyẹ̀wò kẹta láti nnkan bi ọ̀sẹ̀ mẹ́ta sẹ́yìn, ti kan ènìyàn tó lé ni ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgbọ̀n ènìyàn láti Amẹrika, UK, Brazil àti South Africa. Ipele abẹ́rẹ́ àjẹsára kẹta yìí sába maa n kan àwọn ẹgbẹ̀lẹ́gbẹ̀ ènìyàn, ó sì le to ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọdún ko tó pari. Ìwé ìròyìn New York Times kede sita pé, àwọn tó fi ara wọ́n sílẹ̀ fún abẹ́ ìdánwo náà ni wọ́n ti ni àrùn transverse myelitis. Èyí ni ààrùn tó maa n dàmú ọ̀pá ẹ̀yin, ó sì tún le yí sí ààrun míràn tó lágbára. Ẹ̀wẹ́, wọ́n kò ti mọ nǹkan to n fa àisàn náà, àwọn olùwádìí aladani naa ti lọ wá ẹ̀dà ọ̀rọ̀ tó ba jẹ́ pé ó jọ mọ́ abẹ́rẹ́ àjẹsára ọ̀hun Bákan ní ààrẹ ilẹ̀ Amerika Donald Trump ti ni, òun fẹ́ kí àbẹ́rẹ́ àjẹsára náà de sí ilẹ̀ Amẹrika kò tó dí ọjọ́ kẹta osù kọkanlá ọdún 2020. Eyi sí ti kó ìpayà bá ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ ilẹ̀ Amẹrika pé, ọ̀rọ̀ òṣèlú fẹ́ bórí ilera àwọn ènìyàn, pàápàá jùlọ lórí ọ̀rọ̀ abẹ́rẹ́ àjẹsára náà. Ní ojọ́ Iṣẹgun, ìgbìmọ̀ ẹlẹ́ni mẹ́sàn tó n ṣeto àbẹ́rẹ̀ àjẹsára náà ń fi ọkàn ara ìlú balẹ̀ pé, ìlànà iṣẹ̀ ìṣègùn àti sáyẹnsì kò ni mẹ́hẹ, bí àwọn ṣe ń wá abẹ́rẹ́ ajẹsára fún Covid-19.",0,yoruba ẹ̀kọ́ dídì yìí ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ẹkọ́: ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó ga jù.,0,yoruba "ìṣẹ́ ni a ní láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba Àwọn olùfẹ́hónúhàn dáná sun ọ̀pọ̀ ṣọ́ọ̀ṣì mẹ́ta àti mọ́ṣáláṣí ní Ethiopia,0,yoruba "Tó bá jẹ́ òótọ́, a óò ṣàfihàn ìṣàfarawé kọ̀ǹpútà ẹja tí ó yípo lórí àwọn pánẹ́ẹ̀lì òòró.",0,yoruba "Election 2019: Afẹ́nifẹ́re pín nítorí Buhari àti Atiku Eyi tẹ siwaju pẹlu ipa pataki ti oloogbe Oloye Awolọwọ pẹlu ẹgbẹ ọmọ oduduwa to yirapada di ẹgbẹ Oṣelu Action group ko ninu idagbasoke oṣelu ilẹ Yoruba titi de ori Afẹnifẹre ati NADECO to jija gbara fun iṣejọba tiwantiwa. Ko si jẹ ohun tuntun lati ri awọn ẹgbẹ aṣiwaju ilẹ Yoruba bii Afẹnifẹre, Igbimọ agba, OPC ati bẹẹbẹẹ lọ lati dide kede ohun ti wọn wo pe o yẹ ni ṣiṣe fun ilẹ Yoruba ni irinajo oṣelu. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ṣugbọn nigba ti ẹgbẹ kan ba tun ti n tako ara rẹ lori ọna ti wọn fẹ tọ tabi fẹ ki Yoruba tọ lasiko oṣelu kan tabi omiiran, o n fẹ amojuto. Ẹgbẹ Afẹnifẹre ni oun ti buwọlu idapada sipo aarẹ fun aarẹ Muhammadu Buhari ati igbakeji rẹ, Yẹmi Oṣinbajo ninu ibo 2019. Agbẹnusọ fun ẹgbẹ naa, Oloye Biọdun Akin-Faṣae lo kede eyi lẹyin ipade kan eyi ti o waye laarin awọn aṣoju ẹgbẹ naa kaakiri ipinlẹ mẹfa ilẹ Yoruba lorilẹede Naijiria ni Gbọngan awọn lọbalọba ni ile ijọba nilu Ibadan. Atiku ni igun ẹgbẹ Afẹnifẹre kan n tẹle Ẹgbẹ Afẹnifẹre ni ọna itẹsiwaju ni oloye Awolọwọ to da ẹgbẹ naa silẹ maa n tọ, idi niyi ti awọn si fẹ fi tẹlẹ aarẹ Buhari nitori pe ""o n sa ipa rẹ bi o ti mọ"" Amọṣa ohun ti o wa n ṣe ọpọ onwoye ni kayefi ni bi ẹgbẹ Afẹnifẹre yii kan naa ti ṣe kede ni ọsẹ diẹ sẹyin pe Atiku Abubakar to jẹ oludije ẹgbẹ oṣelu PDP ni awọn n ba lọ. Ṣugbọn igun Afẹnifẹre to fi atilẹyin han fun Atiku Abubakar ti ṣalaye pe ẹgbẹ afẹnifẹre kan ṣoṣo ni o wa, Alagba Faṣọranti si ni olori ẹgbẹ naa. Nǹkan ti rí bákan lẹ́gbẹ́ Afẹ́nifẹ́re báyìí pẹ́lú bí àwọn àgbà ẹgbẹ́ náà ṣe pínyà lórí àtìlẹ́yìn wọn fún Ààrẹ Buhari ti APC àti Atiku ti ẹgbẹ́ òṣèlú PDP Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ, agbẹnusọ fun Afẹnifẹre, Yinka Odumakin ni awọn oloṣelu ni awọn to korajọpọ lati fi atilẹyin wọn han fun Buhari ati Oṣinbajo kii ṣe Afẹnifẹre. Gẹgẹ bi o ṣe wi, lẹyin oloye Fasanmi, ko si eyikeyi ninu awọn to ṣe ipade ni ilu ibadan ti o wa ninu ẹgbẹ naa. Nibi ọrọ de duro yii, ibeere ti o n gba ẹnu ọpọ bayii ni pe, ewo gan an ni Afẹnifẹre ninu awọn mejeeji yii ati pe ewo gan an ni ki Yoruba o tẹle ninu wọn?",0,yoruba "eyi, ara eni lo ni àṣà yorubá eyti o gbe lori iwa rere.",0,yoruba o fe lo si kuje abi kirikiri aare ti pe awon woli ati aafa si ilu ilorin fun adura,0,yoruba "Kí a tó ó ṣe iṣẹ́ kan tàbí òmíràn, ẹ jẹ́ kí bèrè lọ́wọ́ orí, kí Ajé ba bá wa gbé. Ire Ajé o! #IgbagboYorubaNipaAje",0,yoruba "kan. Nitori eyi, ara eni lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde sí ara ilẹ̀.",0,yoruba "A sọ , a kọ , a p'èdè .",0,yoruba "Ajafẹtọẹni Kunle Wiseman Ajayi lo sọ ọrọ naa fun BBC Yoruba, lẹyin ti minisita fun eto ibaraẹnisọrọ ati ọrọ aje ori itakun agbaye, Isah Pantani sọ pe, ijọba n gbe igbesẹ lati ri dena ki eeyan kan lo ju kaadi ipe mẹta lọ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kunle ni oun to yẹ ki ijọba ṣe ni ko ba awọn awọn ileeṣẹ ibanisọrọ wi lori awọn aṣemaṣe ti wọn n ṣe, paapa bi wọn ṣe ma n ja owo awọn onibara wọn ni ijakuja. O ṣalaye pe, ootọ ni pe awọn eeyan kan n lo ẹrọ ibanisọro lati wu iwa ibajẹ, ṣugbọn ko digba ti ijọba ba gbe gbendeke le oye sim kaadi ti eyan n lo ki eto abo to ṣe dede. Ajafẹtọẹni ọhun tẹsiwaju pe ""Awọn eeyan n ṣe oriṣirisi ibajẹ lai lo ẹrọ ibanisọrọ, ko di igba ti wọn ba sọ pe eeyan kan ko gbọdọ lo ju simu mẹta lọ ki eto abo ilẹ wa to ṣenu ire."" O ni kaka ki ijọba maa fi akoko ṣofo lori iye simu ti eeyan nlo, n ṣe lo yẹ ki ijọba wa nnkan ṣe si iwa jibiti ti awọn ileeṣẹ ibanisọrọ n hu si awọn ọmọ Naijiria. Ajayi lero pe nnkan to le din iwa ibajẹ ku ni ki ijọba mu aye dẹrun fun awọn eeyan, ki wọn si fi ọrọ siimu silẹ. Bo tilẹ jẹ pe siimu kan ṣoṣo ni ajafẹtọ ẹni naa n lo, o ni oye owo ti oun n nna lori ẹrọ ibanisọrọ rẹ loṣu le ni ẹgbẹrun un lọna ọgbọn naira. Amofin agba Dayo Akinlaja ni, labẹ ofin gbogbo ọmọ Naijira ni ẹtọ lati sọrọ bo ṣe wuu, nitori naa, ti eeyan ba ni idi pataki lati ni ju siimu mẹta, ko yẹ ki ijọba sọ pe eeyan ko gbọdọ lo siimu mẹta lọ. O ni ẹni to ba fẹ wu iwa ọdaran lee huwa ọdaran, bo ba n lo kaadi ipe kan tabi ju bẹẹ lọ. Akinlaja sọ pe, iwa ọdaran ko ni nnkan ṣe pẹlu iye siimu ti eeyan n lo. Female Genital Mutilation Day: Ọ̀mọ̀wé kan ní obìnrin tí kò bá dá abẹ́ yóò ṣe ìṣekúṣe O ṣalaye pe oun to yẹ ijọba ṣe ni lati maa lo ẹrọ igbalode lati tọpinpin awọn ọdaran, nitori simu kan to eniyan lati ṣe iṣẹ ibi. Amofin ọhun pari ọrọ rẹ pe ""Ti eeyan ba ni simu meji tabi mẹta, emi o mọ bi iyẹn ṣe lee din iwa ọdaran ku.""",0,yoruba àwẹ ọba. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jẹ́ dára jù...,0,yoruba gbé lọ yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba "RT @user: Ekaro dede omo ile Yoruba, inu mi dun la ti ri pe a n gbe asa wa laruge l'oni. Oduduwa a gbe gbogbo wa 😊 #TweetinYoruba",0,yoruba "@user ẹ káàárọ̀. Ẹ bọ́ sí títìi márosẹ̀ oṣòdì, kí ẹ tẹ̀ ẹ́ tàrà dé #cele, tàbí kí ẹ gba #mile 2 já sí #AgoOkota, kẹ bẹ̀rẹ̀ ọ̀nà :)",0,yoruba "Adajọ agba nipinlẹ Bayelsa, Kate Abiri ti ṣe ibura fun oludije ipo gomina fẹgbẹ oṣelu PDP, Douye Diri gẹgẹ bi gomina tuntun ipinlẹ naa. Ni irọle ọjọ Ẹti ọjọ kẹrinla oṣu lkeji ni ibura naa waye nile iṣẹ ijọba nilu Yenagoa tii ṣe olu ilu ipinlẹ Bayelsa. Bakan naa ni adajọ agba ipinlẹ Bayelsa ṣe ibura fun Sẹnẹtọ fun Lawrence Ewhrudjakpo gẹgẹ bi igbakeji gomina tuntun ipinlẹ naa. Ẹwẹ, ile iṣẹ ti kede ofin konile o gbele ti yoo maa bẹrẹ lati irọlẹ di idaji ọjọ keji nipinlẹ Bayelsa lẹyin tawọn olufẹhonu ati awọn janduku kọlu ile gomina tuntun fun ipinlẹ naa, Douye Diri ti wọn si ba nkan jẹ. Ọga agba ọlọpaa nipinlẹ naa, Uche Anozia lo ṣe ikede naa fawọn akọroyin lọjọ Ẹti. Ọgbẹni Anozia to ṣe ikede naa nibi tawọn ọga ajọ eleto aabo miran naa ti wa nijoko ṣalaye pe alẹ ọjọ Ẹti, ọjọ kẹrinla oṣu Keji yii naa ni eto konle o gbele ọhun yoo bẹrẹ. Ọga ọlọpaa naa ṣe ikilọ pe ẹnikẹni to ba ta felefele laarin aago mẹjọ alẹ si aago mẹfa aarọ yoo foju wina ofin. Niṣe ni ile iṣẹ ijọba ipinlẹ Bayelsa kun fọfọ nigba ti ọga ọlọpaa n ṣe ikede naa. Àwọn jàndùkú kọlu ilé gómìnà ìpínlẹ̀ Bayelsa tuntun, wọ́n ba nkan jẹ́ Iroyin kan to tẹwa lọwọ ni pe awọn olufẹhonu ati awọn janduku kọlu ile gomina tuntun fun ipinlẹ Bayelsa, Douye Diri ti wọn si ba nkan jẹ. Gẹgẹ bi iwe iroyin The Punch ṣe jabọ iroyin, awọn janduku naa ba awọn ọkọ kan ti wọn gbe sinu ọgba ile naa jẹ, ati abala kan lara ile naa. Eyi waye lẹyin ti ajọ INEC fun Diri ni iwe ẹri moyege gẹgẹ bi gomina ipinlẹ Bayelsa. Ọsan ọjọ Ẹti ni ajọ eleto idibo Nigeria, Inec ti fun oludije gomina fẹgbẹ oselu PDP, Sẹnatọ Douye Diri ati igbakeji ni iwe ẹri moyege ibo gẹgẹ bi gomina ipinlẹ Bayelsa. Eyi waye lọjọ lẹyin ipade ti ajọ Inec ṣe nilu Abuja lati jiroro lori idajọ ileẹjọ to ga julọ ni Naijiria to waye l'Ọjọbọ. Ile ẹjọ naa wọgile ibo to gbe oludijẹ ẹgbẹ oselu APC wọle nipinlẹ Bayelsa, to si yẹ ki wọn bura fun lonii. Eyi lo si fidi rẹ mulẹ pe gbogbo igbiyanju oludije fun ipo gomina labẹ ẹgbẹ APC, David Lyon lati sebura wọle bii gomina ipinlẹ Bayelsa l'oni, ọjọ Ẹti lo ti ja si pabo. Ṣaaju ni ajọ eleto idibo naa ni oun ti setan lati gbe iwe ẹ́ri moyege ibo fun oludije ẹgbẹ oselu PDP, Senator Douye Diri ati igbakeji rẹ, Lawrence Ewhruojakpo, gẹgẹ bi ileẹjọ ti paa lasẹ. Lati Ọjọbọ ti ile ẹjọ si ti dajọ ni omi nu ti n kọ awọn eniyan ipinlẹ Bayelsa lori taa ni gomina ipinlẹ Bayelsa ti wọn yoo bura fun loni. Idi ni pe ẹgbẹ oselu APC ati PDP ti n tutọ si ara wọn loju lori ohun ti idajọ ileẹjọ naa sọ, ti ko si tii foju han, ẹni ti wọn yoo bura fun bii gomina ni Bayelsa. Lasiko to n bawọn akọroyin sọrọ nilu Abuja, alaga ẹgbẹ oselu APC, Adams Oshiomole leri leka, to si n tọ ilẹ la pe ko si ẹnikẹni ti wọn yoo bura fun bii gomina ni Bayelsa lonii. Oshiomole ni ""kii se bonkẹlẹ mọ pe ile ẹjọ to ga julọ ti dajọ pe wọn ko lee bura fun David Lyon, bẹẹ si ni ẹni to ni ibo to pọ julọ sikeji ni ki wọn bura fun. Eyi tumọ si pe lati ọla lọ, ko ni si ijọba kankan mọ ni Bayelsa."" O fikun pe oludije fẹgbẹ PDP ko ni ida mẹta ibo to yẹ ninu eto idibo gomina ọhun, ti ọwọja ibo rẹ ko si tan ka ida mẹta ijọba ibilẹ to wa nipinlẹ naa. Amọ agbẹnusọ fun ẹgbẹ oselu PDP, Kọla Ọlọgbọndiyan ni ofo lasan ni ihalẹ Oshiomole nitori ofuutu, fẹẹtẹ, aasa ti ko ni kaun ni. Ẹgbẹ oselu PDP wa n fewe ọmọ mọ Oshiomole leti lati ta kete si ipinlẹ Bayelsa nitori igbinyanju rẹ lati da rogbodiyan silẹ nipinlẹ naa, ti kuna. Bẹẹ ba gbagbe, a mu iroyin wa fun yin pe ile ẹjọ to ga julọ nilẹ wa ti yẹ aga gomina mọ David Ylon, tii se oludije gomina fẹgbẹ APC nidi, ẹni ti ajọ Inec kede pe oun lo moke ninu ibo gomina to waye nipinlẹ naa losu Kọkanla ọdun 2019. Idi ni pe ẹni to jẹ igbakeji Lyon naa, Biobarakuma Degi-Eremienyo, ko ayederu iwe ẹri kalẹ fun ajọ eleto idibo, to si mu ki awọn Lyon ati igbakeji rẹ naa kuna lati lee de ipo gomina. Oni, ọjọ Ẹti lo yẹ ki wọn bura fun Lyon ati igbakeji rẹ naa amọ nibayii, ti ileẹjọ ti kede pe ki wọn gba iwe ẹri moyege ti ajọ Inec fun, ki wọn si kọ iwe ẹri miran fun oludije ẹgbẹ oselu PDP, taa wa ni wọn yoo bura fun bii gomina Bayelsa lonii. Koda, lọwọ aarọ ana ni Lyon ti n se igbaradi fun bi wọn yoo se bura fun bii gomina lonii, ti ko si mọ pe riro ni teniyan, sise ni ti Ọlọrun, bẹẹ ni igun ijọba ẹgbẹ oselu PDP to n dari Bayelsa gan ti setan lati fa ibi ti akoso de duro le Lyon lọwọ.",0,yoruba "lo lọ. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "Dino Melaye gba Abuja lọ fún ìtọ́jú tó péye Dino Melaye wà lọ́nà Abuja fún ìtọ̀jú ara rẹ̀ Agbẹnusọ fún Sinetọ Dino Melaye, Ogbẹni Gideon, ṣalaye fun BBC Yorùbá pé, Dino Melaye ti wa lọna Abuja bayii nitori pe ile ẹjọ ti fi i silẹ ko lọ gba itọju ni Abuja. O ni Adajọ ni ki Dino ṣì wà labẹ ìpamọ́ awọn ọlọ́pàá ni Abuja. O ni àwọn agbejoro Dino Melaye yoo pada si Lokoja lọ́jọ́ Ajé tó m bọ̀, ki won le lọ gba onídúro ọmọ Melaye bí o ti yẹ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ogbeni Gideon ni ìdí ti Adajọ Ajanah ṣe pàṣẹ yìí ni pe ilé ìwòsàn àwọn ọlọ́pàá ti wọn gbe Dino si ni Lọkọja kò ni ohun eelò to tó láti fi tọ́ju Dino",0,yoruba "Won furasi Luca Traini pe o se eniyan mẹfa lọṣẹ Ni owurọ ọjọ kẹta osu keji, Otioto duro ni ibudokọ akero ni ilu Macerata. Ọkunrin Italy kan ti o jẹ ọmọ ọdun mejidinlọgbọn, Luca Traini, lọ si ọdọ rẹ ni Alfa Romeo o si yin in nibọn. Otioto, ti o jẹ onidiri ti wa ninu irora ijamba ibọn lọwọlọwọ bayi. O wa ninu ibanujẹ latari isẹlẹ yi pẹlu. ""Iru wahala bayi ko ye mi rara,"" o sọ. Luca Traini yinbọn si eniyan marun lọjọ yẹn. Ko si ẹni ti o ku ninu wọn, gbogbo wọn ye. Ami oju ọta ibọn ti apaniyan yi fẹ fi pa awn eniyan O farahan pe o se afojusun ẹnikẹni ti o dabi pe wọn wa lati ilẹ Afirika. Kofi Wilson, ti o jẹ ọmọ ogun ọdun lati orilẹ̀ede Ghanan jade l lati lọọ ge irun ori rẹ nigbati o kagbako. O gba ọta ibọn ni aya rẹ. ""A gbọ ti awọn iro ibọn ndun ni akọkọ,"" Wilson rántí. ""Lẹhin awọn iro ibọn akọkọ yi, a ko gbọ nnkan kan mọ"", o sọrọ. Kofi Wilson fara gbọta nigbati o lọ ge irun ori rẹ ""Kii ṣe ipinnu mi lati jẹ dudu [eniyan],"" o tẹsiwaju. ""O jẹ aṣiṣe buburu lati [gbiyanju lati] pa eniyan dudu."" Kofi Wilson ti wa ni Itali fun ọdun mẹta. Ibon yiyan fun un yi ko mu ki o yi okan rẹ pada nipa ọjọ iwaju rẹ. Ko ni ipinnu lati pada si Ghana. ""Emi yoo fẹ lati duro ni Italy, ko da fun igba iyoku aye mi."" Ṣugbọn otitọ ni wipe ọpọlọpọ awọn ọmọ Italy yoo fẹ lati ri pe ki awọn eniyan lọ kuro nilu wọn. Iwọde ifẹhonuhan ti n waye ni awọn agbegbe kan ni orilẹede Italy lori isele yi Awọn ọkẹ mẹrin eniyan ngbe ilu yii. Olori Macerata, (Mayor) Romano Carancini sọ wipe ida mẹsan ninu ọgọrun ninu awọn olugbe ilu naa jẹ awọn aṣikiri tabi arinrinajo.",0,yoruba lojiji. Ọmọ lo ni àṣà ìdílé ni nfàn ojú kakaaki.,0,yoruba "1. Òkè Àgọ́ Òwu, Òkè Olúmọ, Òkè Ọnà. Àdó Èkìtì, Ìyìn Èkìtì, _______ Ìjẹ̀bú Òde, Ìjẹ̀bú Ìliṣàn, Ìjẹ̀bú Igbó. #Ibeere #Yoruba",0,yoruba _Kò sí (lo kókó ètò kọ̀ǹpútà),0,yoruba "Àfi 'bádì' là á ń rí, bó bá jẹ́rọ ẹ ja mi ń rọ. #DemocracyDay2013 #Nigeria",0,yoruba Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó ṣe pàtàkì. (Item 19),0,yoruba ilera ṣẹlẹ ni Eko ti gbogbo eniyan sọ o ṣe pataki. (2018),0,yoruba "tó kún jú, àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba ìwájú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "#iroyin, #yoruba, Ewon osu meta ni Bamidele to jale ni Modakeke n lo o: Tolulope Emmanuel… https://t.co/pnUzRgujZE",0,yoruba "jẹ́ ìlú tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba lojiji. Ọmọ lo ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba kọ. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ àti ìbi tí wọn wà.,0,yoruba Bẹ́ẹ̀ àwọn àwòrán ayẹyẹ ìgbéyàwó ọmọ rẹ̀ rèé rẹpẹtẹ lórí Ayélujára wọ̀nyí. Ẹ̀san ń bẹ.,0,yoruba "@user @user Awa, ani fans to da juwon lo....#Yoruba stay winning https://t.co/iCLcIdEviQ",0,yoruba "Ẹ ṣeun, ẹ sì kú iṣẹ́ ìlú, Èkó ò ní gbàgbée yín. Ó dìgbà o! @user @user http://t.co/L0P7vzhIcs",0,yoruba 10. Èwo ni ó tọ̀nà nínúu gbólóhùn méjèèjì : A. Àkàlàmàgbò kì í pa ọdún jẹ B. Àkànnàmọ̀gbò kì í pa ọdún jẹ #Ibeere #Yoruba #Owe,0,yoruba ".@user ipo giga ti e fi parowa pe ema gbe omo karo ojire si ninu ipolongo ibo aare Nijeria ni odun 2019 da? Se agba ofifo lasan lasan ni? Koda @user ti wa di eni awati ninu ipolongi yin, se apere bi ijoba @user se ma ri re? Ile lapoti joko de idi. Be efe ka ta omo wa lopo",0,yoruba "RT @user: O'oko temi ni Olumide Jokotade. Gbogbo eyin 'o nife si ere boolu, boo loju oja fun egbe agbaboolu yin? #TweetInYoruba",0,yoruba ó jí lówùúrọ̀ oníkuukù ọjọ́ yẹn ó nawọ́ gan ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ alágbèéká rẹ̀ láti kà nípa ìgbòkègbodò ọkọ̀ lórí ibùsùn rẹ,0,yoruba "ìgbà kan. Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "Ní nígbà àkerekere, Olùwo ri Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú. ti A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..",0,yoruba "Ẹ kú ọjọ́ọ eérú o, ẹ̀yin onígbàgbọ́ òdodo #AshWednesday http://t.co/BtDZtWvBaG",0,yoruba "ayé ọ̀ṣun. Nitori eyi, ara eni ni nfàn ojú kakaaki.",0,yoruba RT @user: @user aworan lati ibi idanwo igbani sise NIS #Youthunemployment http://t.co/m6NFrdD9TO http://t.co/d72t5FpXbJ,0,yoruba "Yinka Quadri ni lati igba ti iṣẹlẹ Baba Ijẹsha ti ṣẹlẹ ni awọn ko dakẹ gẹgẹ bi agba ninu ẹgbẹ awọn oṣere ni Naijiria , TAMPAN. Ninu ọrọ rẹ, Quadri ni dajudaju ilẹ Yoruba ko fi aye gba ki nkan ma a daru nigba ti awọn agbaagba wa nibẹ. Yinka Quadri ni: ''Ni ọlọkan o ju ọkan ni awọn agbaagba oṣere n ba Yomi Fabiyi ati Iyabo Ojo sọrọ lati pe fun alaafia lori ọrọ yii'' ''A n pe wọn ni ẹyọ kọọkan bi a ṣe sunmọ wọn si, a ko dakẹ rara'' Ansoogun jagunjagun Iresa Adu Ogbomoso tó máa ń bínú gba ẹbọ- Oloye James Olawale Amọ Yinka Quadri ni ọrọ awọn mejeeji ti wa ni ọdọ awọn alakoso ẹgbẹ awọn oṣere, ti wọn si n gbe igbeṣẹ lori rẹ. Agba oṣere naa fikun wi pe laipẹ yii ni ẹgbẹ yoo sọrọ lori rẹ, ti wọn yoo si fi atẹjade lede. Baba Ijesha yóò ṣì wà látìmọ́lé títí ilé ẹjọ́ yóò fi parí ìyanṣẹ́lódì- Kọmisọ́nnà Ọlọ́pàá Kọmisọna Ọlọpaa ipinlẹ Eko, Hakeem Odumosu ti ni titi igba ti awọn oṣiṣẹ ile ẹjọ yoo pari iyanṣẹlodi wọn ni Baba Ijesha yoo fi wa latimọle. Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko ti sọ pe awọn ko mọ ọ mọ ṣi fi oṣerekunrin, Olanrewaju Omiyinka Baba Ijẹsha, si ahamọ lai gba beeli rẹ. International Nurses Day 2021: Wo ìpèníjà àti àǹfàní inú iṣk nọ́ọ̀sì- Adetokunbo Shaba Kọmisọnna ọlọpaa, Hakeem Odumosu, sọ ọrọ yii gẹgẹ bi esi si iwọde ti akẹẹgbẹ Baba Ijẹsha, Yomi Fabiyi ṣe ni ẹka ileeṣẹ ọlọpaa to n wadii ẹsun ọdaran, Panti, Yaba. Ọjọru ni Fabiyi ati awọn eeyan kan ṣe iwọde naa lati beere fun gbigba beeli Omiyinka. Ṣugbọn ṣa, kọmisanna ọlọpaa naa sọ pe imọran ileeṣẹ eto idajọ lo mu ki awọn o sẹ fi afurasi naa si ahamọ. Eyi ti ko ṣẹyin bi awọn oṣiṣẹ ile ẹjọ ṣe wa ni iyanṣẹlodi. Lasiko iwọde to ṣe, Yomi Fabiyi sọ pe ifiyajẹni ati fifi ẹtọ ẹni dun-un ni bi awọn ọlọpaa ko sẹ gba beeli akẹẹgbẹ oun. Ansoogun jagunjagun Iresa Adu Ogbomoso tó máa ń bínú gba ẹbọ- Oloye James Olawale Ninu alaye rẹ, kọmisanna ọlọpaa sọ pe ileeṣẹ ọlọpaa ti pari iwadii rẹ lori ẹsun ti wọn fi kan Baba Ijẹsha pe o ba ọmọ ọdun mẹrinla ni ibalopọ. ""Nigba ti wọn ṣe iwọde wọn de SCIID, igbakeji kọmisanna to n dari ẹka naa, DCP Adegoke Fayoade ba wọn sọrọ."" ""O sọ fun wọn pe nigba ti a pari iwadii wa, a fi abajade rẹ ranṣẹ si ileeṣẹ eto idajọ fun imọran. Imọran ti wọn si gba wa ni pe ka ṣi fi afurasi naa si ahamọ, titi ile ẹjọ yoo fi bẹrẹ iṣẹ pada."" Ọgbẹni Odumosu ṣalaye pe o ṣe e ṣe ki ileeṣẹ eto idajọ tun ero rẹ pa lori bi Baba Ijẹsha ṣe wa ni atimọle, ti iyanṣẹlodi ẹgbẹ JUSUN, ba fi tẹsiwaju kọja bo sẹ yẹ. O sọ pe awọn oṣiṣẹ ile ẹjọ ti gba lati ma a ṣiṣẹ fun ọjọ mẹta laarin ọsẹ, ti wọn o si ma a fi ọjọ meji to ku yan iṣẹ lodi. ""Ṣugbọn, ti ile ẹjọ ba ṣi fi wa ni titi pa, ileeṣẹ eto idajọ le gbe igbesẹ miran, amọ lọwọlọwọ, imọran ti wọn fun wa ni a n tẹle."" Akomolede ati Aṣa lori BBC Yoruba: Wo díẹ̀ nípa àbùdá Olodumare- Iyabo Ayinde",0,yoruba "@user: o ju moo re ni o @user: Ẹ kú ojúmọ́ o""""""""""""""""ọpẹ́ ni fún bàbá lókè",0,yoruba "ọ̀pọ́lọ̀ ni ìbàdandun àtọ́wọ́dá, àwọn oníṣẹ́ ìṣẹ́ ni a ní nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó ga.",0,yoruba "Ẹ̀bùn pàtàkì yìí wà fún oníbàárà ilé iṣẹ́ méjèèjì , àti pé ní àfikún sí MB ẹgbẹ̀rún 2 tí wọ́n yóò fún wọn , owó ìpè ọ̀fẹ́ fún ìsẹ́jú 15 yóò wà lófò fún pípe èyíkéyìí òpó ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ orílẹ̀ - èdè náà tí ó sì gbọdọ̀ jẹ́ lílò kí ó tó d'ọjọ́ 30 , Oṣù Kẹrin .",0,yoruba "ìyẹ̀ alẹ́. Èyí ni òun tí a ní nípa ire àti ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn ẹ̀kọ́ ọmọ aláwọ̀ wà níṣẹ̀.",0,yoruba "RT @user: Bí ọmọdé bá ṣubú á wo iwájú; bí àgbà bá ṣubú á wo ẹ̀hìn. / Upon falling, a youngster looks ahead (for help); an elder…",0,yoruba ojú onà. ti Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó ṣe pàtàkì. (Item 42),0,yoruba "Dokita kan ti kilọ fun awọn obinrin lati dẹkun ati maa lo ọṣẹ ifọyin, oru to n jade lati ara atupa ati omi gbigbona fun itọju okun to so olubi pọ mọ iya ọmọ. Nigba to n sọrọ pẹlu akọroyin ileeṣẹ iroyin abẹle Punch, dokita naa tun kilọ fun awọn obinrin lati ṣọra fun lilo igbẹ maalu fun itọju okun yii kan naa. O ni nitori o le yọri si aisan, eyii to le yọri si iku aitọjọ irufẹ ọmọ bẹẹ. Dokita ọhun to jẹ adari ẹka kan nile iwosan awọn ̣ọmọ wẹwẹ Massey Street Children Hospital niluu EKo, Olanike Olutekunbi sọ pe itọju okun to so olubi pọ mọ iya ọmọ bẹrẹ lati igba ti wọn ṣẹṣẹ bi ọmọ naa. O ni lẹyin ti wọn ba bi ọmọ ọhun ni wọn maa ge okun naa, wọn si gbọdọ ṣe itọju àpá ibi ti wọn ti ge lori idodo ki kokoro aifojuri ma baa gba ibẹ wọle si agọ ara ọmọ jojolo. Olutekunbi sọ pe ""Okun to so olubi pọ mọ iya ọmọ naa le wú, o si le maa pọn, ati pe kokoro aifojuri le gba ibẹ wọle si agọ ara inu ọmọ tuntun lati inu ẹjẹ."" ""Irufẹ ọmọ bẹẹ le ni aisan 'tetanus' paapaa ti iya rẹ ko ba tii gba abẹrẹ ajẹsara rẹ ṣaaju."" Dokita naa ṣalaye pe inu ewu nla ni irufẹ ọmọ bẹẹ yoo wa ti iya rẹ ko ba kiyesara. Gẹgẹ bii ohun to sọ, o ṣe pataki ki okun to so olubi pọ mọ iya ọmọ wa ni imọtọ fun anfani ọmọ ti wọn ṣẹṣẹ bi. O ni ""Lara awọn nnkan ti awọn eeyan maa n lo lati ṣetọju okun to so olubi pọ mọ iya ọmọ wọn ni igbẹ maalu, atupa, omi gbigbona, agbo, atawọn nnkan mii to lewu pupọ fun ọmọ jojolo."" Lasiko to n da si ọrọ naa, dokita mii, Ayodele Renner sọ pe okun yii lo so ọmọ naa pọ mọ ile ọmọ ninu iya rẹ. Ọmọ naa maa n gba afẹfẹ oxygen lati inu olubi ati okun yii, okun naa lo si jẹ ki ọmọ ọhun wa laaye ninu iya rẹ. O ni ọmọ naa le fara kasa arun ti wọn ba fi ọṣẹ ifọyin ṣe itọju okun to so pọ mọ iya rẹ, nitori naa ki awọn iyalọmọ dẹkun ati maa ṣe bẹẹ.",0,yoruba "Nígbà tí Ìyá fè joko, Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..",0,yoruba "Iroyin sọ pe awakọ ọmọ ọdun mẹrinlelọgbọn k'agbako nipinlẹ Ondo Isẹlẹ naa waye nigba ti awọn ọlọọpa n wa ọkọ kaakiri ni agbeegbe Anyibe titi to fi de ijọba ibilẹ Ayilamọ ni ipinlẹ Benue. Ile isẹ ọlọọpa ipinlẹ naa gba ẹnu agbẹnusọ wọn, ASP Moses Yamu sọwipe lati ibẹrẹ ọdun yii ni ikọlu awọn Fulani darandaran ti n waye lagbeegbe naa, ti ọpọlọpọ ẹmi si ti ba isẹlẹ naa lọ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Arakunrin yamu sọwipe adari ajọ ọlọọpa, Ibrahim Idris ti ran awọn ikọ ọlọọpa to n wa ọkọ ofurufu si agbeegbe naa lati se iwadi ofintoto nipa isẹlẹ naa Agbẹnusọ ile isẹ ipinlẹ Benue naa wa fikun wipe ajọ ọlọọpa yoo sa ipa wọn lati ri wipe ọwọ tẹ awọn asekupani naa, ti wọn yoo si foju wina ijọba.",0,yoruba "lọ, Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ìyá lo mú.,0,yoruba mú yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa iṣẹ́: ti o ní wúlò.,0,yoruba eḳọ nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o lẹ.,0,yoruba nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa iṣẹ́: ti o dara.,0,yoruba "Ekaro o eyin temi,e je ki a ni suuru ati itelorun ki ire le te wa lowo! #TweetinYoruba",0,yoruba si ẹyin alatileyin buhari a rọ yín láti gbaju mọ àṣeyọrí àti ifomoniyanse oludije ẹ̀rí láti sá fihan fún ifesunkani láti ilè okere kii ṣe ọ̀rọ̀ àbùkù,0,yoruba RT @user: Ere idaraya: Akoni mogba fun RealMadrid Ancelotti ti so wipe kodara ki agbe gbogbo ebi fun Balotelli nitori igbakugba LFC @user…,0,yoruba Kò s'ígi t'ó dà bí igi àṣórín; ìrókò ni baba.,0,yoruba "Àwọn ẹ̀ṣọ́ aláàbò ti sọ tajútajú sí àárín àwọn tí kò gbọ́ràn láti tú wọn ká , wọ́n sì kó àìmọye ènìyàn .",0,yoruba BRINGING BACK THE CLASSICS / A MÚ ÀWỌN ORIN AYÉBÁYÉ PADÀ WÀÁ: Káyọ̀dé Fáṣọ̀lá - Bí Pẹ́pẹ́yẹ Bá J'òkúta 🎶 What memory does the song bring back to you? 😀 Kíni orin yìí múu yín rántí? 😀 https://t.co/st3h2kLgGy,0,yoruba "Bakan naa ni ijọba kede pe ki gbogbo awọn oniṣẹ ko ṣee mani naa pada si ẹnu wọn. Olori awọn oṣiṣẹ ni Naijiria, Ọmọwe Folashade Yemi-Esan lo sọrọ naa ninu atẹjade kan to fi sita lọjọ kẹwaa oṣu kẹjọ, ọdun 2020 yii. Ṣaaju akoko yii, awọn oṣiṣẹ lati ipele kẹrinla soke lo ti pada sei ẹnu iṣẹ, igbesẹ naa wa ni nibamu pẹlu akitiyan ijọba lati dena itankalẹ aarun coronavirus. Ọjọ mẹta pere lawọn oṣiṣẹ naa ṣi fi n ṣiṣẹ laarin ọsẹ. Ṣugbọn Yemi-Esan ti sọ pe lati igbayi lọ, awọn oṣiṣẹ yoo maa lọ sibi iṣẹ lati ọjọ Aje si ọjọ Ẹti. Bakan naa lo ṣalaye pe aago mẹjọ lawọn oṣiṣẹ yoo maa wọṣẹ, nigba ti wọn yoo ṣiwọ laago mẹrin irọlẹ. Igbimọ PTF to n ri si ari dena ajakalẹ aarun covid-19 lo gba ijọba nbi imọran tẹlẹ jẹki awọn oṣiṣẹ ijọba lati ipele kejila pada sẹnu iṣẹ. June 21 ni pápákọ̀ òfurufú márùn-ún yóò di ṣíṣí padà - Ìjọba àpapọ̀ Ijoba apapọ ti kede pe, papakọ ofurufu marun-un pere ni oun yoo si lati bẹrẹ iṣẹ pada ni ọjọ kọkanlelogun oṣu kẹfa ọdun 2020. Awọn papakọ ofurufu maraarun ti yoo bẹrẹ iṣẹ ni ti Murtala Muhammed nilu Eko, Nnamdi Azikiwe tilu Abuja, Malam Aminu Kano tilu Kano, Omagwa tilu Portharcourt ati Sam Mbakwe tilu Owerri. Atẹjade kan ti oludari agba fun Ileesẹ to n ṣe akoso eto irinna ofurufu nilẹ wa, ọgagun Musa Nuhu fọwọsi tun salaye pe awọn papakọ ofurufu yoku labẹle yoo si wa ni titipa nigba ti awọn baalu ilẹ okeere naa ko ni raye ba sawọn papakọ ofurufu wa. Nuhu fikun pe, lẹyin ọpọ agbeyẹwo ati aato, diẹ diẹ ni ìjọba yoo si awọn papakọ ofurufu yoku labẹle pada. Bẹẹ ba gbagbe, oṣu kẹta ọdun 2020 ni aarẹ Muhammad Buhari pasẹ pe, ki wọn ti awọn papakọ ofurufu ilẹ wa pa, eyi to wa gẹgẹ bii ara ọna lati dẹkun ọwọja itankalẹ arun Coronavirus ni Naijiria. Airport reopening in Nigeria: Àwọn ìlànà fún ìrìnàjò bàálù tí pápákọ̀ òfurufú bá sí padà ní Nàìjíríà Ajọ to n mojuto igboke-gbodo ọkọ ofurufu ni Naijiria, NCAA, ti gbe ilana ti awọn arinrinajo gbọdọ maa tẹle ti wọn ba ṣi awọn papakọ ofurufu pada Ajọ NCAA sọ pe nibi ti nkan de duro bayii, awọn oṣiṣẹ inu baalu gbọdọ maa wọ aṣọ idaabo bo ara lọwọ aarun, lasiko ti wọn ba wa ninu baalu. Ninu atẹjade kan ti Oludari Agba fun ajọ naa, Captain Musa Nuhu fi ọwọ si, NCAA sọ pe dandan ni fun awọn baalu to ba wọ Naijria lati ilẹ okeere, lati pa gbogbo ilana aabo, idena ati amojuto aarun mọ. Ọjọ kẹtalelogun, oṣu Kẹta, ni ijọba Naijria da eto irinna oju ofurufu duro fun awọn baalu ilẹ okeere, nitori itankalẹ aarun coronavirus. Lara oun ti ajọ NCCA tun sọ ni pe oun ko ni fi awọn oṣiṣẹ inu baalu si iyasọtọ , ṣugbọn wọn gbọdọ maa ṣe ayẹwo Covid-19 ni ọjọ mẹrinla-mẹrinla. Awọn ileeṣẹ baalu si ni yoo san owo ayẹwo naa fun awọn oṣiṣẹ rẹ. Eyikeyi oṣiṣẹ to ba ni i yoo si gba itọju. Awọn nkan miran to tun wa ninu ilana tuntun naa Ṣaaju ni agbẹnusọ fun ajọ ṣe akoso awọn papakọ ofurufu ni Naijiria, Henrietta Yakubu sọ fun BBC pe awọn arinrinajo gbọdọ maa de papakọ ọkọ ofurufu o keretan, wakati mẹta ṣaaju asiko ti baalu wọn yoo gbera. Ajọ naa sọ pe oun n ṣiṣẹ kara-kara lati ṣe eto ti yoo daabo bo awọn arinrinajo, ti papakọ ofurufu ba ṣi pada. Ajọ FAAN ti kọkọ kede pe hun ti fin oogun apakokoro si awọn papakọ ọkọ ofurufu, ṣaaju ki wọn o to o ṣi wọn pada. Bakan naa lo sọ pe awọn tun ti bẹrẹ si ni fi ami si ilẹ'lẹ papakọ ọkọ ofurufu, lati ṣaami aaye ti eero kọọkan yoo duro si lori ila.",0,yoruba "Ajura wa lọ, ti ijakandi kọ o! Liverpool kọ ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal lẹkọ ti wọn ko le gbagbe ni papa iṣere Anfield lọjọ Abamẹta. A na sare ni Liverpool lu Arsenal ninu ifẹsẹwọnsẹ Premier League nirọlẹ ọjọ Satide. Ami ayo meji sodo ni wọn fi fẹyin Arsenal gbi lẹ ni Anfield. Adilemu, Joel Matip lo kọkọ fori kan bọọlu wọ le Arsenal, ki David Luiz to fa Mohamed Salah laṣọ nigba to fẹ gbayo sawọn, ni rẹfiri ba fọn feere pẹnariti. Salah ko beṣu bẹgba, niṣe lo gba pẹnariti naa wọ le, eleyi to mu Liverpool siwaju pẹlu ami ayo meji sodo. Laipẹ lai jina, Salah tun gbayo sawọn eleyi to jẹ ki Liverpool siwaju pẹlu ami ayo mẹta sodo ti Arsenal ko si ri ọkankan da pada. Amọ, Lucas Torreira gbiyanju lati dayo kan pada nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa ku iṣẹju marun un ko pari. Pierre-Emerick Aubameyang ati Nicolas Pepper to ṣẹṣẹ rọpo mọ Arsenal lanfaani lati gba goolu sawọn fun Arsenal, ṣugbọn wọn ko lo anfaani ti wọn ni.",0,yoruba "ibile. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "@user: Ohoo! O tumo si wipe won a gbe igba meji s'inu yara alaisan. Okan fun igbe, oka fun eebi. E seun a'dupe."""""""""""""""" O ní yẹ̀yẹ́ :)",0,yoruba Ọba lo ni àṣà yorubá eyti o gbe lori iwa rere.,0,yoruba "Amọṣa, ọmọ gomina ipinlẹ Kaduna, ElRufai naa lọ sileewe loni o ariwo si ta. O daju pe ko si bi ariwo owo ileewe sisan ṣe lee dide nitori baba rẹ, gẹgẹ bii gomina ri jajẹ yatọ si pako lawujọ. Ariwo to ta ni pe ileewe ijọba ni ọmọ gomina Elrufai naa ti lọ forukọ silẹ bayii. O daa, ẹ wo bo ṣe ri. Nigba ti baba rẹ, gomina Elrufai n polongo fun idibo rẹ si ipo gomina fun saa keji lo ti fi ẹnu ja ewebẹ sawo fawọn araalu pe bi wọn lee dibo fun oun ti oun wọle, ileewe ijọba ti awọn ọmọ tiwọn n lọ ni ọmọ ti oun naa yoo lọ. Ileri ti gomina Elrufai ṣe ni ọdun naa lọun lo wa muṣẹ bayii nitori, odidẹrẹ awo olokun, boo ba johun gbe, maa johun gbe. Nibayii, Abubakar Al-Siddique El-Rufai ọmọ gomina El-Rufai ti di akẹkọ nileewe alakọbẹrẹ Kaduna Capital School. Baba rẹ gan an lo si faa lọwọ lọ fi orukọ silẹ nibẹ. O daa o, ki wa ni awsn eeyan n sọ lori eyi? Lati igba ti gomina El-Rufai ti kede rẹ naa ni olukuluku ti n wi tẹnu rẹ lori rẹ. Bi awọn kan ṣe n kan saara sii naa ni awọn kan n kan an ni ikuuku. Fun apẹrẹ, J.J. Omojuwa kan sara si gomina El-Rufai lori oju opo Twitter rẹ 'lootọ awọn kan sọ pe o tun ileewe naa ṣe ki o to fi ọmọ rẹ si. Bi o ṣe yẹ ko ri naa niyi nitori ti awọn to dipo ilu mu ba n titori ọmọ wọn mojuto awọn ileewe ijọba, gbogbo wa la o jijọ pọn la nibẹ."" Ni tirẹ, @tissann_ ni, "" O dabi ẹni pe awọn ti ko gbe ninu ipinlẹ Kaduna lo n wo gomina El-Rufai gẹgẹ biiohun gidi kan fun ipinlẹ naa."" bakan naa ni@I_Am_Ilemona koro oju si gomina El-Rufai. o ni pe o na igba miliọnu naira si ileewe ko to ṣee lọ fun ọm rẹ finhan iru ipo ti ileewe naa wa. Ẹ gbọ naa, ki ni ero tiyin. Ẹ lọ soju opo facebook wa ni @bbcnews Yoruba tabi oju opo @bbcnewsyoruba lori instagram ki ẹ fi ero sibẹ. Ire o.",0,yoruba "Nígbà tó kún jú, àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa òkè: ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si.",0,yoruba "Baàlè se. Nitori eyi, ara eni ni nfàn ojú kakaaki.",0,yoruba "Ninu ikede ti ijọba ipinlẹ Kaduna fi sita lọjọ Aje, ọjọ kẹrindinlọgbọn, oṣu Kẹrin, wọn ni wọn ti gbe oku mejeeji lọ si mọsuari, ti wọn si tun ti sọ fun awọn alasẹ fasiti naa. Ọjọ diẹ sẹyin ni wọn kọkọ ri oku mẹta lára àwọn akẹkọọ naa ni abule kan nipinlẹ Kaduna. Kọmisanna fun eto aabo abẹle nibẹ, Samuel Aruwan sọ pe ibanujẹ ni isẹ ibi ọwọ àwọn eeyan naa jẹ fun Gomina Nasir El-Rufai. ""Ibanujẹ ni ikọlu si awọn akẹkọọ ti ko mọ nkankan, lasiko ti wọn n kekọọ wọn fun ọjọ ọ̀la to dara."" Bakan naa ni ijọba ti ránṣẹ ibanikẹdun si ẹbí àwọn akẹkọọ naa. Wọn ti kọkọ ri oku akẹkọọ mẹta ṣaaju Mẹta lara awọn akẹkọọ fasiti Greenfield ti awọn agbebọn kan ji gbe ni ipinlẹ Kaduna ti dero ọrun. Awọn akẹkọọ naa wa lara awọn akẹkọọ ti awọn agbebọn ji gbe ni fasiti aladani naa to wa loju ọna marosẹ Kaduna si Abuja loru ọjọ Iṣẹgun. Nigba to n fidi iroyin naa mulẹ fun awọn akọroyin, kọmiṣọna fun eto abo ati ọrọ abẹle ni Kaduna, Samuel Aruwan sọ pe wọn ti ko oku awọn akẹkọọ naa lọ sile igbokusi. O ni wọn ri oku awọn ekẹkọọ naa ni abule Kwanan Bature, iyẹn lagbegbe ti ko fi bẹẹ jina si fasiti ọhun. Ọjọ Iṣẹgun ọsẹ yii lawọn agbebọn kan ṣadede kọlu fasiti naa ni Kasarami, lẹba oju ọna marosẹ Kaduna si Abuja, ti wọn si ji awọn akẹkọọ kan gbe lọ. Oṣojumikoro kan sọ fun awọn akọroyin pe awọn agbebọn naa ya bo fasiti ọhun, ti wọn si ṣina ibọn bolẹ, ki wọn to ji awọn akẹkọọ naa gbe lọ. Ikorodu cult crisis:A máa gbé Orò síta lọ́jọ́kọ́jọ́ tí ìjà ẹgbẹ́ òkùnkùn bá tún ṣẹlẹ̀- Àwọ Awọn eeyan to n gbe lagbegbe fasiti ọhun sọ pe ile ẹkọ naa, ti gbogbo awọn akẹkọọ rẹ ko ju bii ogoji ko ni eto abo to peye, wọn ni eredi ree to fi rọrun fun awọn agbebọn naa lati kọlu fasiti ọhun. Ẹnu ọjọ mẹta yii ni awọn agbebọn bẹrẹ si n ṣakọlu lemọ-lemọ ni ipinlẹ Kaduna, ti wọn si sọ oju da awọn akẹkọọ. aaaaaaaaaaaaaaa Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin? Àwọn agbébọn tún ti jí ọ̀pọ̀ akẹ́kọ̀ọ́ gbé ní fásitì kan ní Kaduna Awọn alaṣẹ ijọba ipinlẹ Kaduna lapa iwọ oorun ariwa orilẹ-ede Naijiria ti fidi rẹ mulẹ fun BBC pe awọn agbebọn ti ṣigun wọn fasiti GreeFiel University, ileẹkọ fasiti aladani kan nipinlẹ naa ti wọn si ji ọpọ awọn akẹkọọ ko lọ. Awọn ọlọpaa pẹlu ni awọn agbebọn naa ya wọ Ileewe giga fasiti naa ti o wa lagbegbe opopona Kaduna si Abuja ni aṣalẹ ọjọ Iṣẹgun ogunjọ oṣu kẹrin ọdun 2021. Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Kaduna Mohammed Jalige ṣalaye pe ni bi a ṣe n sọrọ yii, awọn ọlọpaa ko tii le sọ ni pato iye awọn akẹkọs ti wọn ko lọ tabi ibi ti wọn ko wọn gba. O ni ""awọn ọlọpaa ti wa lọgba ileewe naa bayii awọn si ti n beere fun iwe iforukọ silẹ awọn akẹkọọ nibẹ lati lee mọ iye awọn akẹkọọ ti awọn agbebọn naa jigbe salọ"" Inu yara awọn akẹkọọ naa ni wọn ti ji wọn gbe, okunrin ati obinrin pẹlu. Akomolede ati Aṣa lori BBC Yoruba: Ẹ̀yà Ara Ifọ̀ ní olùkọ́ Adedokun kọ́ wa",0,yoruba Mó kí ẹ̀yin ti #America kú ìdìde. Ṣẹ́ẹ jí dáadáa?,0,yoruba "Bẹẹ ni ọrọ ri lori aba eto isuna ipinlẹ Oyo fọdun 2021, eyi to fa ede aiyede laarin gomina Seyi Makinde ati ile asofin ipinlẹ Oyo. Bẹẹ ba gbagbe, ọjọ Kẹrindinlọgbọn osu Kọkanla ọdun 2020 ni Makinde gbe aba isuna ọdun to n bọ kalẹ siwaju awsn asofin lati yiiri wo, ki wọn si fontẹ lu. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Apapọ owo aba isuna naa ni biliọnu lọna ọrinlerugba o din mẹwa naira (N266bn), tijọba si n reti abọ ile asofin lori rẹ. Amọ, iwadi BBC Yoruba fihan pe ariwo sọ laarin gomina Makinde ati awọn asofin naa lẹyin ọjọ diẹ lori aba isuna ọhun. Idi ni pe iwadi BBC fidi rẹ mulẹ pe ile asofin fi awọn akansẹ isẹ kan sinu aba isuna naa, eyi ti owo rẹ to biliọnu mẹwa naira, ti apapọ owo aba isuna naa si fo soke lọ si biliọnu lọna ọrinlerugba o din meje naira (N273bn). Sugbọn igbimọ ile asofin to wa feto isuna, ninu awijare rẹ ni, ile ti fi aaye silẹ fun ẹka alasẹ lati gba owoya fi gbọ bukata aba isuna ọhun, eyi to mu ki aba isuna naa ga soke. Ile asofin ni kii se pe awọn de idi fun aba isuna naa, tabi fi owo kun, eyi ti yoo bọ sapo awọn. Amọ Gomina Makinde la gbọ pe o fi apa janu pe nibo ni oun yoo ti ri alekun biliọnu mẹwa naira lati fi gbọ bukata isuna ọhun lasiko ọda owo to n ba ilẹ wa finra yii. Gomina Makinde ni oun ko fẹ ki owo isuna ọdun 2021 naa ga soke debi pe yoo nira lati gbọ bukata rẹ, eyi to le mu alekun ba gbese to wa lọrun ipinlẹ Oyo. Amọ lẹyin o rẹyin, ile asofin ati ẹka alasẹ ipinlẹ Oyo fi ọgbọn agba yanju ede aiyede naa, to si yanju nitubi n nubi. Zlatan: Ọ̀rẹ́ ni mo sìn lọ ‘studio’ tí mo fi bẹ̀rẹ̀ orin lẹ́yìn tí mo kùnà ìdánwò WAEC Igun mejeeji si lo pada gba pe ko ni dara ki wọn se agbekalẹ isuna fọdun to n bọ ti yoo nira lati se amusẹ rẹ, tile asofin si yọ owo gbese to ni oun fi sori aba isuna ọhun, eyi to mu ko ga soke. Lẹyin o rẹyin, ile asofin Oyo fontẹ lu aba isuna ọdun 2021 naa, eyi ti apapọ owo rẹ jẹ biliọnu lọna ọtalerugba naira o le mẹjọ (N268bn).",0,yoruba "Ọdún mẹ́ta ti lọ , ó bani lọ́kàn jẹ́ , ìlérí tí gómìnà àná Arẹ́gbẹ́ṣọlá ṣe láti rí dájú wí pé alífábẹ́ẹ̀tì tuntun náà jẹ́ kíkọ́ ni àwọn iléèwé tí ó ń bẹ ní Ìwọ̀ - oòrùn gúúsù ilẹ̀ Nàìjíríà kò tíì di múmú ṣẹ .",0,yoruba "Fisayo Soyombo lorukọ akọroyin yii n jẹ, o ti figba kan jẹ alamojuto iroyin fun ile iṣẹ iroyin The Cable to si ti ṣe iroyin to tu aṣiri gbigba owo abẹtẹlẹ ninu iṣẹ awọn onimọ ofin nipa iwa ọdaran. Odidi ọsẹ meji ni akọroyin yii lo latimọle tori ati tọpinpin iwa ibajẹ nile iṣẹ naa. Ọjọ marun un lagọ ọlọpaa ati ọjọ mẹjọ lọgba ẹwọn Ikoyi nilu Eko ni o lo. Minisita gboriyin fun iṣẹ arakunrin yii ati ileeṣẹ iroyin The Cable fun iṣẹ takuntakun ti Soyombo dawọle pẹlu ajọṣepọ ilbi iṣẹ rẹ. ""Bi ẹ ba n dupẹ lọwọ ajọ bii EU atawọn ajọ agbaye to ku, itanjẹ gbaa ni yoo jẹ bi a ko ba mọ riri iṣẹ takuntakun ti Soyombo ṣe"". Aregbesola ni Àwọn ọkùnrin tó wà nínú ayé wa gbúdọ̀ bọ̀wọ̀ fún wa - Adarí FIN ""A n mọ riri a si n ṣe ayẹsi akọroyin atọpinpin yii ni ibamu pẹlu ilana ẹkọ fun iṣẹ takuntakun rẹ... Paapaa mo tun gbudọ gboriyin fun ileeṣẹ to ṣe eyi nitori mo rii pe iṣẹ agbajọwọ ni"". Aregbesola tun bu ẹnu atẹ lu bi wọn ṣe maa n ṣe awn ẹlẹwọn lọna aitọ eyi to ni o maa n dina mọ ayipada wọn gẹgẹ bi araalu. O ni ọna kan ti ẹ lee fi ri eeyan to jade lẹwọn tori rẹ si ti pe ni lati kọ ẹni bẹẹ lẹkọ, ""ohun taa si n ṣe nibi niyii"". Àṣà àti ìgbàgbọ́ Yorùbá ni pé òbí wọn máa ń padà wá sáyé",0,yoruba ẹkọ́ ṣẹlẹ ni Ibadan ti gbogbo eniyan sọ o ṣe pataki. (2005),0,yoruba "Minisita Sunday Dare sọ eyi di mimọ ninu atẹjade kan to fi soju opo Twitter rẹ ninu eyi to ti jẹ ko di mimọ pe eto agunbanirọ lorilẹede Naijiria kun ara awọn eroja pataki ti ijọba fi n peeli ikokoọbẹ idagbasoke to loorin fun awọn ọdọ. Ọrọ yii n jẹyọ lẹyin ti iroyin jade pe awọn aṣofin apapọ lorilẹede Naijiria n gbero abadofin kan ti yoo wọgile eto agunbanirọ lorilẹede yii. Abadofin naa ti kọja ipele kika akọkọ ni ileegbimọ aṣoju-aṣofin Minisita f'ọrọ ọdọ ati ere idaraya ni awọn atunto to loorin ti n lọ lọwọ lori eto naa ati pe orilẹede Naijiria ko ni fi awọn ọdọ rẹ silẹ. Lẹ́yìn ọdún méjì tí iná ìjà tí n jó láàrin wọn, Lizzy Anjorin sọ àwọn ẹ̀ṣẹ̀ tí Toyin Abraham ṣẹ̀ ẹ́ Akeredolu, yéé rí Ààrẹ Buhari fín mọ́- BMO Mo máa ń déédé ṣubú lulẹ̀, tẹ́ẹ bá fi ọwọ kàn mí lásán, kódà lójú ọ̀nà márosẹ̀ - Fatimah Ìdí tí àwọn aṣòfin ṣe fẹ fagilé NYSC, ohun táa mọ rèé Abadofin ti awọn aṣofin gbe ka iwaju lori pe ki wọn da eto agunbanirọ duro ni Naijiria ti kọja kika fun igba akọkọ bayii. Iroyin to n gbode kan ni pe aṣofin Họnọrebu Awaji-Inombek Abiante to n ṣoju kun Opobo/Nkoto lo mu aba naa wa gẹgẹ bo ṣe tska si ọrọ iṣoro abo to wa lorilẹede Naijiria ni lọọlọ yii. Ninu abadofin naa, o sọ pe ""ipaniyan to n peleke sii to si kan awọn agunbanirọ naa lawọn ipinlẹ kan nitory awọn ikọlu adigunjale, ija ẹsin ati ẹlẹyamẹya. Ìpayà ní Kano lẹ́yìn tí òṣìṣẹ́ Àjọ NYSC kú lẹ́yìn tó lùgbàdì ààrùn Coronavirus Ajimobi kò ṣe NYSC tó fi di gómìnà, àmọ́ wọ́n yọ mí ní Mínísítà torí ẹ̀ṣùn yìí - Adebayo Shittu Àbọ̀ wá bá ni ọ̀rọ̀ Iyabo Ojo àti Yomi Fabiyi lórí ọ̀rọ̀ bàbá Ijẹsha - Damola Olatunji, ẹgbẹ́ TAMPAN Ọdún 32 ni mo fi ṣiṣẹ́ oko mọ́ ìṣẹ́ tíṣà kí àwọn ọmọ mi le jẹ́ èèyàn, àmọ́ ikú mú Taiwo lọ - Baba Taiwo Asaniyi A ti ń fẹ́ Hausa, Ibo, ó sàn ka jọ ṣe é ní tùbí-ǹ-nùbí lórí ọ̀rọ̀ Nàìjíríà ju ìjà ogun lọ - Ọba Alara ""Ati ileeṣẹ ijọba ati ti aladani, ko si eyi to n gba awọn ọdọ Naijiria to koju osuwọn mọ paapaa bi wọn ṣe n deede da awan agunbanirọ silẹ lawọn ileeṣẹ ni kete ti wọn ba ti pari isinru ilu lai fun wọn ni ireti pe wọn yoo ri iṣẹ"". O ni nibayii, ipenija aabo ti mu ki wọn maa pin awan agunbanirọ si agbegbe wọn gangan eyi to si ba ọkan lara eredi pataki ti wọn fi da eto agunbanirọ silẹ jẹ eyi to jẹ mimu idagbasoke ba irẹpọ laarin awọn ọdọ Naijiria fun isọkan ati ibaṣepọ laarin oriṣiriṣi ẹya. Nibayii, abadofin naa ti ṣaṣeyọri la kika fun igba akọkọ kọja. Ki ni wọn n ṣe ninu eto NYSC gan? Eto isinruulu jẹ eto ọlọdun kan to pọn dandan fun awọn akẹkọja ileewe giga ni Naijiria ti ko ba tii pe ọgbọn ọdun. Ọna ti wọn maa n gba pin wọn ni pe ẹni to ba jẹ ọmọ ẹkun ariwa loke ọya, yoo gba iwe lati lọ si bii iha Guusu Naijria. Ọsẹ mẹta gbako ni wọn yoo fi gba ẹkọ lọdọ awọn oṣiṣẹ afara jologun ki wọn to lọ bẹrẹ iṣẹ ni ileewe, họsibitu, banki, atawọn ileeṣk aladani mii ti ajọ naa ba pin wọn si. Amọ ni asiko yii, wahala aisi aabo lorilẹede ti ṣakoba fun eto yii gẹgẹ bi iroyin wọn n pa agunbanirọ kaakiri ati jiji wan gbe ṣe n peleke sii. Ọ̀rọ̀ Yorùbá Nation ń fa aáwọ̀ láàrin Gani Adams àti Sunday Igboho A kò tíì gbọ́ ohun kan láti ọ̀dọ̀ àwọn ajínigbé tó gbé akẹ́kọ̀ọ́ fásítì wa lọ - FUNAAB Ki ni yoo ti ibi abadofin fifagile NYSC wa? Idahun si ibeere yii ko tii jade toripe o ṣẹṣẹ kọja kika fun igba akọkọ ni. Ki abadofin kankan to le di ofin ni Naijiria, o gbudọ jajabọ gba ipele kika mẹta kọja nile igbimọ aṣofin yoo si tun gba waju awọn igbimọ naa kọja. Lkyin eyi, wan yoo fi ṣọwọ si ile igbims aṣofin agba ti wọn yoo si ni lati gba a wọle ki aarẹ orilẹede to buwọlu u lati di ofin. Eleyi ks ni igba akọka ti wan n gbe ọrọ boya eto naa ṣi wulo siwaju ile fun ijiroro. Amọṣa ọrọ yii ti rin wọ ori ayelujara ti awọn ọmọ Naijiria kan si n to sẹyin pe ki wọn fagile eto agunbanirọ. Ni ijọba ologun ni saa ijọba Ọgagun Yakubu Gowon ni wọn ṣe agbekalẹ eto agunbanirọ lọjọ kejilelogun oṣu karun, ọdun 1973 gẹgẹ bi ọna lati fopin si aala ti ogun ti pa si aarin awọn araalu nigba ogun abẹle to waye laarin ọdun 1967 si ọdun 1970. Awọn ọmọ Naijiria mii ni awọn ko fẹ ki ijọba fagile e tori awọn anfani ti wọn gbagbọ pe o n ti ara rẹ wa fun orilẹede.",0,yoruba "Àkóbá ńlá l'èròja kiní ajílẹ̀ tòun apako wọ̀nyí ń ṣe ẹ̀dá ilẹ̀ ayé gbogbo. Àǹfààní ni wọ́n sọ fún wa, ìdàkejì ò sunwọ̀n. #AyajoOjoIle",0,yoruba ìdílé. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tobi jù lọ ní Afríkà gúúsù.,0,yoruba Mo ki @user wipe won ku ojo ibi o opolopo e ni won o se ni oke eepe. Iwaju ni opa ebiti n re si Iwaju ni e o maa lo,0,yoruba "Iyansẹlodi lẹka ilera orileede Naijiria ki se ohun tuntun mọ Awọn oṣiṣẹ náà, paapa julo, àwọn tó n ṣiṣe ni awọn ile ìwòsan ìjọba àpapọ, ni yóò kọ̀kọ̀ bẹrẹ iyansẹlodi náà. Atẹjade kan lati ọdọ igbákejì alága ẹgbẹ́ náà, Ogbonna Chimela ní, ti ìjọba ba je ki iyanselodi náà tẹsiwaju lẹyìn ọsẹ méjì, gbogbo awọn ile iwosan ìjọba ìpínlè àti tìbílẹ̀ ni yóò darapo mo iyanselodi náà. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Eyi kìí ṣe iyanselodi àkọkọ Losu kẹsán ọdún tó lọ, ní iyanselodi kàn wáyé lórí àfikún owó oṣù, ajemọnu, igbega ati àwọn ẹtọ míràn fún àwọn osíṣe ìlera lorileede Naijiria. Idasẹsile náà mú ìnira ba opo aláìsàn ṣugbọn lójó keje idasẹsile náà, wọn yanjú òrò ọ̀hún ní tunbi n nubi pẹlu ijọba. Ijọba ko ka wa kun Jack Lampang, to je alamojuto eto iroyin fun Johesu ni, ko si nnkan ti ẹgbẹ naa n beere fun, bi ko se ki ijọba fun awọn ni ẹto awon. Johesu ni oun mo wi pe ara yoo ni awọn ara ilu lori idasẹsile naa ''Awọn Dokita nikan kọ ni osise ilera to wa ni Naijiria. Lai pe yi ni ijọba sika adehun ti wọn se pẹlu awọn onimo isegun sugbọn ti ọrọ ba kan ti awa osise to ku, awawi ni wọn ma n so'' Jack ni awọn ti fun ijoba ni anfaani lopo igba lati yanju oro naa lai se pe awọn dase sile. ""A mo wi pe ara yoo ni awọn ara ilu lori idasẹsile nitori re ni alaga wa fi ni ki idasesile naa mo ni awọn ile iwosan ijọba apapo nikan bayi. Bi won ba ko lati sika adẹhun ti wọn se pẹlu wa, awọn ile iwosan ìjọba ìpínlè àti ìbílẹ̀ naa yóò darapo mọ iyansẹlodi náà. '' BBC Yoruba gbiyanju lati ba Minista feto ilera lorileede Naijiria sọrọ sugbọn ẹni to gbe ipe rẹ ni o wa ninu ipade kan. Awọn Dokita ati awọn osise ilera miran ko gba dede iye owo kannáà. Ìjà orogún awọn dokita àti oṣiṣẹ ilera. Losu kẹwa ọdún tó kọjá, awọn Dókítà orileede Naijiria, labẹ àsìá ẹgbẹ onimo isegun sapèjúwe ẹgbẹ àwọn oṣiṣẹ ilera Johesu gẹgẹ bii ""ajo ti ko bofinmu"". Wọn ni ọpọ òun ti Johesu n béèrè fún ko bójú mu. Ọjọgbọn Mike Ogrima, to jẹ Ààrẹ ẹgbẹ onimo ìṣegun ni '' A lòdì sí kí àwọn Dókítà àti oṣiṣẹ ilera jijo ma gba iye owo kannáà. Johesu n bèèrè fún ìbádọ́gba owo láàrin àwọn oṣiṣẹ ilera to ku ati awon Dókítà.''",0,yoruba "Pa ẹ̀fọn, kí ẹ̀fọn tóó pa ọ́ #Kill #Malaria #Iba",0,yoruba #Repost @user with @user ・・・ A ó máa retí àwọn ìbéèrè yín o... . . . . . . . . . . . . . #yoruba #BBCNewsYoruba @user https://t.co/xNsFkhllKf,0,yoruba #Nigeriadecides aku eto idibo o. Ijoba tuntun yio San wa sowo; sanwa somo; sanwa si alafia. A ko ni ri idamu badiloki mo o.,0,yoruba àyàn mọ́ àlàfo àárín yìí ni o n tí a yàn láti òde ọ̀run tí ẹ̀dá kọ̀ọ̀kan wa gbé wa sóde ayé,0,yoruba "Iṣẹ́ ńlá ni @user Ìkànnì O'òduà ń ṣe, òǹwòran lè ka ìròhìn lédè Yoòbá. Ó dùn mọ́ mi nínú gan-an gan-an! #Yoruba https://t.co/AD2SIMtO68",0,yoruba ní nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Bàbá lo tun se joko.,0,yoruba #AwonEniyanIyitiMopadeLodun2012 @user @user @user @user @user odun 2013 yoo san gbogbo wa si ohun rere O,0,yoruba ìṣẹ́ ni a ní láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ọ̀pọ́lọ̀ àti àlàáfíà.,0,yoruba "Ile isẹ ẹ̀rọ ibaraẹnisọrọ Whatsapp ti ni ki awọn 1.5bn eniyan to n lo ki wọn 'update Whatsapp' wọn. Nitori naa, alamojuto whatsapp ti ni ki gbogbo ẹni to n lo whatssap lọ ṣe eto ayipada ti wọn pese pẹlu 'update'. Whatsapp to jẹ wi pe Facebook lo ni i, sọ wi pe awọn aṣebajẹ yii n lepa awọn eniyan kan ni wọn se se eyi, ati wi pe awọn gboogi ni ẹka imọ ẹrọ lo se isẹ naa. Amọ, Facebook ni awọn ti wa wọrọkọ fi sada, ati wi pe ọna abayọ ti de si isoro naa. 'Bí ìrẹsì tèmi Ayinde bá ń pàkùta, kò tọ́ sẹ́nu aláàrù Barrymaade' Facebook ni ‘Israeli security firm NSO Group’, lo se isẹ ibi yii. ọna ti wọn gba ni pe, wọn yoo pe ẹrọ ilewọ rẹ lori Whatsapp, boo gbe e, boo gbe e, ‘spy software’ yoo wo ori ẹrọ ilewọ rẹ, eleyii ti yoo fun wọn ni anfaani lati wo gbogbo ohun to ba wa lori ẹrọ ilewọ rẹ. Ti wọn si parọwa si eniyan to le ni biliọnu kan to n lo ‘Whatsapp’ lati lọ tẹ ‘Update’ ẹrọ ikansiẹni yii ki awọn asebi ma baa ri gbogbo ohun ti wọn n ko pamọ si ori ẹrọ ilewọ wọn.",0,yoruba "mi owó àkokò, Ọmọ lo ni ìgbà mi owó àkokò, Ọba lo ìgbà ọkọ.",0,yoruba "Ẹ wo ìgbésẹ̀ tí ẹ máa gbé láti di ọlọpàá Naijiria bayii. Agbẹnusọ ileeṣẹ awọn ọlọpaa nipinlẹ naa, DSP Abdullahi Haruna lo fi ọrọ naa lede lasiko ayẹwo naa ni Ọjọ Ẹti ni ilu Kano. Haruna ni awọn ti ṣe ayẹwọ fun awọn eniyan to wa lati ijọba ibilẹ ogoji ninu mẹrinlelogoji to wa ni ipinlẹ naa. Wọn fikun un wi pe lara awọn ti wọn ti ṣe ayẹwo fun naa wa lati ijọba ipinlẹ Takai, Tarauni, Tofa, Tsanywa, Tudun Wada, Warawa, Wudil, ati Ungogo Bakan naa ni ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Kano naa ṣeleri lati ṣe ayẹwo awọn ti wọn ba kuna lati wa fun eleyii ti wọn n ṣe lọwọlọwọ laipẹ. Gẹgẹ bi ọrọ agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa naa, gbogbo eto ti to lati ri i wi pe awọn to fẹ darapọ mọ iṣẹ ọlọpaa, ti wọn si wa fun ayẹwo naa tẹle ofin ijinasiraẹni ati awọn ofin miran to rọmọ didena itankalẹ arun Covid- 19. Nigeria Police Recruitment 2020: Àwọn ohun tí ẹ nílò fún àyẹ̀wò ìgbanisíṣẹ́ ọlọ́pàá tí yóò bẹ̀rẹ̀ ní Mon, Aug 24 Ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Eko, Oyo, Osun, Cross River ati Bayelsa yoo bẹrẹ ayẹwo igbanisiṣẹ fun awọn to ti forukọ silẹ lati darapọ mọ ọ bẹrẹ lati ọjo Aje, ọjọ kẹrinlelogun, oṣu Kẹjọ, ọdun 2020. Ninu atẹjade kan to fi lede loju opo Twitter rẹ, ileeṣẹ ọlọpaa ni ayẹwo ọhun yoo waye fun ọsẹ meji gbako. Lara awọn ohun to ni ki awọn eeyan naa mu wa sojuko ti ayẹwo naa yoo ti waye ni yii: 1. Nọmba idanimọ gẹgẹ ọmọ Naijiria, NIN. 2. Ojulowo ati fọtokọpi iwe ẹri ile iwe girama, iwe ẹri ilu abinibi, iwe ẹri to n ṣafihan ọjọ ori, faili funfun meji ati aworan pelebe. 3. Fọọmu iforukọsilẹ 4. Fọọmu oniduro 5. Aṣo penpe funfun ati ṣokoto pelebe to ṣee sare 6. Ibomu. Ileeṣẹ ọlọpaa ayẹwo naa yoo ni ilbanu pẹlu ilana itaketesiraẹni nitori ajakalẹ arun Covid-19 to wa lode. Ẹwẹ, fun awọn to wa ni ipinlẹ Osun, ayẹwo naa yo waye ni awọn ijọba ibilẹ kọọkan ni awọn ọjọ wọnyii: Ọjọ Aje, 24/08/2020 1. Ayedaade 2. Ayedire 3. Atakumosa East Ọjọ Iṣẹgun 25/08/2020 4. Atakumosa West 5. Boluwaduro 6. Boripe Ọjọru, 26/08/2020 7. Ede North 8. Ede South Ọjọbọ, 27/08/2020 9. Egbedore 10. Ejigbo Ọjọ Ẹti, 28/08/2020 11. Ife Central 12. Ife East Ọjọ Abamẹta, 29/08/2020 13. Ife North 14. Ife South Ọjọ Aje, 31/08/2020 15. Ifedayo 16. Ifelodun 17. Ila Ọjọ Iṣẹgun, 1/09/2020 18. Ilesa East 19. Ilesa West Ọjọru, 2/09/2020 20. Irepodun 21. Irewole 22. Isokan Ọjọbọ 3/09/2020 23. Iwo 24. Obokun 25. Odo-otin Ọjọ Ẹti 4/09/2020 26. Ola-Oluwa 27. Olorunda 28. Oriade Ọjọ Abamẹta, 5/09/2020 29. Orolu 30. Osogbo Gbé àwọn ìgbésẹ̀ yìí láti ṣàfikún ìròyìn nípa ará rẹ lójú òpó ìgbanisíṣẹ́ ọlọ́pàá Ileeṣẹ ọlọpaa lorilẹede Naijiria ti kesi gbogbo awọn to n wa isẹ to forukọ silẹ loju opo wọn, lati ṣe afikun iroyin nipa ara wọn ti wọn ti kọ silẹ ṣaaju. Igbaniwọle ṣisẹ ọlọpaa bẹrẹ pẹlu ṣisi oju opo wọn lọjọ Kọkanlelọgbọn oṣu Keje ọdun 2020. Nibẹ ni awọn to n wa iṣẹ pẹlu ọlọpaa yoo fi awọn iroyin nipa ara wọn si . Wo bi o ti ṣele ṣafikun iroyin nipa ara rẹ Kan si oju opo yii: http://www.policerecruitment.gov.ng/ Kọ nọmba idanimọ NIN rẹ si oju aaye ti wọn la kalẹ. Bi o ba ti fi nọmba yi ṣọwọ si aaye naa, o ma ni lati kọ gbogbo iroyin ti wọn n beere silẹ lati le fi ṣafikun eleyi to ti kọ tẹlẹ. Awọn iwe ti o ma ni lati fi ṣọwọ: •Iwe ẹri sabuke akẹkọjade ileewe girama •Iwe ẹri ọjọ ori tabi iwe miran to tọka ọjọ ibi rẹ •Iwe ẹri ọmọ ilu to ti wa eleyi ti oloyinbo n pe ni Certificate of Origin Lẹyin to ba ti fi awọn nkan wọn yi ranṣẹ, tẹ aaye atẹjisẹ, buwọlu laaye ti wọn la kalẹ ki o si fi ṣọwọ. Ri wi pe o tẹ iwe ẹri jade ti yoo ṣafihan pe o ti pari ipele yi ko si ṣakiyesi nọmba idanimọ ti yoo wulo fun ni ipele miran ninu eto igbaniwọle. Tẹ iwe awọn ti yoo ṣe oniduro fun ọ jade. Njẹ o tun ni awọn ibeere miran? Pe sori ago yi 08100004507. Tabi ki o tẹ iwe atẹjiṣẹ si adirẹsi yi loju opo ayelujara e-training@recruitment.gov.ng or support@policerecruitment.gov.ng. Iléeṣẹ́ Ọlọ́pàá ṣetán láti bẹ̀rẹ̀ ètò ìgbanisíṣẹ́ lákọ̀tun Ileeṣẹ Ọlọpaa Naijiria ti kede eto igbanisiṣẹ lakọtun bayii. Wọn ni ẹni ọdun mẹtadinlogun si mẹẹdọgbọn nikan lo ni anfani lati kopa ninu eto naa. Gẹgẹ bi wọn ṣe sọ loju opo ikansiraẹni Twitter wọn pe Bawo ni ẹ ṣe maa fi orukọ silẹ? Ti o ba ṣetan lati kopa ninu eto igbanisiṣe naa, kan si oju opo yii ki o si fi orukọ rẹ silẹ bi o ti yẹ: Ẹ tẹ ni ori ẹrọ ibanisọrọ yin: www.policerecruitment.gov.ng/maintainance tabi ki ẹ kan si : http://policerecruitment.gov.ng/maintanance.html Kete ti ẹ ba ti de ibi yii ni ẹ ki ẹ pese awọn ifitonileti bii ibi ti ẹ ka iwe de, awọn iwe ẹri ti é ni ati bẹẹ bẹẹ lọ bayii: Ṣaaju ni Bashir Ahmed to jẹ olubadamọran si Aarẹ Buhari lori ifitonileti lori ayelujara naa ti kọkọ fi soju opo twitter rẹ nipa eto igbanisiṣẹ naa Diẹ lara awon Amuyẹ ki wọn to gba eeyan siṣẹ ree: Ileeṣẹ ọlọpaa ni ẹni to ba fẹ kopa ninu eto igbanisi iṣẹ naa gbọdọ ni esi idanwo WAEC rẹ pe iṣẹ marun un, Ki o da pe lọmọkunrin tabi lọmọbinrin laini aisan kankan lara. O tun gbọdọ jẹ ọlọpọlọ pipe ti ko ni aisan opolo. Wọn ni alaboyun ko nile ko pa lasiko yii afi to ba bimọ tan. O ko gbọdọ kuru ju iwọn 1.67 fun ọkunrin ati 1.64 fun obinrin to ba fẹ kopa. Fifẹ aya rẹ gẹgẹ bii ọkunrin ko gbọdọ pọ ju iwọn 34 inches lọ. léeṣẹ́ Ọlọ́pàá ṣetán láti bẹ̀rẹ̀ ètò ìgbanisíṣẹ́ lákọ̀tun",0,yoruba ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba "Láìpẹ yii ni fidio jade to ṣe afihan akẹkọbinrin ileewe Federal Girls College Akure to n fọ awọn ẹrọ ibanisọrọ tí àwọn akẹkọ̀ọ́ ń lọ̀. Alukoro ẹgbẹ awọn obi awọn akẹẹkọ ile iwe girama Federal Girls College Akure, Arakunrin Akintunde Akinṣemọla to ba BBC sọrọ fi idi rẹ mulẹ wi pe awọn olukọ naa laṣẹ lati ba ẹrọ ibanisọrọ awọn ọmọ ile iwe jẹ. End of Instagram post, 1 Akinṣemọla ni iwe ofin ijọba apapọ to de eto ẹkọ ni ile iwe alakọbẹrẹ ati girama fi lọlẹ pe ẹru ofin ni ẹrọ ilewọ ni awọn ile ẹkọ, nitori naa ẹnikẹni to ba mu wa si ile ẹkọ ti rufin to de ile iwe girama. O fikun wi pe o ti le ni ọdun meji bayii ti awọn ọmọ ileewe naa ti n mu ẹrọ ibanisọrọ wa si ile iwe ti awọn si ti n gba lọwọ wọn, amọ ti wọn kọ lati jawọ ninu iwa bẹẹ. ‘Awọn ọmọ to ṣẹṣẹ wọle si JSS1 ni ileewe naa lo fi ẹjọ sun awọn ọga ileewe naa pe awọn to je bi agba si wọn ninu ile iwe naa ma n lọ ẹrọ ibanisọrọ ninu yara ti wọn gbe lorun, ti wọn kii si jẹ ki awọn sun ninu yara.’ ‘Awọn olukọ bẹrẹ iwadii lori ẹsun naa, ti wọn si ri orisirisi ẹrọ ilewo ninu ẹru awọn ọmọ ileewe naa.’ Bakan naa ni awọn olukọ fẹsun kan awọn akẹkọọbinrin naa wi pe ọkunrin ni wọn fi ẹrọ ilewọ naa pe, ti wọn a si ma a sọrọ ibalopọ nigba miran. Alukoro ẹgbẹ awọn obi awọn akẹẹkọ ile iwe girama Federal Girls College Akure fikun wi pe awọn olukọ naa fun awọn akẹkọọ ti ọrọ naa kan lati lọ rọkun nile fun igba diẹ, lẹyin naa ni awọn wa pàsẹ fun lati ba ẹrọ ilewọ naa jẹ. Akinṣemola ni awọn akẹkọọ tun n ya ara wọn ninu yara, ti wọn si n gbe si ori ẹrọ ikansiraẹni Facebook, Twitter ati Instagram,eleyii to le fa ijamba abi ijinigbe fun wọn. O ni eyi yoo kọ awọn ọmọ naa lọgbn lati maṣe wu iru iwa yii mọ nitori ọpọ igba ni wọn ti sọ fun wọn ki wọn yee mu u ma si ileewe, nitori yoo fa ifasẹyin fun ẹkọ wọn.akẹkọọ yii. Bawo ni awọn akẹkọọ naa ṣe n ba awọn obi wọn sọrọ nigba ti wọn ko laṣẹ lati lo ẹrọ ibaraẹni sọrọ? Akinsemola ni akẹẹkọbinrin kọọkan lo ni alagbatọ ni ileewe naa, ti wọn lọ ma n ba ti wọn ba ni ohun kan ti wọn ṣe alaini, tabi ti wọn ba n ṣe aisan ti wọn si nilo lati ba awọn obi wọn sọrọ. Bakan naa ni wọn fikun wi pe awọn satide akọkọ ni osoosu ni wọn ma n fun awọn obi laaye lati wa wo awọn ọmọ wọn. O fikun wi pe ileewe Federal Girls College Akure wa lara awọn ileewe to n ṣe daradara julọ lorilẹede Naijiria, ti awọn olukọ naa si n gbiyanju lati ri wi pe ina wọn ko jọ ajorẹyin. Alukoro ẹgbẹ awọn obi awọn akẹẹkọ ile iwe girama Federal Girls College Akure naa wa parọwa si awọn obi naa lati maṣe fun awọn ọmọ wọn ni ẹrọ ibanisọrọ wa si ile iwe, ki wọn ba le foju si ẹkọ wọn, ki wọn si maṣe di awọn akẹkọọ to ku lọwọ.",0,yoruba "Ìbéèrè kan tí ó nílò ìdáhùn ni ti ọ̀nà ìtànkálẹ̀ àrùn yìí : bóyá ó leè rànká láti ara èèyàn kan sí ìkejì , àti ìyè èèyàn mélòó ló leè kó àìsàn yìí látara ẹni tí ó bá ti ní i .",0,yoruba "RT @user: Amin o """"""""""""""""""""""""""""""""@user: Ayée wa á tòrò bíi omi àf'òwúrọ̀ pọn""""""""""""""""""""""""""""""""",0,yoruba Ẹ wa jẹ ẹ̀pà sísè o! Ẹ bá mi re o :) #yoruba http://t.co/lRSR9bkmuo,0,yoruba "kún jú, àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde sí ara ilẹ̀.",0,yoruba àwọn ọmọ ìbàdàn nìyẹ́n o ọmo láyípo,0,yoruba Ìdí tí a fi fẹ́ràn-an rẹ̀ àti ìdí tí a fi nílòo rẹ̀ ju ti àtẹ̀yìnwá lọ ni àkòrí ti 2015. #WorldRadioDay #Yoruba,0,yoruba ẹ̀daèdè yorùbá wo la ti ń fi u bẹ̀rẹ̀ ọ̀rọ̀,0,yoruba Ope o mo pari abala akoko ise yii Eledumare ran mi lowo dele o,0,yoruba "Ní ọjọ́ kẹrin oṣù Èrèlé , Global Voices bá Fernando Gomes , ajìjàǹgbara ọmọ orílẹ̀ èdè Angola tí ó jẹ́ ọ̀kan lára àwọn alátìlẹ́yìn ìfẹ̀hónúhàn náà tàkùrọ̀sọ , láti mọ ohun gbogbo tí ó rọ̀ mọ́ ìṣẹ̀lẹ̀ náà .",0,yoruba Adúpẹ́ p'éran yín ò tú níso. Ẹ dín in dáadáa o :) @user,0,yoruba "Eekan kan ninu ẹgbẹ oselu APC, Joe Igbokwe ti tutọ soke, fi oju gba a lori ikede kan ti awọn agbaagba lẹkun ariwa naijiria fisita lori ẹni ti yoo rọpo aarẹ Muhammadu Buhari. Ẹgbẹ awọn agbaagba ni Ariwa ilẹ yii lo kede ni Ọjọru pe ko si ohun to buru ninu ki aarẹ ti yoo rọpo Buhari tun wa lati ẹkun ariwa orilẹede yii. Baba Ahmed, tii se agbẹnusọ fun ẹgbẹ awọn agbaagba naa fikun pe ẹkun ariwa Naijiria ko tii setan lati gbe ipo agbara silẹ lọdun 2023. O wa gba awọn eeyan ti igbesẹ naa ko ba tẹ lọrun niyanju lati fi Naijiria fun awọn. Amọ nigba to n fesi lori ọrọ yii, Igbokwe ni ọrun yoo ya bọ silẹ, ti ohun buruku yoo si maa ja lu ohun buruku, ti eeyan miran lati apa ariwa Naijiria ba tun rọpo aarẹ Buhari. Igbokwe, ẹni to fi ọrọ naa lede loju opo ayelujara rẹ ni oun gbọ ohun ti Baba Ahmed sọ o amọ ọrun yoo bọ silẹ o. Ọpọ ọmọ Naijiria si lo ti dara pọ lati maa tako ohun ti ẹgbẹ awọn agbagba Arewa sọ naa, tawọn gomina ẹkun guusu Naijiria naa si ti fun lesi pada pe awada akọ lasan lo n se. O kere tan, awọn dokita onisegun oyinbo bii ọtalelọọdunrun o din meje (253) ni wọn ti fi orukọ silẹ laarin ọgọrun ọjọ lati sisẹ pẹlu ijọba ilẹ United Kingdom. Gẹgẹ bi oju opo itakun agbaye fun ajọ to n se akoso isẹ isegun nilẹ UK, to maa n fawọn dokita niwe asẹ lati sisẹ ti kede rẹ. Laarin ọjọ Kẹwa osu Kẹfa si ogunjọ osu Kẹsan ọdun 2021, dokita ọmọ Naijiria bii ọtalelọọdunrun o din meje lo ti gba iwe asẹ lati sisẹ nilẹ naa. Bakan naa, gẹgẹ bi iwe Punch ti salaye, laarin osu keje ọdun 2020 si osu Kẹsan ọdun 2021, awọn dokita to to ọtalelẹgbẹrin ati meji (862) lo ti gba iwe asẹ lati sisẹ ni UK lai naani arun Coronavirus to gbilẹ nibẹ nigba naa. Lọwọ lọwọ bayii, dokita bii ẹgbẹrun mẹjọ ati ọrinlelẹẹdẹgbẹrin o din mẹta (8,737) ti wọn gba idanilẹkọ nipa isẹ dokita lorilẹede Naijiria, lo ti n sisẹ nilẹ UK. Nigba to n ba iwe iroyin naa sọrọ, igbakeji aarẹ ẹgbẹ awọn dokita to n gba imọ kun imọ ni Naijiria, Julian Ojebo ni o seese ki alekun ba bi awọn dokita se n lọ soke okun laarin ọsẹ melo kan si. Ojebo ni ti ijọba ko ba san owo osu ati ajẹmọnu to yẹ fawọn onisegun oyinbo naa, o seese ki iye awọn ti yoo gba orilẹede Saudi Arabia lọ gan ju ti UK lọ. O fikun pe o se ni laanu pe ijọba kuna lati wa ojutu si ohun tawọn dokita naa n beere fun lati ọjọ Kinni osu Kẹjọ ọdun 2021 ti wọn ti bẹrẹ iyansẹlodi.",0,yoruba báwo làgbàrá yóò ṣe sàn báyìí,0,yoruba "igba mi owó àkokò, Ìyá ri Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba e kaaro ajiire bi a ku isinmi opin ose ẹ kú ojúmọ́ o ẹ sì kú àlàjá ọ̀sẹ̀,0,yoruba "Coronavirus Update: Ebi lé pa ènìyàn 12,000 lójoojúmọ́ lẹ́yìn Covid-19- Oxfam International",0,yoruba "Pasitọ Adeboye paṣẹ lọjọ Aiku, ọjọ kẹwaa oṣu kini ọdun 2021 pe ki gbogbo awọn ọmọ ijọ naa lagbaye gba awẹ ọjọ mẹtalelọgọta naa. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Gẹgẹbi iransẹ Ọlọrun naa ṣe sọ, ọpẹ ni ọjọ mọkanlelogun akọkọ ti wọn ba aawẹ naa yoo da le lori, ọjọ mọkanlelogun keji yoo da lori adura fun idile and bibeere fun aanu. Pasitọ Adeboye ni ipele kẹta awẹ naa yoo wa lati gba adura fun ijọ, idile ati ara wọn. Amọ ọpọ ọmọ Naijiria ko jẹ ki ikede naa balẹ loju opo Twitter, bi wọn ṣe n ka ikede naa, ni wọn n fesi loniruuru le lori. Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó Fun awọn kan, bi eto oselu orilẹde Naijiria ṣe dagun lo mu ki ijọ maa kede awẹ ọlọjọ gbọọrọ bii eyi ti ijọ RCCG kede naa. Bi o tilẹ jẹ pe awon kan dahun pe ṣaaju iṣejọba to wa lode bayii ni ijọ naa ti n seto awẹ ati adura ibẹrẹ ọdun. Ẹwẹ, awọn kan naa n beere pe ṣe kii ṣe ara ọna ati maa gba owo osu akọkọ lọwọ awọn ọmọ ijọ ni wọn se kede aawẹ naa, gẹgẹ bi awọn ijọ kan ti maa nṣe.",0,yoruba eni lo ni àṣà ìdílé lo je ti ibile.,0,yoruba "Bẹẹ ni ọrọ baba ẹni ọgọrun ọdun kan ri, Celestine Egbunuche, ẹni ti ijọba tu silẹ ni ọgba ẹwọn lẹyin ọdun mejidinlogun to ti fi asọ penpe ro oko ọba. Ohun to wa jẹ kayeefi pẹlu baba yii ni pe oun ati ọmọkunrin rẹ, Paul, ni wọn dijọ dajọ ẹwọn fun lori ẹsun pe wọn gbindanwo lati seku pa eeyan kan. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Celestine Egbunuche, ni ẹgbẹ kan ti kii se tijọba, eyi to n gbogun ti iwa ajẹbanu, Global Society for Anti Corruption (GSAC), ja fun idande rẹ rẹ ati ọmọ rẹ lọgba ẹwọn. Amọ baba naa, ẹni to ti n se aisan atọgbẹ, ti ko si riran daada, ni ijọba tu silẹ lọgba ẹwọn to wa nilu Enugu, ti ọmọbinrin rẹ, Chisom Celestine ati awọn asoju ẹgbẹ GSAC, si lọ pade rẹ ni kede ti wọn tu silẹ lọgba ẹwọn ọhun. Nigba to n ba ikọ iroyin BBC sọrọ, Chisom Celestine salaye pe inu oun dun pupọ pe baba oun pada ri itusilẹ lọgba ẹwọn sugbọn o se oun laanu pe oun ko ni agbara lati lee setọju baba naa bo se yẹ. Lọwọ-lọwọ bayii, wọn ti gbe baba Celestine lọ sile iwosan fun itọju, ti ko si si ẹni to lee sọ ohun ti yoo sẹlẹ sii nitori Paul, ọmọ baba naa lo n tọju rẹ lasiko ti awọn mejeeji wa lọgba ẹwọn. Odebiyi: ìgbà gbogbo ni Bàbá mi ń polówó iṣẹ́ mi fáráyé Saa isejọba gomina Rochas Okorocha ni ipinlẹ Imo, to bẹbẹ fun isiju aanu wo baba naa ti kogba wọle, ti ijọba tuntun si ti wa nijọba, a ko si mọ boya o seese ki wọn seto iranwọ fun baba naa.",0,yoruba "ìwájú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba A kò ní gba ojú orunrun di ẹni ẹbọra ń bá jẹun láṣẹ Elédùà. Àsùnjí o! 🌜,0,yoruba "L'oni ni wọn yoo bẹrẹ igbẹjọ Jacob Zuma lori ẹsun iwa ibajẹ Lara àwọn ẹ̀sun mẹrìndínlógún ti wọn yóò fi kan an, ni ìwà ìbàjẹ, jìbìtì àti kíkówó jádé lọ́nà àìtọ, èyí tó ń wáyé nile ẹjọ̀ ńlá kan ni ìlú Durban. O ṣeéṣẹ́ ki ìgbẹ́jọ́ rẹ̀ gba àsìkò gbọ́ọ́rọ́, pàápàá ní báyìí ti àwọn eeyàn fẹ bẹ̀rẹ̀ ìjà lori bóyá ki ìjọ̀ba maá san owó ìgbẹjọ́ Zuma lọ àbí bẹ́ẹ̀ kọ́. Ìgbẹ́jọ́ Zuma jẹ́ ẹ̀rí pé ìjọba alágbádá fìdí múlẹ̀ ní South Africa Àwọn olọ́pá ń gbárádì fún ẹgbẹgbẹ̀rún àwọn álátìlẹyìn ààrẹ orílẹ̀èdè náà tẹlẹ̀ri, ti wọn ti ṣé ìlérí pe àwọn yóò ṣe ìwọde lọ si ilé ẹjọ́ náà. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Orin idanimọ South Africa. Akọ̀ròyìn BBC, Andrew Harding, sọ wipe, kí ààrẹ orilẹ̀ẹde náà tẹ́lẹ̀rí fi ojú ba ilé ẹjọ́ yóò jẹ ńǹkan ńlá fún ìjọba àwá-arawá ní South Africa. O sọ wipe òpọ̀ yóò ri ìgbesè náà gẹgẹ bi òpin ṣiṣẹ̀ s'ofin lai ni ìjìyà.",0,yoruba "Kọmisọna ọlọpa nipinlẹ Ọyọ, naa ṣe afihan igbaradi ajọ ọlọpa nibi akanṣe apero naa. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: INEC tako àṣẹ Buhari lórí pípa ẹni tó bá jí ìbò gbé Kà nípa ìròyìn mánigbàgbé tí BBC News Yorùbá ṣe láàárín ọdún kan Jí àpótí ìbò, ko fi ikú ṣe ìfà jẹ - Iléeṣé ológun laago ìkìlọ̀ Ninu ọrọ rẹ nibi ipejọpọ naa, Kọmisana ajọ eleto idibo nipinlẹ Ọyọ, amofin Mutiu Agboke ṣe alaye wi pe gbogbo eto lo ti to lati rii daju pe eto idibo baa kẹsẹ jari.O tẹsiwaju pe gbogbo kudiẹkudiẹ to ṣokunfa isunsiwaju ibo ni ijọba ti ṣe atunṣe rẹ bayii, bẹrẹ lati ori igba ibo ati awọn iwe to n ṣe akẹsilẹ esi ibo.O fi kun ọrọ rẹ pe omimi kan ko ni mi ibo ọjọ Abamẹta. Bakan naa ni awọn agbofinro pẹlu naa jabọ eto abo ti wọn ti gbe kalẹ fun idibo naa faraalu Kọmisọna tuntun fun ajọ ọlọpa nipinlẹ Ọyọ, Shina Tairu Olukolu naa ṣe afihan igbaradi ajọ ọlọpa nibi akanṣe apero naa.O ni ajọ naa ti n sa gbogbo ipa rẹ lati le jẹ ki ohun gbogbo lọ ni irọwọrọsẹ saaju, lasiko ati lẹhin ibo.Komisọna ọlọpa fi kun ọrọ rẹ pe amojuto to pe ye yoo wa lori ayunlọ ati ayunbọ awọn ohun elo fun eto idibo naa. Nigeria 2019 Elections: Àwọn aráàlú kan ní ìṣúnsíwájú ìbò ṣàkóbá fún ọrọ̀ ajé Ẹgbẹ oṣelu kọọkan lo ni aṣoju nibi apero naa, gbogbo wọn sini wọn ni anfani lati beere ohun gbogbo to ru wọn loju nipa eto idibo ati ojuṣe awọn agbofinro.Satide ọjọ kẹrindinlogun oṣu keji odun yii lo ti yẹ ki eto idibo naa waye ṣugbọn ajọ INEC sun eto naa siwaju nitori awọn kọkọrọ kan to ba eyin aja jẹ nipasẹ imurasilẹ ajọ naa.Nibayii, ọjọ kẹtalelogun oṣu keji ni eto idido naa yoo waye.",0,yoruba @user è é ṣe tí ẹ ò fọ èdè Yorùbá sí mi? Orúkọ yín tọ́ka gbàgàdà wípé ọmọ Yoòbá ni yín. 😡,0,yoruba "Ìjẹ̀. Nitori eyi, ara eni lo ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..",0,yoruba se o ti de level yi ni,0,yoruba Àkójú ọ̀rọ̀ yi kún fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde sí ara ilẹ̀. (Item 24),0,yoruba ọmọ ri pe jẹ́ pàtàkì wey ti o jare.,0,yoruba "Ajọ to n mojuto irinajo Hajj ni Naijiria, National Hajj Commission of Nigeria, NAHCON, ti fidi rẹ mulẹ pe ọmọ orilẹ-ede Naijiria marun un lo ti ku lara awọn to rinrinajo lọ silẹ mimọ Mecca. Lara awọn to ku ọhun ni ọkunrin meji ati obinrin mẹta. Ọkan lara wọn ku si ilu Madina, nigba ti awọn mẹrin toku ku si ilu Makkah. Ninu atẹjade kan ti Alaga igbimọ eto ilera ninu ajọ NACHON, Dokita Ibrahim Kana fi sita, to si tẹ BBC Yoruba lọwọ, ajọ naa sọ pe oriṣiriṣi aisan bii aisan ọkan ati ẹdọforo lo pa awọn eeyan to ku naa. Awọn meji lara awọn eniyan to ku ọhun, ọkunrin kan ati obinrin kan wa lati ipinlẹ Katsina. Nigba ti awọn mẹta tó kù si wa lati ipinlẹ Sokoto, Nassarawa ati Kano. Nigba ti awọn mẹta tó kù si wa lati ipinlẹ Sokoto, Nassarawa ati Kan Kana fi kun ọrọ rẹ pe, arinrinajo to le ni ẹgbẹrun mẹwaa lati Naijiria lo ti gba iwosan ni awọn ileewosan orilẹ-ede Naijiria to wa ni Makkah ati Madinah. Bakan naa lo sọ pe, eeyan mejidinlaadọfa ni wọn gbe lọ si awọn ileewosan orilẹ-ede Saudi fun itọju to l'agbara nitori pe, aisan wọn le pupọ. Ṣugbọn, pupọ lara wọn ti kuro nileewosan bayii. Pupọ lara wọn ti kuro nileewosan bayii Ajọ naa si ti gba awọn arinrinajo ni imọran lati yago fun rínrìn ninu oorun, ki wọn si maa mu omi daadaa, ki wọn o si maa wọ aṣọ to fẹlẹ.",0,yoruba ati ogun ati oogun ati ogun nii n laa eni nii ogun dun nii ede,0,yoruba tí wọ́n bá fi ẹ́wàá ẹ wa pa àrọkò sí èèyàn ó túnmọ̀ sí wípé wọ́n ti ń wá ẹni náà kí ó ma bọ̀ ní ìtòsí if they send ten as an encrypted message to someone it means they have been searching for the person so heshe should come around,0,yoruba "Akọroyin BBC, Aaron Akinyemi ni ọdun mẹta saaju Rosa Park ni Babatunde Olatunji ti bẹrẹ ijijagbara fun ẹtọ awọn ọmọ ilẹ Afrika gẹgẹ bi eniyan bi i alawọfunfun ni ilẹ America. Ọdun 1950 si ọdun 1960 ni awọn alawọdudu dide lati ja fun ẹtọ wọn gẹgẹ bi i ọmọniyan. Ọkan lara wọn ni Babatunde Olatunji, eleyii ti Ajafẹtọ ọmọniyan, Opal Tometi to jẹ adari ikọ ''Black Lives Matter'' sọ wi pe wọn jẹ iwuri fun oun ni aye ode oni lati tako ẹlẹyamẹya ati ifiyajẹni nitori awọ ara eniyan. Babatunde Olatunji fi orin ati ilu ja fun ẹtọ alawọdudu Ọlatunji wa nibẹ pẹlu awọn gbajugbaja ajafẹtọ to jẹ ilumọọka bii James Baldin, Harry Belafonte ni ọdun mẹtadinlọgọta sẹyin nigba ti Martin Luther King Jr sọ ọrọ akinkanju lasiko ifẹhọnuhan to waye nigba naa lati fopin si idẹyẹsini nitori ẹya lorilẹede America. Babatunde Olatunji pẹlu Martin Luther King (L) ati Malcolm X (R) ni 1964 Ọdun 1927 ni wọn bi Olatunji to jẹ ọmọ Yoruba nipinlẹ Eko, ko to di wi pe Olatunji gba ami ẹyẹ lati lo kawe ọfẹ ni oke okun ni ''Morehouse College'' ni Atlanta, lorilẹede America ni ọdun 1950. Olatunji da ilumọọka lẹyin to ṣe awo orin mẹtadinlogun pẹlu awo orin to kọkọ ṣe lọdun 1959, eyi to pe akọle rẹ ni ""Drums of Passion"". Wọn gbe oriyin fun Olatunji pe orin rẹ ṣe igbalarugẹ asa ati orin ilẹ Afrika, eleyii to gbe awo orin naa wa si gbagede lagbaye. Babatunde Olatunji ati Malcolm X ni Nigeria ni 1960 Bawo lo ṣe bẹrẹ? Ọdun 1952 ni Olatunji bẹrẹ ifẹhọnuhan tirẹ ni awọn ọkọ igboro ni Guusu ilẹ Amerika. Lasiko ti Olatunji wa ni ileese Morehouse, ọpọlọpọ nkan to buru jai lo waye nigba naa ti awọn alawọfunfun ṣe si awọn alawodudu nitori ofin ẹlẹyamẹya. Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos Bakan naa ni Olatunji to ma n kọrin ilẹ Afrika ni Amerika ni awọn ile ijọsin ati fasiti ni awọn agbẹgbẹ ilu Atlanta, ni ilẹ Amẹrika. Ni ọdun 1952 ni Olatunji bẹrẹ ifẹhọnuhan tirẹ ni awọn ọkọ igboro ni Guusu agbegbe naa. Olatunji ati awọn ọrẹ rẹ tilẹ ma n wọ aṣọ alaranbara ilẹ Yoruba lati wọ awọn ọkọ igboro naa. Bakan naa ni wọn ma n ṣe ifẹhọnuhan tako ofin ''Jim Crow'' ni Guusu ilẹ Amẹrika. Babatunde Olatunji fẹ iyawo rẹ Ammiebelle Bush ni ọdun 1957 Awọn ẹbi Olatunji sapejuwe rẹ gẹgẹ bi akinkanju eniyan Iyawo Olatunji, Iyafin Ammiebelle Olatunji to jẹ ẹni ọdun mọkandinlaadọrun ṣe apejuwe ọkọ rẹ gẹgẹ bi ẹni to gbe igbeaye rẹ lati ṣe igbelarugẹ fun ifimọsọkan awọn ọmọ ilẹ Afrika. Ni ọdun 1964, Olatunji ṣiṣẹ pọ pẹlu aarẹ akọkọ lorilẹede Tanzania, Julius Nyerere ati Malcolm X lati fopin si ofin ẹlẹyamẹya lorilẹede Amerika. Awọn ọmọ meji ninu awọn mẹrin ti Olatunji bi, Folasade ati Modupe Olatunji ṣe apejuwe baba rẹ gẹgẹ bi akinkanju eniyan to si kọ awọn ọmọ rẹ ni ṣiṣe iṣẹ takuntakun lọna ati jẹ ki wọn jẹ akinkanju eniyan nibi gbogbo ti wọn ba de. Ọdun 2003 ni Olatunji sun ti ko ji mọ ni ẹni ọdun mẹrindinlọgọrin. Iṣẹ takuntakun to ṣe ni ẹka orin kikọ ti jẹ ki Babatunde Olatunji jẹ awokọṣe fun Afrika ati awọn ọmọ ilẹ Afrika ti wọn bi tabi ti wọn n gbe ni Amerika.",0,yoruba "Eyi ṣeeṣe ko ribẹ nitori bi eto aabo ṣe ri l'orilẹede naa bayi, latari bi aarẹ orilẹede naa nigba kan, Mohammed Morsi ṣe ku nile ẹjọ lasiko to n jẹjọ, ti idije naa si n waye lẹyin ọjọ diẹ ti eyi waye. Gẹgẹ bi iroyin to n lọ labẹle, awọn oṣiṣẹ alaabo to to ẹgbẹrun mẹẹdogun ni yoo ṣiṣẹ ni awọn ilu mẹrẹẹrin ti idije naa yoo ti waye; Cairo, Alexandria, Suez ati Ismailia. Bakan naa ni ibudo ayẹwo pọ yika papa iṣere ti eto naa ti waye lalẹ ọjọ Ẹti. A gbọ pe eto ayẹwo kan tun ti wa nilẹ, lati maa tọ pinpin awọn oluworan lati igba ti wọn ba ti wọ papa iṣere, titi wọn yoo fi jade. Fẹmi Kuti wa lara awọn akọrin ti yoo side AFCON 2019 Idije AFCON tọdun 2019 ni igba kejilelọgbọn ti idije naa yoo waye. Femi Kuti, tii se ọmọ Kaarọ Oojire, to tun jẹ ilumọọka akọrin lati orilẹede Naijiria, yoo dara pọ mọ awọn gbajugbaja akọrin miran, ti yoo ma a bawọn si idije bọọlu fun ife ẹyẹ ilẹ Afirika, AFCON 2019 pẹlu orin. Orin kikọ̀ naa wa lara awọn ayẹyẹ ibẹrẹ idije Afcon naa, ti ọpọlọpọ ayẹyẹ ti yoo gbe asa ga ni ilẹ Afirika yoo rinlẹ nibi ayẹyẹ iside idije naa. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Tani Femi Kuti ti yoo kọ orin iside Afcon 2019? Orúkọ àwọn orílẹ̀èdè tí yóò kópa ní AFCON 2019 rèé Idije ti AFCON tọdun yii lo tobi ju lati ọdun 1957 to ti bẹrẹ. Ẹgbẹ agbabọọlu mẹrindinlogun ni yoo kopa fun igba akọkọ. Bakan naa fun igba akọkọ, idije naa to maa n waye laarin oṣu Kinni ọdun si oṣu Keji yoo waye, laarin oṣu Kẹfa ọdun si oṣu Keje. Eyi waye nitori bi o ṣe maa n fa ariyanjiyan laarin igbimọ ajọ to n mojuto idije naa, CAF ati awọn ẹgbẹ agbabọọlu nilẹ Yuroopu, to ni lati yọnda awọn agbabọọlu wọn fun idije naa lai jẹ pe saa bọọlu gbigba nilẹ Yuroopu ti pari. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ṣugbọn ninu oṣu Keje ọdun 2017, ajọ CAF pinnu lati sun idije ti ọdun yii si oṣu Kẹfa ati ikeje. Bakan naa ni wọn sọ ẹgbẹ agbabọọlu ti yoo kopa si mẹrinlelogun. Ẹgbẹ agbabọọlu mẹrindinlogun lo maa n kopa tẹlẹ. Orilẹede Egypt lo gbalejo idije naa bayii fun igba karun un. Ẹgbẹ agbabọọlu Pharaoh ti Egypt si lo ti gba ife ẹyẹ idije naa ju lọ. O ti gba a fun igba meje. Orilẹede Cameroon lo yẹ ko gba alejo idije AFCON 2019, ṣugbọn wọn gba a kuro lọwọ wọn l'oṣu Kọkanla, ọdun 2018, nitori pe wọn ko jara mọ imurasilẹ ati eto aabo to mẹhẹ l'orilẹede naa. Oṣu Kinni ọdun 2019 ni ajọ CAF kede Egypt pe oun ni yoo gbalejo idije naa. Awọn orilẹede ti yoo kopa ninu idije naa ni Egypt, Madagascar, Tunisia, Senegal, Morocco, Nigeria, Uganda, Mali, Guinea, Algeria, Mauritania, Ivory Coast, Kenya, Ghana, Angola, Burundi, Cameroon, Guinea-Bissau, Namibia, Zimbabwe, DR Congo, Benin, Tanzania, ati South Africa.",0,yoruba wọn yóò wá tàgíìrì a ó rẹ́ ẹ sómi pẹ̀lú iyọ̀ diẹ̀ láti fi yọ irun ara awọ,0,yoruba "RT @user: B'ọ́mọdé bá ń dalẹ̀, kí ó má ṣe da Ògún; ọ̀rọ̀ Ògún léèwọ̀. #EsinOro🐎 #Yoruba",0,yoruba "Iyale wa lo ni Mon, Tues. Iyale keji lo ni Wed, thurs. Emi moni Fri, Sat & Sun gege bi last wife.#Movie #Yoruba #Comedy #Landlord #Throwback",0,yoruba Femi Branch: Gbogbo dúkìá mi àti ti ìyá mi ni mo tà láti tọ́jú ẹsẹ̀ mi fún ọdún méjì,0,yoruba nípa ìròyìn tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò.,0,yoruba "Nigeria Army: Kò sí òtító nínú ọrọ náà pé Boko Haram gba owó lọwọ wa Awọn alakatakiti ẹsin Islam, Boko Haram ni iroyin ni wọn dena gba ẹgbẹlẹgbẹ miliọnu naira lọwọ awọn ọmọ ogun ilẹ yii ni opin ọsẹ to kọja. Iroyin naa sọ pe, koto nla kan ni awọn ẹgbẹ́gun Boko Haram naa gbẹ silẹ de awọn ọmọ ogun naa ni popona Azare si Kamuya ni ipinlẹ Yobe ni ariwa Naijiria. Lori ayelujara ni iroyin naa ti ni eeyan kan ninu awọn ọmọ ologun naa farapa yanna-yanna ti ọpọ ohun ija si bajẹ kọja aala. Ninu awọn ohun ija ti awọn ọmọ ologun n ko lọ ni iroyin salaye pe awọn Boko Haram naa tun gba, ti wọn si ko lọ. Iroyin naa ni wọn gba owo to le ni miliọnu mẹẹdogun lọwọ wọn. Nigba ti BBC kan si ileeṣẹ ọmọ ogun Naijiria lati fidi iroyin yii mulẹ ni wọn sọ pe irọ funfun balau ni. Ẹka iroyin ati ifitonileti ni ileeṣẹ ọmọ ogun ilẹ̀ ni ko si ootọ kankan ninu ọrọ naa àti pé ko si bi awọn ọmọ ogun boko Haram ṣe le gbena woju awon ọmọ ogun. Ni afikun, wọn ni awọn ọmọ ogun ilẹ wa ti gbaradi lati dena gbogbo ọna ti Boko Haram n gba lati ṣe ijamba fun ara ilu. Oga ologun to ba BBC sọrọ ni pe boko haram ko da ọmọ ogun lọna de ibi pe wọn gba owo ajẹmọnu lọwọ wọn rara.",0,yoruba "Omoluabi wa ni ọba lálai lo je ti ibile. Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.. Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "Ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu BBC, o ni ẹya Yoruba ti jiya pupọ fun orilẹ-ede Naijiria, paapaa lori ọrọ ominira kuro lọwọ amunisin, ati lẹyin to gba ominira tan. Lẹyin naa lo tun tọka si ipa ti Yoruba ko ninu ogun abẹle Biafra to waye. O ni Yoruba ni igbagbọ pe orilẹ-ede Naijiria ṣi ma a dara laipẹ O ni lootọ ni nkan ko lọ bo ṣe yẹ ko lọ, paapaa lati bi ọdun marun ti ijọba to wa nibẹ bayii ti gun ori aleefa. ""Lati igba ti mo ti de aye, ko si asiko ti ija ẹlẹyamẹya ati ẹsin pọ ni Naijiria buru to bo ṣe ri bayi. Bakan naa ni ọrọ abo. ""O fojuhan pe ijọba naa fi si apa kan."" O tẹsiwaju ninu ọrọ rẹ pe awọn ko ti i ṣetan lati lọ si ibi kankan, pe ko rọrun bẹẹ, ""nitori pe a ti wa papọ, o ti le ni ọgọrun ọdun"". O ni ṣaaju ki awọn oyinbo to de ni ibaṣepọ ti wa laarin awọn ẹya to parapọ di Naijiria. ""Awọn ọdọ to n binu ni ẹtọ lati binu, nitori pe wọn n ja fun ọjọ ọla wọn ni. Àwọn ọ̀rọ̀ Yorùbá kan wà tí ẹ kò lè lò pọ̀ mọ́ ara wọn, àwn ọ̀rọ̀ tẹ́ẹ lè fi rọ́pò rèé Ṣugbọn awa agbagba n sọ pe ko yẹ ki wọn tẹ ẹ jẹjẹ, nitori pe ọmọ ọdọ naa ma an fi ọgbọn ṣe."" ""A ni ki wọn o rọra, nitori pe a ko ni i fẹ ki ogun abẹle kankan ti ọdọ Yoruba bẹrẹ. O ni ayafi to ba jẹ pe aarẹ deedee sọrọ lọjọ kan pe ki kaluku ma a ba tiẹ lọ. ""Awa naa ṣetan. ṣugbọn kii ṣe ki a doju ija kọ ijọba Naijiria nitori pe kaakiri Naijiria ni awọn ọmọ Yoruba wa. Ka fi suuru yanju rẹ ni awa agbaagba n sọ.""",0,yoruba "Laarin osu kan, o si le ni miliọnu marun eeyan to ti lugbadi kokoro arun naa, idi si ree ti ileesẹ BBC se tanna wadi ohun to fa itankalẹ arun naa lẹnu lọọlọ yii ni India. Iwadii BBC ti wa fidi rẹ mulẹ pe bi awọn eeyan se seraro lori awọn ilana to n dena itankalẹ arun Covid-19 lo fa sababi. Bakan naa la tun fidi rẹ mulẹ pe oniruuru ẹya arun Coronavirus lo ti su yọ ni India, to si rọrun fun lati tete ran ẹlomiran. Iwadii tun fidi rẹ mulẹ pe ẹya arun naa to wa lati ilẹ United Kingdom UK lo pọ ju awọn ẹya arun Covid-19 miran lọ. Koda, aaye ko fẹ si mọ lati sin awọn oku to n jade laye lati ipasẹ arun naa bayii. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:",0,yoruba Ajìjàǹgbara Guinea Macky Darsalam sọ ti ìgbésẹ̀ láti tọwọ́ bọ èròńgbà àwọn ará ìlú lójú :,0,yoruba ẹkọ́ ṣẹlẹ ni Ibadan ti gbogbo eniyan sọ o ṣe pataki. (2010),0,yoruba Láìpẹ́ yìí ni Khafi Kareem di oní mọ́tọ̀ lẹ́yìn tó jẹ̀bùn ọkọ̀ lórí ètò BB Naija Khafi ni yoo ma a koju iwadii ti o ba pada si ẹnu isẹ nitori iroyin gbe e pe ko gba aṣẹ ki o to bẹrẹ si ni kopa ninu Big Brother Naija. Laipẹ yii ni Khafi di onímọ́tọ̀ lẹ́yìn tó jẹ̀bùn ọkọ̀ lórí ètò BB Naija. Ọpọlọpọ eniyan lo fẹran rẹ nitori wọn ri i gẹgẹ bi ẹni ti kii fi dudu pe funfun. Khafi ati Gedoni lo fẹran ara wọn ju ninu Big Brother Naija ko to di wi pe wọn le Gedoni naa laipẹ yii. African Migrants: Awọn arinrinajo sọ iriri wọn lọ si ilẹ Amerika,0,yoruba "Látàrí ìbálòpọ̀ tí kò ní ààbò , ọ̀pọ̀ l'ó ti kó àrùn kògbéwékògbègbó HIV àti AIDS .",0,yoruba yii nípa ayé ọ̀ṣun lo je ti ibile.,0,yoruba "Sẹnetọ Bukọla Saraki ni ọga agba ọlọpa lorilẹede Naijiria, Ibrahim Idris n gbero lati hun panpẹ akoba kan fun oun Nigba to n sọrọ nibi ijoko ile lọjọọru, Sẹnetọ Saraki ni Ọga ọlọpa n gbero lati lo awọn afunrasi ẹlẹgbẹ okunkun kan ti ọwọ ọlọpa ba ni ilu ilọrin ti wọn si ti bẹrẹ eto ati ṣe ẹjọ wọn lati parọ mọ ohun ati awọn eekan oloṣelu kan ni ipinlẹ Kwara pe awọn ni baba isalẹ wọn. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ""Iwadi ti pari, eto si ti nto lati gbe wọn lọ siwaju ile ẹjọ ni ibamu pẹlu amọran olupẹjọ agba nipinlẹ Kwara. Ṣa dede ni wọn ni ọga agba ọlọpa ni ki wọn ko wọn wa si ilu Abuja. Iroyin ti mo si n gb ni pe wọn fẹ wa ọna ti wọn yoo fi yii akọsilẹ ti wọn kọ nilu Ilọrin pada lati fi ẹsun kan ijọba ipinlẹ Kwara, paapaajulọ emi."" Ọ̀gá ọlọ́pàá, Ibrahim Idris àti àwọn aṣòfin ti ń gbéná wojú ara wọn fún ìgbà pípẹ́ Ile aṣofin agba kọminu lori igbesẹ yii ti wọn si ṣe apejuwe rẹ gẹgẹ bii 'iwa idunkokomọni ati ibanilorukọ jẹ.' Ninu ọrọ to sọ, Sẹnetọ Mishau ni oun ti pe akiyesi ile si 'iwa ijẹgaba ati idunmọhuru mọni lati ileeṣẹ ọlọpaa ni nkan bii ọdun kan sẹyin pe gbogbo wa ni ọga ọlọpaa yii yoo ṣi fi oju rẹ ri rẹdẹrẹdẹ.' Amọṣa, gbogbo awọn aṣofin agba naa lo fẹnuko pe ki ile aṣofin agba o gbe igbimọ kalẹ ti yoo lọ ṣepade pẹlu Aarẹ Buhari lori ọrọ naa.",0,yoruba "Mo ti pè pè pè 111 títí síbẹ̀ kò sí àtúnṣe, gbogbo ohun tí wọ́n ní ń ṣe ni mo ti ṣe. @user @user @user",0,yoruba eba wa gbe agbejero agba nijeria femi falana laruge femi ti pe ọgọta odun femi a pe laiye fun ile oodua barisita femi je baba fun akorin igbalode folarin ti inogije re je abi femi si ilu ilawe ekiti ni ogun ojo osu karun odun,0,yoruba òní. ti Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò.,0,yoruba "''Yíyan Shettima ní igbákejì mi kò níí ṣe pẹ̀lú ọ̀rọ̀ ẹ̀sìn, ìdí abájọ rèé...''",0,yoruba òkèòkun kì í dùn kátukọ̀ máà lórí padà bọ̀ ṣoríire lọ́hùn ún kío kóríire ọ̀hún ran naija àwé ò dákun mọ́ gbàgbé ilé o,0,yoruba "Ọ̀pẹ̀kẹ́tẹ̀ tí a bá nà ní pàpá, ẹni tó bá bà kó máà fi ṣèbínú, kó tún 'bẹ̀ ṣe. #IjoOle @user @user @user @user",0,yoruba ojú òní.. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba ọmọ oòduà ọmọ yorùbá ọmọ aládé ni mí ìwọ ń kọ́ àní o tẹ bí o bá jọ́kan,0,yoruba ọmọ ri pe jẹ́ pàtàkì wey ti o tẹ.,0,yoruba Ire! Ire!! Ire!!! Ire gbogbo di oríi mi,0,yoruba 2/2 » Mẹ́ta là á pa á. Mẹ́ta là á mọ̀ ọ́n. Ọmọ láílo. Kí ni o? @user,0,yoruba Imọ-ẹrọ @user wa ni iṣawari fun gbigbe owo ailewu. Ṣayẹwo awọn iroyin lati wa idi ti a fi gbagbọ ninu #XRP. Awọn ilana jijo #global #dance #challenge #fun #Africa #Yoruba https://t.co/HiO4OQEfWk,0,yoruba "o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì lẹ̀.",0,yoruba iseju mewa ìsẹ́jú mélòó ló gbà kí ẹ̀bà tó tẹ̀ gaàrí ìjẹ̀bú ni o,0,yoruba "Mo feran lati mo Tweeti ni Ede Yóòba pu po. O sunmo wìípe hin tun Ede naa ko, Agaga awon orisirisi ami ti owa Ni ori Alufabeti imiran. #Yoruba",0,yoruba nípa ẹkọ́: ti o ní wúlò fún gbogbo.,0,yoruba "Ẹnu wọn l'ẹ̀fà, ẹnu wọn l'èje, àwa ò b'ẹ́lẹ́nu méjì ṣ'eré mọ́"""""""""""""""" - #Orin #MusiliuIsola #Yoruba #Enulebo",0,yoruba "Iniesta gbá bọ́ọ̀lù fún ikọ̀ Barcelona fún ọdún méjìlélógún Iniesta ṣoju ikọ agbabọọlu naa fun igba ikẹyin lọjọ Aiku, nigbati Barcelona koju Real Sociedad lẹyin igbati ti o ti wa nibẹ fun ọdun mejilelogun. Barcelona fagban han ẹgbẹ agbabọọlu Real Sociedad pẹlu ami ayo kan ṣ'odo ninu ifẹsẹwọnsẹ La Liga naa. Agbabọọlu aarin gbungbun Phillipe Coutinho lo gba ayo naa wọle ni iṣẹju mẹtadinlọgọta. Iniesta wá lára àwọn agbábọ́ọ̀lù tí àwọn olólùfẹ́ Barcelona fẹ́ràn jù Lẹyin naa ni wọn gbe ife ẹyẹ La Liga fun ẹgbẹ agbabọọlu Barcelona fun saa yii. Iniesta ti sọ tẹlẹ pe oun yoo fi adagba oun rọ pẹlu ikọ Barcelona nipari saa yii.",0,yoruba Baàlè fi. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó ga jù.,0,yoruba "Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin Ekiti yọ Abenugan rẹ̀ INEC: Èsì ìdìbò Ekiti lẹ́kùnrẹ́rẹ́ Ẹlẹka: Ìdá àádọ́rin nínú ọgọ́rùn ni mo ní nínú ìbò Ekiti #EkitiDecides: 'Ìjà ẹgbẹ́ òkùnkùn ló ń ṣẹlẹ̀ kìí ṣe ti òṣèlú' Kayode Fayemi : Awọn osisẹ ni Ekiti ko i tii gba owo osu ni ọdun yii Bákan náà ní wọn ti yàn abẹnugan mìíràn, Adeniran Alagbada nígbà ti wọn tún igbákejì abẹnugan tí wọn ti gbọ̀n yọ tele Segun Adewunmi pada sípò gẹ́gẹ́ bíi igbákejì abẹnugan ilé. Olorí ilé tuntun ti wọn yan bayìí ní olori ọmọ ilé tó kéré jùlọ tẹ́lẹ̀, Gboyega Aribisogan nígbà ti Sunday Akinniyi tí gbogbo ènìyàn mọ si 'Gbosa' bó tilẹ̀ jẹ́ pe ó ṣẹ̀ṣẹ̀ darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ APC ló wá jẹ́ olórí ọmọ ilé tó kéré jùlọ báyìí. Ní bayìí wọn ti bura wọlé fún gbogbo wọn. A ó máa mú ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ìròyìn náà wá fún un yín.",0,yoruba lo ni ìgbà àkerekere lo je ti ibile.,0,yoruba "Ǹjẹ́ o mọ pe eniyan máa n pe ojo? Kìí ṣe òni ní a ti máa ń gbọ nípa àwọn alagbara ayé l'ókùnrin àti l'obinrin, àwọn aláwo ti wọn máa ń ṣe oníruuru òògùn, ti omíran a sì máa sọ pé oun le ti òjò tàbi yí oju ọja padà. Agbára ju agbára lọ: Wo bàbá Godwin to pe òjò Awọn ènìyàn míràn máa ń mú kí òjò rọ lásìkò tí wọn bá ń fẹ, ti àwọn ènìyàn sì máa ń kà wọn kún alágbara ẹ̀dá tó lè mú kí òjò rọ tàbí kí òjò dá. Wọ́n rò pé mo ya wèrè ni Saudi lẹ́yìn ikú ọkọ mi Bó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn míràn ní ìgbàgbọ pé ènìyàn kò lè mú ki òjò rọ tàbí dí òjò lọ́wọ́ tí àwọn àjọ tó ń ri sí bí ojú ọjọ́ ṣe rí (NIMET) pẹ̀lú sọ pé kò sí eni tó lè dán irú ẹ wò. Sùgbọn nínú ìwádìí BBC a ri i pé àwọn tó ń ti òjò ti wọn sì ń ṣí òjò pọ̀ jántìrẹrẹ ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Sùgbọn nínú ìwádìí BBC a ri pé àwọn tó ń ti òjò ti wọn sì ń sí òjò pọ̀ jántìrẹrẹ ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Iṣẹ́ wọn ni láti tí òjò fún àwọn tó bá ni ìnáwo láti ṣe, yálà òkú àgbà, ìgbéyàwó tàbí láti lọ ta ọjà wọn, nínú ìwádìí BBC wọn tún ni àwọn míràn máa bẹ̀wọ́n lọ́wẹ̀ láti jẹ́ kí òjò rọ̀ níbí ayẹyẹ ọ̀tá wọn. Ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ní èrò ṣe fún àwọn míran nítorí wọn gbàgbọ́ pé ọgbọ́n àrékérekè lásán ní àti pé kò sí ẹni to lè tú iṣẹ́ olúwa wò nípa rírọ òjò tàbí dídáa dúró. Mo lé rán òjò dí ilé ọ̀tá àwọn alábara mi Pẹ̀lú ìrànwọ àwọn ènìyàn àkòròyìn BBC sàbẹ̀wò sí Godwin Onasedu ní ìlú Ifitedunu, ni ìjọba ìbílẹ̀ Dunukofia ìpínlẹ̀ Anambra, Okùnrin yìí jẹ́ a mú òjò rọ. Lẹ́yìn ìpèsè gbogbo ǹkan wọnyìí Godwin rọ ojò lẹyìn wákatí méjì, ti ojò náà rọ fun ìṣẹ́jú márùn kó to dá., òjò náà kò lágbára púpọ̀. Nínu àlàyé rẹ̀, o ni iṣẹ́ ti ìran oun ni oun ń ṣe láti ìgbà ìwáṣẹ̀ ṣùgbọn láti mú òjò rọ̀ àwọn nílò. Lẹ́yìn ìpèsè gbogbo ǹkan wọnyìí Godwin rọ ojò lẹyìn wákatí méjì, ti ojò náà rọ fun ìṣẹ́jú márùn kó to dá., òjò náà kò lágbára púpọ̀.",0,yoruba "Ibalopọ ladun pupọ, o si jẹ ohun ti ọkunrin ati obinrin maa n gbadun lọpọ igba. Ṣugbọn lọpọ igba naa ni awọn to n ni ibalopọ ọhun le ko sinu ewu iku ojiji, tabi ki awọn mejeji lẹpọ, tabi se aisan. Ọkunrin le ku sori obinrin, bẹẹ si ni o ṣeeṣe ki obinrin ku sabẹ okunrin lasiko ti wọn n gbadun ara wọn pẹlu ibalopọ, eyi to maa n ya ọpọ eeyan lẹnu. Oniruru iroyin lo ti jade pe awọn eeyan kan ku lori ibalopọ, eyii to jẹ kayeefi ati ara meeriri fun ọpọ eeyan. Bi awọn kan ṣe n sọ pe iṣẹ aye ni, ni awọn mii maa n di ẹbi irufẹ iṣẹlẹ bẹẹ ru eyikeyi ninu takọ-tabo naa, paapaa awọn to n ni ibalopọ lẹyin ọkọ tabi iyawo wọn. Ọpọ eeyan miran si lo maa n fi oju asasi wo iru iru isẹlẹ yii lasiko to ba waye, ti kii si jẹ ootọ nigba miran. Amọ awọn onimọ ijinlẹ isegun oyinbo ti ṣalaye ohun to le mu ki eeyan gbẹmi mi lasiko ibalopọ, yala ọkunrin tabi obinrin. Awọn ohun mẹ́rin wọnyi le mu ki eeyan ku lasiko ibalopọ si ree: 1. Aṣilo oogun: Ọpọ igba ni awọn ọkunrin maa n lo agbo ibilẹ ki wọn le ni okun daadaa lasiko ibalopọ. Awọn mii ẹwẹ a maa da agbo ibilẹ mọ ọti oyinbo pẹlu igbagbọ pe yoo le ṣiṣẹ daada ninu agọ ara wọn alti fi pa itu meje sara obinrin. Nigba mii ẹwẹ, awọn ọkunrin kan maa n mu siga, igbo, to fi mọ oniruru oogun ti wọn n ta, lati le ṣe afikun okun wọn lori obinrin. Ṣugbọn ohun ti ko ye wọn ni pe, pupọ ninu awọn oogun naa lo ni eroja ti wọn n pe ni ""Nitrate"" ninu, eyi to le fa ẹjẹ riru, to si le yọri si iku ojiji. Gbogbo ẹ gbogbo ẹ, igbesẹ naa ko sẹyin iyi ti wọn fẹ gba lọdọ obinrin ti wọn n ba ni ibalopọ ọhun. 2. Aisan ọkan: Gbogbo aisan to jẹ mọ ọkan lo lewu ninu, kii si ṣe ohun to yẹ ki eeyan fi ọwọ yẹpẹrẹ mu. Ẹni to ba ni aisan ọkan tẹlẹ le dakẹ lasiko ibalopọ nitori ọkan naa yoo maa ṣiṣẹ ju be ṣe yẹ lasiko ibalopọ ọhun. Lara awọn ohun to maa n fa aisan ọkan, paapaa fun awọn obinrin ti ọjọ ori wọn ti le ni marundinlọgọta atawọn okunrin ti ọjọ ori wọn ti le ni marundinlaadọta ni ẹjẹ riru, siga mimu, aisan itọ ṣuga, ara sisan ati bẹẹ bẹẹ lọ. Ohun kan gboogi to tun maa n fa aisan ọkan ni wahala aṣeju ti wọn n pe ni ""Stress"" lede Gẹẹsi. 3. Magun: Gẹgẹ bii igbagbọ Yoruba, magun jẹ oogun kan ti wọn maa n fi sara obinrin ti oju rẹ ko ba gbe ibikan, lati kọ irufẹ obinrin bẹẹ lọgbọn. Wọn tun maa n lo magun lati fiya jẹ okunrin to ba n ni ibalopọ pẹlu iyawo oniyawo. Oriṣiri magun lo wa, lara rẹ ni magun mamuomi, magun matakiti, magun ma fotiti, magun majẹla ati bẹẹ bẹẹ lọ. Fun irufẹ awọn magun bayii, ti ọkunrin to lu magun ọhun ba ti jẹ eewọ rẹ, yoo jade laye dandan ni. Igbagbọ Yoruba ni pe ọrun lala ni okunrin to ba lu magun, yoo si lọ ṣalaye ara rẹ fun Eledumare. 4. Ifipabanilopọ: Oniruru iroyin lo ti wa lode nipa awọn obinrin to n dakẹ sabẹ okunrin lasiko ti wọn ba fi tipa ba wọn lopọ, eyi ti ko ti ọkan obinrin naa wa. Iru iku bayii wọpọ laarin awọn obinrin ti wọn ba fi agidi ba lopọ. Irufẹ iku bẹẹ tun wọpọ laarin awọn ti ọjọ ori wọn ko tii nnkan, ṣugbọn ti wọn fi ipa ba lopọ bakan naa, paapaa awọn ọmọdebinrin. Nigba miran ẹwẹ, ti ọkan irufẹ obinrin naa ko ba si nibi ibalopọ ọhun, o ṣeeṣe ko dakẹ sabẹ okunrin to n fi ipa balopọ.",0,yoruba "àti àsà tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Bunmi Akinnanu: Ọlọ́run kìí fún èèyàn méjì ní orin ẹ̀mí kan ṣoṣo, ẹ jẹ́ ká ṣe sùúrù",0,yoruba "èrò àti àsà tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba owo ṣẹlẹ ni Eko ti gbogbo eniyan sọ o dara. (1993),0,yoruba "Ọdun 1982 ni aarẹ Paul Biya gba ọpa asẹ lati maa dari orilẹ-ede Cameroon, o si jẹ ọkan lara awọn aarẹ to dagba julọ lori oye ni ilẹ Afrika. Nigba to si jẹ pe saa keje lo fẹ se bayii lori aleefa, o yẹ kẹ mọ awọn ohun meje nipa aarẹ Biya, ti orilẹ-ede Cameroon naa. 1. O jẹ́ ọ̀kan lara awọn olórí ni Afrika to n gba owó ju lọ Abọ iwadi kan sọ pe ìlọpo igba le mọkandinlọgbọn owo oṣu ti oṣiṣẹ n gba ni Cameroon, ni owo oṣu Aarẹ Biya Aarẹ Biya wa lara awọn aarẹ to n gbowo ju lọ ni Afrika. O ti ẹ ṣeeṣe ko jẹ oun lowo oṣu rẹ pọ ju. Iwe iroyin African Review sọ pe, Biya n gba ọtalelọọdunrun o din ẹyọkan miliọnu CFA francs, owo orilẹede Cameroon, ti afiwe rẹ jẹ ẹgbẹrun lọna ẹgbẹta o le mẹwa Dọla ($610,000) lọdọọdun. 2. Baba onile to n sun ita ni Biya Ile itura to gbayi ni Switzerland ni Biya n gbe ju Awọn kan maa n ṣapejuwe Aarẹ Biya gẹgẹ bi baba onile, ṣugbọn ti kan-in-kan-in ile rẹ kii ta nidi, nitori pe ọpọlọpọ akoko lo maa n wa ni awọn ile itura to gbayi, to si wọ́n pupọ ni orilẹede Switzerland. O si maa n ko to ogoji eniyan dani lọ fun irinajo kọọkan to ba n lọ, wọn si le na to ẹgbẹrun mejidinlaadọta le ni ẹẹdẹgbẹta Dọla l'ọjọ kan. Ajọ aladani kan tilẹ sọ pe o ti na to aadọrun biliọnu FCFA laarin ọdun 1982 si 2017. 3. Aarẹ Biya jẹ ọkan lara awọn aarẹ to dagba ju ni Afrika Biya yoo pe ẹni ọdun mejidinlaarun nigba ti yoo ba fi pari saa keje rẹ Aarẹ Biya bọ si ori aga iṣakoso l'ọjọ kẹfa, oṣu Kọkanla, ọdun 1982, lasiko ti Aarẹ Amadou Ahidjo gbe agbara iṣakoso le e lọwọ. Yoo si tun bura wọle fun saa ọlọdun meje mi i, eyi ti yoo mu ko pe ọdun marundinlogoji to ti wa nipo. Biya ti pe ẹni ọdun marundinlaadọrun. Ilaji awọn ọmọ orilẹede Cameroon tilẹ sọ pe Biya lo ti wa ni ipo lati igba ti wọn ti bi wọn. 4. Igba meji lo ti ṣegbeyawo Chantal Biya Aarẹ Biya ti fi igba kan jẹ́ ọmọ ile ẹkọṣẹ alufaa Katoliiki, ko to di pe o fẹ iyawo rẹ akọkọ, ti ko bimọ fun un. Aṣa wọn si ni pe o le bimọ lati ara arabinrin iyawo rẹ. Lẹyin ti Jean Irene Biya ku, ni aarẹ Biya fẹ Chantal, wọn si bi ọmọ meji. Chantel ti kọkọ bi ibeji fun ọkunrin kan. 5. Biya ko kuna ri ninu eto idibo aarẹ Ọjọ keje, oṣu Kẹwaa ni wọn ṣe eto idibo to gbe Biya wọle fun igba keje Aarẹ Biya kọkọ fi ẹyin Amadou Ahidjo janlẹ l'ọdun 1982. Lẹyin ọdun mẹwaa, o tun bori ni 1992, 1997, 2004 ati 2011. Bakan naa ni 2018, o bori pẹlu ibo ìdá mọkanlelaadọrin, botilẹ jẹ pe eniyan miliọnu meji ataabọ pere lo dibo ninu miliọnu mejilelogun to yẹ ko dibo. 6. Iwa jẹgudu-jẹra gbayi l'orilẹede naa Cameroon ti gba ami ẹ̀yẹ fun iwa ibajẹ lẹẹmeji, kekere kọ si ni kiko owo ìlú jẹ lati igba ti Aarẹ Biya ti wa nipo fun ọdun marundinlogoji bayii. Cameroon lo wa ni ipo mẹrindinlaadọjọ ninu orilẹede mẹrindinlaadọsan to n hu iwa ijẹkujẹ. 7. Aarẹ Biya kii ṣe ipade pẹlu awọn minisita rẹ Orilẹede Isreal ni awọn oṣiṣẹ alaabo Biya ti n kẹ́ẹ̀kọ̀ọ́ Aarẹ Biya kii ṣe ipade pẹlu awọn ọmọ igbimọ iṣakoso ati minisita rẹ ni gbogbo igba, ayafi asiko to ba fẹ ẹ yan minisita sipo nikan. Eyi si mu ki kaluku wọn maa ṣe boṣe wu wọn lẹnu iṣẹ. Ọdun 2015 ni Biya ti se ipade igbimọ alaṣẹ kẹhin, ko to o tun ṣe ni 2018. O tilẹ maa n gba iṣẹ́ lọwọ minisita ti ko ti ẹ ri soju ri.",0,yoruba "Adebayo Shittu: Ajimobi ló ṣẹ̀ mí, n kò ṣẹ Ajimobi, ipò kan náà la jọ ń wá àmọ́ kò fẹ́ mi ní ìjọba",0,yoruba ìṣẹ̀: ti o nuni ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ẹkọ́: ti o ní wúlò.,0,yoruba oníṣẹ́ ìbílẹ̀ wo ni à ń pè ní ọ̀pàpàpagidàsọgidèèyàn a onígẹdú b agbẹ́gilére d àgbẹ̀,0,yoruba Ọpẹ́ ni f'Ólúwa Ọba Apọnmọnmáwẹ̀hìn. Pọ̀n wá Olúwa f'ọ̀já múwa káa má baà ré lulẹ̀ lẹ́hìn rẹ o. #ekaaro,0,yoruba "ni ọ̀gbọ́n. Ọmọ lo ni Nitori eyi, ara eni lo ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba "Ipinu Saba Gul ree eleyi ti o sọ di orin apilẹkọ to fi n gbe igbesi aye rẹ. Ọsọrọ olomọge yi ko ni apa mejeeji ṣugbọn ipenija yi ko jẹ idiwo fun lati ma gbe igbe aye rẹ. Okun Ina manamana ni o gbamu nigba ti o wa ni ọmọ ọdun maarun eleyi ti mo ki awọn dokita ge apa rẹ mejeeji lati doola ẹmi rẹ. Lati igba naa ni o ti bẹrẹ si ni lo ẹsẹ rẹ fii ṣe ohun to yẹ ki o fi apa ṣe. ''Awọn kan a ma sọ wi pe iṣowolofo ni kin wn ran mi lọ ile iwe ṣugbọn mi o ka ọrọ wọn kun'' Saba Gul lero lati di agbẹjọro lọjọ iwaju ki o ba le ma ja fun ẹtọ awọn obinrin ati awọn eeyan miran to ba ni ipenija kan tabi omiran. ''Mo fẹ rin kaakiri,kin mọ ilu ati awọn aṣa miran to yatọ si tiwa.O wu mi lati mu ayipada rere ba awujọ wa lorileede Pakistan''",0,yoruba "Olorin ẹmi kan to fi ilu Akure ṣe ibugbe, Ajihinrere Tolu Adelegan, lo ti sọrọ nipa bi o ṣe gba imisi orin ""Oniduro"" ti o n fa awuyewuye lori ẹrọ ayelujara lati bii wakati mejidinlaadọta sẹyin. Awuyewuye ọhun lo bẹrẹ lẹyin ti gbajugbaja olorin ẹmi, Tope Alabi, fẹnu tabuku orin naa pe o tako ọrọ Ọlọrun. Ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu ile iṣẹ iroyin BBC Yoruba, Adelegan wipe ohun gba imisi orin yii lasiko ti awon ẹgbẹ Akọrin rẹ n ṣe igbaradi orin kikọ ni ọdun 2014 atipe lẹyin naa ni ẹmi mimọ tun dari oun lati kọ ọ nibi ipade itagbangba kan lẹyin eyi. Kí ló fa gbas gbos láàrin Tope Alabi àti Olórin tó kọ ""Oniduro Mi e se""? Mo ti tọrọ aṣọ àti yẹtí etí rí, kí n tó leè ṣe àwo orin - Tope Alabi Lizzy Anjorin yòó ṣayẹyẹ ìkómọ ní ìlú mẹ́wàá ọ̀tọ̀tọ̀ l'Ámẹ́ríkà A kò ní ṣe ètò ìsìnkú TB Joshua ní bòńkẹ́lẹ́ - Evlyn Joshua ""Lọgan ti mo rii pe Yinka Alaseyori ti ṣe ẹda orin mi sita ni mo fi ẹjọ rẹ sun Bisi Alawiye ati Bukola Akinade (Ṣẹnwẹlẹ Jesu) ti wọn jẹ atọnisọna fun Alaseyori, dipo ki n wọ iyaaja pẹlu rẹ"". Adelegan wipe Alawiye ati Akinade ni wọn panupọ ba Alaseyori wi pe ohun kọ lo lorin, bi kii ṣe Adelegan. Olorin ẹmi to fi ilu Akure ṣebugbe ọhun ṣalaye fun BBC Yoruba pe Ọlọrun lo fun oun ni imisi orin ọhun to si wipe ki oun gba alaafia laaye nigba ti Alaseyori ṣe ẹda orin naa. ""Mi o ba Alaseyori ja toripe ọmọ ti mo julọ lọjọ ori ni, amọ mo fi ẹjọ rẹ sun awọn to ju wa lọ nidi iṣẹ orin ẹmi ki wọn ki i nilọ, mo si tun fi si ori ẹrọ facebook. Bakan naa ni Ọlọrun sọ fun mi pe ki n fi ọwọ lẹran pe ọjọ ọrọ o tii to, titi di ana ti Ọlọrun pada sọ fun mi pe ki n sọrọ soke pe ohun yoo ṣe atilẹyin fun mi."" Adelegan ti ko fibẹẹ mọ pe orin olorin ṣee gbe sita tẹlẹ gẹgẹ bo ṣe sọ ni ""mo ṣẹṣẹ mọ nipa bi a ṣe n daabo bo iṣẹ ọpọlọ ni. Mo si ti ṣetan lati ṣiṣẹ le e lori. Koda, ogidi iṣẹ ọhun ṣi wa nibi ti wọn ti poo pọ.""",0,yoruba yorubá tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba èkó aṣà. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa iṣẹ́: ti o jare.,0,yoruba RT @user: I'm ever proud to be YORUBA. èdè yí kò ní parun #yoruba,0,yoruba "Èyí [ ni ọ̀nà kan ] fún ìpèsí àkíyèsí ìjọba João Lourenço , wípé àfilé ìdíyelé kò yẹ nírú àsìkò yìí , nítorí owó náà ti ṣe gegere ju fún àwọn ọmọ ìlú .",0,yoruba olohun alagbara wa bawa dasi oro orilede naijiria ki gbogbo nkan dewa lorun tomode ati agba,0,yoruba ọsẹ àsa. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba "Àgékúrò àwòrán adarí iléeṣẹ́ náà , Irina Reyder ní ọ́fíìsì iléeṣẹ́ BlaBlaCar ti Russia .",0,yoruba kosi fun wa ni emi imo ore ati ma se idupe fun gbogbo ore ti o dekun yi,0,yoruba Ìlú Ọ̀yọ́ jẹ́ ilẹ̀ agbègbè tí ó tìkẹ́ gbfi yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba RT @user: Bi o se wu Oluwa ni nse Ola! http://t.co/n9j2bKw0oT,0,yoruba "ní láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.",0,yoruba "Idi ni pe lọjọ Isẹgun lawọn eeyan kan to n fẹhonu han morile awọn ileesẹ South Africa to wa nilu Ibadan, ti wọn si kọlu wọn, koda, wọn dana sun ileesẹ MTN to wa ni Bodija, ti wọn si ko ọpọ ẹru olowo iyebiye ni ile itaja Shoprite to wa ni Ring Road. Niwọn igba to si jẹ pe ina eesi kii jo ni lẹẹmeji, awọn alasẹ ileesẹ Shoprite to wa ni ibudo itaja Palm Halm ni Ribgroad naa, ti wa sọ agadagodo sẹnu ọna ibudo itaja Palm Mall lapapọ lati dena ikọlu ẹẹkeji. Nigba ti BBC Yoruba se abẹwo si ibudo itaja naa, wa wa wa ni awọn agbofinro gbarodan sẹnu ọna abawọle ibẹ, ti wọn si setan lati wọn esinsin to ba ta firi nibẹ. Koda, awọn osisẹ ati onibara to fẹ wọle sibudo itaja naa ni jẹbẹtẹ gbe ọmọ le lọwọ nigba ti wọn foju kan awọn agbofinro naa, ti ẹnikẹni ko si lee wọle tabi jade latinu ibudo itaja naa. Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, awọn osisẹ ibudo itaja naa salaye pe ọna lati mase jẹ ki itakun kan soso da awọn lepo nu lẹẹkeji lo mu ki awọn alasẹ ileesẹ Shoprite gbe igbesẹ naa, tori owo gọbọi ni wọn padanu lọjọ Isẹgun lasiko ikọlu awọn eeyan to n fẹhonu naa, ti wọn ko ọpọ ọja wọn. Amọ sa, igbesẹ titi ibudo itaja Palm Mall ti n se akoba nla fun awọn ọmọ Naijiria to ni sọọbu sinu ibudo itaja naa nitori kii se Shoprite nikan lo n ta ọja nibẹ. Osisẹ agbofinro agba fun ibudo itaja naa, Tony, salaye pe ọpẹlọpẹ awọn osisẹ agbofinro, ninu eyi ta ti ri awọn ọlọpa atawọn aabo ara ẹni laabo ilu (Civil Defence) ti wọn tete pana ikọlu tawọn ọmọ Naijiria se si ibudo itaja naa lọjọ Isaẹgun eyi ti wọn fi n gbẹsan. Naijiria gbọdọ kẹyin si irẹpọ pẹlu South Africa Igbakeji Aarẹ orilẹede Naijiria ki kesi awọn adari lorilẹede South-Africa pẹlu ibanujẹ ọkan lati dẹkun ipaniyan nitori ẹya to n lọ lọwọ lorilẹede South Africa. Osinbajo lasiko to n ba awọn oniroyin sọrọ ni ipinlẹ Kano, sọ wi pe o lodi si igbelarugẹ ẹto ọmọniyan ti awọn adari ilẹ South Africa ja fun ni igba aye wọn. Ọ̀pọ̀lọpọ̀ adarí ní Naijiria ló ti bu ẹnu àtẹ́ lu ìpànìyàn nítorí ẹ̀yà, pàápàá àwọn ọmọ Naijiria ní South Africa. O ni oun to buru jai ni lati kọju ija si awọn ọmọ Naijiria ti wọn wa ni South Africa bayii, nitori pe Naijiria pẹlu awọn to ja fun ominiran ilẹ naa lọwọ awọn amunisẹru. Òun tọjú àwọn ọmọ Nàìjíríà n rí ní South Áfríkà kọjá afẹnusọ Bẹẹ lo wa kesi ijọba orilẹede naa lati dide ati lati wa wọrọkọ fi sada lori ipaniyan naa ki oun gbogbo le pada si ipo. 'Naijiria gbọdọ̀ kọ ìrẹ́pọ̀ pẹ̀lú SouthAfrica ' Bakan naa, Igbakeji Aarẹ Ile igbimọ Asofin to kọja, Ike Ikeremadu ti kesi ijọba orilẹede Naijiria lati jawọ ninu gbogbo irẹpọ pẹlu orilẹede South Africa, titi ipaniyan awọn ọmọ Naijiria lorilẹede naa yoo fi dopin. Ikeremadu ni o seni laanu pe ijọba orilẹede South Africa fi ọwọ yẹpẹrẹ mu ipaniyan to n waye naa, lo se di ohun to n la ẹmi ọpọlọpọ eniyan lọ. ‘Naijiria gbọdọ̀ kọ ìrẹ́pọ̀ pẹ̀lú South Africa ’ O wa kesi ijọba Naijiria lati ri wi pe ijọba ilẹ South Africa da gbogbo ikolọ awọn ọmọ Naijiria ti wọn bajẹ pada, bakan naa ni ki wọn fi imu awọn aseka yii fọn fere. Ike Ekeremadu naa parọwa si Ajọ isọkan Ilẹ Afirika, Africa Union lati da si ọrọ naa, ki o to di gbọnmi si, omi o to laarin orilẹede mejeeji.",0,yoruba "Ojúmọ́ ire ló mọ́n gbogbo wa. A ò ní tẹ́, a ò ní pòfo, a ò ní pàdánù lónìí o. Elédùmarè ti f'àṣẹ sí i.",0,yoruba "Èyí tí ò rí bẹ́ẹ̀ lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀, ó ṣì ń lọ ní ọ̀nà àrà lábẹ́lẹ́. #TAST #OwoEru",0,yoruba "Ikọ̀ BBC tó wà ní'bi ìwọ́de naa rí bó ṣe ṣẹlẹ̀ Abiy ṣẹṣẹ ba awọn ero sọrọ tan nibi iwọde naa, ni ado oloro ọhun dun. O ṣe apejuwe iṣẹlẹ naa bii iṣe ọwọ awọn ti ko fẹ ki Ethiopa ṣ'ọkan. Wọn tete gbe e sa lọ lẹyin ti eniyan kan ju ado oloro naa si aarin awọn ẹgbẹgbẹrun awọn oluwọde to wa ni orita Meskel to wa ni olu ilu orilẹede Ethiopa, Addis Ababa. Olori orilẹede naa tuntun, Abiy Ahmed ṣẹṣẹ ba awọn ero sọrọ tan nibi iwọde naa, ni ado oloro naa dun Ko ju bii wakati melo kan lọ ti ori ko aarẹ orilẹede Zimbabwe Emmerson Mnangagwa yọ lọwọ ado oloro ti ti Ethiopa naa ṣẹlẹ. Ni kete ti iṣẹlẹ naa waye ni wọn fi olori ile iṣẹ olopa ti Addis Ababa si atimọle pe ko ṣe iṣẹ rẹ to. Wọn tilẹ tun fi ọlọpàá mẹjọ si atimọle pẹlu rẹ. Wọn ni wọn o yẹ ki wọn ṣọ ibi iwọde naa daadaa. Egbẹgbẹrun lo lọ ibi iwode naa fun Abiy Minisita fun Eto Ilera ni Ethiopia sọ pe eniya bii mẹrinlelogoji ni o wa ni ile iwosan bayi ti eniyan marun si wa ni ẹsẹ-kan-aye-ẹsẹ-kan-orun. Abiy di olori orilẹede naa lẹyin ti olori ti tẹlẹ Hailemariam Desalegn, kọ'we f'iṣe silẹ ni oṣu keji ọdun yii. 'Ẹlẹ́dẹ̀ wa ti tó kó jáde síta'",0,yoruba "Mo bi ọ́, ta ni ọ́? #EdeAbinibi #Yoruba #MotherLanguageDay",0,yoruba RT @user: @user @user @user @user @user @user @user @user @user @user Oruko mi ni…,0,yoruba "rere. Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba aláìì dé sí ìbàdandun láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba yoruba mi ko fi be da mo yin ko ise via,0,yoruba "@user: @user Please tell me de phrase: #Bringbackourgirls #InYoruba, i will appreciate that, thank u,""""""""Ẹ dá àwọn ọmọbìnrin wa padà",0,yoruba Coronavirus: Ìwàdìí ní omi ara ẹni tó bá ní àrùn náà leè ta sára ọ́pọ́ èèyàn níbí tí èrò bá pọ̀ sí,0,yoruba owo ṣẹlẹ ni Ibadan ti gbogbo eniyan sọ o dara. (2001),0,yoruba "Awọn eniyan ti bẹrẹ si i ṣe idaro alufaa ijọ Redeemed Christian Church of God, ati ọmọ rẹ meji to ku sinu odo iwẹ nile igbafẹ kan ni Costa del Sol l'ọjọ Aisun ọdun Keresi. Gabriel Diya, ẹni ọdun mejilelaadọta, ati ọmọ rẹ obinrin, Comfort Diya, ọmọ ọdun mẹsan an, to fi mọ ọmọ rẹ ọkunrin, Praise Emmanuel-Diya, ọmọ ọdun mẹrindinlogun ku. Wọn doloogbe lẹyin ti wọn mu omi yo ninu odò iwẹ igbalode to wa ni ile igbafẹ Club La Costa, nitosi Fuengirola ni orilẹ-ede Spain. Awọn ọlọpaa sọ pe awọn n ṣe iwadii ẹsun wi pe ọmọbinrin naa lo wa ninu ewu, ti awọn meji yooku naa si padanu ẹmi wọn lasiko ti wọn n gbiyanju lati doola rẹ. Ijọ ti Ọgbẹni Diya ti jẹ alufaa sọ pe awọn ba ẹbi awọn oloogbe kẹdun. Ijọ RCCG, ninu ikede kan lori Facebook sọ pe: ""Pẹlu ẹdun ọkan, a na ọwọ ibanikẹdun wa si ẹbi, ijọ,ọrẹ, ati awọn alajọṣiṣẹpọ Alufa Agbegbe, Gabriel Diya, to jalaisi, pẹlu ọmọ rẹ meji... ninu iṣẹlẹ to bani ninu jẹ kan to waye lasiko ti wọn lọ fun isinmi l'orilẹede Spain. Ijọ naa sọ pe Ọgbẹni Diya tun jẹ alufaa ẹgbẹ awọn ọmọlẹyin Kristi kan, Open Heavens. Orilẹ-ede Naijiria ni ẹgbẹ naa ti bẹrẹ, ṣugbọn Diya jẹ adari ti agbegbe Charlton, nilu London. Iyawo, Olubunmi Diya, ati ọmọbinrin kan lo gbẹyin oloogbe Diya. Ọkan lara awọn aladugbo idile Diya sọ fun ileeṣẹ iroyin PA pe, ""ibanujẹ lo jẹ fun oun nigba t'oun gbọ iroyin iku naa, to si ṣapejuwe idile Diya gẹgẹ bi eyi to ""gba ẹsìn daada, ni ọyaya, ko ni mọra, to si ni irẹlẹ"". Lara Akins, lasiko to n sọrọ niwaju ita ile rẹ ni Charlton sọ pe ""Iku wọn ba gbogbo eniyan ni ojiji, nitori pe eniyan daadaa ni wọn"". Ọgbẹni Diya ati ọmọ rẹ obinrin ni iwe igbeluu orilẹ-ede Britain, nigba ti ọmọ rẹ ọkunrin ni ti Amẹrika. Ninu atẹjade kan l'Ọjọbọ, awọn alaṣẹ ile igbafẹ Club La Costa World sọ pe iṣẹlẹ naa jẹ ibanujẹ fun awọn"". Ati wi pe awọn yoo ""tẹsiwaju lati fọwọsowọpọ pẹlu awọn alaṣẹ to n ṣewadi iṣẹlẹ buruku naa"". Ṣugbọn ṣaa, wọn ni awọn ti ṣi odò iwẹ pada fun lilo awọn onibaara wọn lẹyin ti ileeṣẹ ọlọpaa ti fun wọn ni aṣẹ lati ṣe bẹ ẹ. Akọroyin abẹle kan, Fernando Torres, sọ fun BBC pe iṣẹlẹ naa jẹ ibanujẹ. ""Awọn oṣiṣẹ ile igbafẹ naa gbọ ti awọn eniyan n pariwo, wọn si gbiyanju lati ṣe itọju pajawiri, CPR, fun wọn, ṣugbọn wọn ko le e ran wọn lọwọ mọ."" ""Koda, awọn dokita pajawiri gbiyanju fun ọgbọn iṣẹju si marundinlogoji, ṣugbọn ẹpa ko b'oro mọ. Ki Olorun dẹ ilẹ̀ fun ẹni rere to lọ, ki O tu awọn ẹbi to ku ninu ni adura ti ọpọ n gba.",0,yoruba "RT @user: Sánbẹ sùn, fapó rọrí. Ìwà ẹni ní mú ni s'òkígbé.... #OweYoruba #Atelewo #Yoruba",0,yoruba "@user I don't pay attention to sienna drivers too, igi ewédú ò ní wó pa wá 🤷🏽‍♀️",0,yoruba "ìlú. Nitori eyi, ara eni lo ni ìgbà mi owó àkokò, Ìyá lo tun se lọ.",0,yoruba omoluabi osinbajo ìwọoòrùn guusu orílẹ̀ èdè nàìjíríà ni a ti bíi ní ifowosowopo pẹ̀lú ààrẹ muhammadu,0,yoruba owo ṣẹlẹ ni Eko ti gbogbo eniyan sọ o ṣe pataki. (1990),0,yoruba "Bi o tilẹ jẹ wi pe amojuẹrọ Seyi Makinde ni oun fesi si ohun ti wọn sọ pe ki wọn jẹ ki oun gbajumọ awọn iṣẹ to dawọle ni lọọlọ yii. Nigba ti BBC Yoruba kan si onimọ nipa ọrọ oṣelu kan ni fasiti ilu Ibadan, Ọmọwe Dikrullahi Yagboyaju ni lakọkọ oun fẹ nigbagbọ pe bi gomina ṣe sọ ọ naa lo ri pe awọn eeyan lo sọ bẹẹ. Ladoja Eyi ni wi pe bo ba ṣe pe lootọ awọn araalu lo n kan sara si iṣẹ rẹ ti wọn si n pe e pe ko lọ fun saa keji ko buru nitori pe awọn oloṣelu lọpọ igba lo maa n fi ọgbọn fi iru ọrọ naa sita lati wo bi awn eeyan yoo ṣe gba a si. Ẹwẹ, ni iha ti awọn araalu to n sọ bẹẹ, Ọmọwe ni o ku diẹ kaato tori gomina gan ko tilẹ tii lo ju oṣu mẹfa lọ ti wọn si ti wa n sare da orin ko wa ṣe dun mẹrin mii. O ni ka tilẹ gba pe gomina ti bẹrẹ saa rẹ daadaa, ""fun emi o, mo ro pe o ti ya ju. Ki gomina le ri orukọ wọn kọ silẹ ninu iwe itan to daa ni ipinlẹ Oyo, agbọgbọn'ti ni ki wọn maa gbọ orin maa jo lọ mo n wo ẹyin rẹ tawọn araalu kan n kọ fun wọn"". O fi we ọmọ ileewe ti ko tii ka ipele ikini yọri na ni fasiti ti wọn ti n sọ fun pe ibi ti yoo ti ṣiṣẹ ree to ba ti pari agunbanirọ rẹ. Ọmọwe Yagboyaju ni ki gomina gbọ ọ̀rọ̀ naa ko kan feti gbọn ọn danu ni ko si yẹ ko tii ka a kun rara lasiko yii. O ni iru orin to yẹ ko maa jade ni pe ""gomina o, a dupẹ lọwọ yin o, ẹ n gbiyanju o, kẹẹ 'se daadaa si ni o"". Ọmọwe ni ẹni to ba mọ nkan to n ṣe gbudọ ṣọra fun apọnju latọdọ araalu. Ni idahun si wi pe ṣe ofin sọ pe asiko kan pato leeyan le kan sara si iṣẹ gomina ati lati sọ pe ko lọ fun saa kan sii, Yagboyaju fesi pe ohun gbogbo lo lasiko tirẹ. ""Bi oloṣelu ba n ṣe awọn nkan to ṣe adehun rẹ nigba ipolongo, o yẹ ka lu wọn lọgọ ẹnu lootọ pe wọn ṣe daa ṣugbọn fun ẹni to ba ni arojinlẹ a mọ pe 'a fẹ kẹ ṣe saa kan sii' ko tii kan iyẹn rara"". Ipa aidaa to wa ninu bi gomina ọhun ba wa gba nkan ti wọn sọ gbọ, ti ara rẹ ya sii, to si ti n fi huwa, o lee ṣi ẹni to n ṣe daadaa ọhun gan lọna. O yẹ ko tẹ ẹ jẹjẹ ni, a mọ pe gomina Seyi Makinde n ṣiṣẹ daadaa ṣugbọn ko fi apẹrẹ ọmọ ile iwe ti oun sọ fi kọgbọn, ko kawe mẹrin akọkọ rẹ ja na. O ni ki awọn araalu gaan ma ṣe ti gomina gbọọn gbọọn.",0,yoruba ẹkọ́ ṣẹlẹ ni Ibadan ti gbogbo eniyan sọ o ṣe pataki. (2008),0,yoruba "Gẹgẹ bi awọn iroyin iwe iroyin abẹle kan ṣe gbe, adajọ Majistreti M. O. Tanimọla paṣẹ naa larin ọsẹ to kọja nigba ti wọn gbe ẹjọ naa wa siwaju rẹ. Ọlanrewaju Saheed to jẹ ọkọ Ronkẹ Odusanya rọ ile ẹjọ naa lati paṣẹ fun ayẹwo DNA naa lati mọ boya lootọ oun ni baba ọmọ naa nitori oun n funra pe irin ẹsẹ iyawo oun ko mọ. Gẹgẹ bi a ṣe gbọ, agbẹjọro fun Ronkẹ ididowo ko ba a jiyan lori rẹ, nitori oun naa gba bẹẹ pe ki wọn ṣe ayẹwo naa. Bayii ti ile ẹjọ naa si gba lati ṣe atọna ayẹwo ọhun ni ileewosan ti wọn ko ni darukọ nibi ti wọn yoo si ti fi esi rẹ ṣọwọ si ile ẹjọ naa taara. Ọdun kan ati oṣu diẹ sẹyin ni Ronkẹ Odusanya bi ọmọbinrin rẹ nileewosan kan loke okun. Ki lawọn eeyan n sọ lori rẹ? Amọ bayii awọn ololufẹ elere itage naa ti n fọnmu lori rẹ. @hotyjay ni ""Ọmọ jọ ẹ bayii o si tun n wa ayẹwo DNA? O dara o, ohun oju rẹ n wa, yoo rii o."" @Studedsavage ni tirẹ kọ pe "" Ọmọ ti mo rii yii jọ baba rẹ bi imumu ni o. O fẹ fi iwọnba owo to ku ti Ronkẹ ko tii gba ṣofo leyi o."" @kxngrivo ni tirẹ kọ wi pe, ""O san ni kiakiao, mo ti ri ọkunrin kan to jẹ wi pe mẹrin ninu awọn ọmọ rẹ ni kii ṣe tirẹ. Bẹẹ, eyi to kere ju ninu wọn, ọmọ ọdun mejidinlọgbọn ni. bawo ni baba ẹni ọdun marundinlaadọrin tun aye rẹ to o. Yara tete ṣe e bayii o arakunrin mi."" @marigoldconcepts, "" ka maa wulẹ bopo lọle olooro lori ayẹwo DNA o, ẹda baba rẹ ni ọmọdebinrin yii o"" Ẹ̀yin olórin ẹ̀mí tó ń bóra, lo èékáná gígùn, oò yàtọ̀ sí aṣẹ́wó hòtẹ́ẹ̀lì tí wọ́n ń gbé bíi súùtì Pepper Menti - Bola Are",0,yoruba iṣẹ́ ni nkan pataki lojiji. Ìyá lo tun se joko. Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba Ẹyẹ náà ti ń dínkù látàrí ìgbẹ́ pípa fún iṣẹ́ ọ̀gbìn àti ìtẹ́lọ ìgbèríko di ìgboro .,0,yoruba "si ìlú.. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Nitori eyi, ara eni lo ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "RT @user: """"""""""""""""@user: A bí wa nílé ẹran, a sì ń hùwà àgùntàn. Ṣé nítorí olùbọ̀bọ̀tiribọ̀ yìí náà ṣá? Ṣíọ̀ kẹ̀lẹ̀bẹ̀! Kilonje olu…",0,yoruba "Ìyàwò kejì tó fi owú ré ọkọ bọ́ láti òkè pẹ̀tẹ́sì gba ìdájọ́ ikú Lónìí ọjọ jimọ ni adajọ AT Badamosi dájọ fún ẹni ọmọ ọdun mọ́kanlélọ́gbọ̀n kan Rashida Saidu nitori pe o jẹbi ẹsùn ìpànìyàn ikú ọkọ rẹ Adamu Ali nitori pe o ti wọ́n láti ori ilé alaja. Ogunjọ oṣù keji ọdun 2019 ni iṣẹ̀lẹ̀ náà ti ṣẹ̀lẹ̀ ni àgbègbè Dorayi ni Kano lásìkò ti òun ati ọkọ rẹ̀ ni gbolohun asọ. Ìjà bẹ́ silẹ̀ nígbà to gbọ́ pe ọkọ oun ń bá obinrin ti o fẹ̀sun kan pe o jẹ ọ̀rẹ́binrin rẹ̀ sọ̀rọ̀ lóri foonu Lẹ́yin to ti jabọ lo ti wà ni ẹsẹ̀ kan aye ẹsẹ̀ kan ọ̀run, eyi si lo bá kú. Gẹ́gẹ́ ìròyìn ṣe sọ, ọmọ meji ni Rashida bi òun lo ni ilé ti wọ́n gbé, bákan náà oun ni ìyàwò ẹlẹ́kiji Adamu lásìkò ìṣẹ̀lẹ̀ náà. Kí wọ́n to ṣe igbéyawò, wọ́n pàdé ni Federal College of Technology ni Kano nibi ti wọ́n ti pada fẹ́ àra wọ́n. Sáájú kii Rashida to pa ọkọ rẹ̀ ni o ti sọ fun ọ̀rẹ rẹ̀ ti wọ́n jọ n gbe pe ki o dúró náà sùgbọ̀n ko gbọ́ osi gba ilé lọ ti iṣẹ̀lẹ̀ aburu náà fi ṣẹlẹ̀.",0,yoruba "Ọkùnrin kan, Terhemen Anongo, ẹni ọdún mẹ́rìnlélógójì tí kò lè tẹ̀síwájú nínú ẹ̀kọ́ ìmọ̀ ìṣègùn òyìnbó ní ipele karùn-ún ní ilé ẹ̀kọ́ gíga fásitì Ìbàdàn ti yọ kórópọ̀n rẹ̀ kejì. Ìwé ìròyìn The PUNCH tí kọkọ fi ìròyìn kan léde nínú oṣù kẹta ọdún 2021 nípa arákùnrin náà tó yọ kórópọ̀n rẹ àkọ́kọ́ lẹ́yìn tó di ẹni tó ń ti ọmọlanke látàrí àìlè tẹ̀síwájú nínú ẹ̀kọ́. Anongo ní nítorí òun kò nì ìyàwó pẹ̀lú ìgbàgbọ́ òun nínú ẹ̀sìn àti ohun tí òun kà nípa Origen Adamantius tó jẹ́ adarí ẹ̀sìn nígbà kan rí ní Egypt ló fún òun ní ìwúrí láti tẹ ara rẹ̀ lọ́dà. ""Nígbà tí mo fẹ́ yọ kórópọ̀n àkọ́kọ́, ẹ̀jẹ̀ pọ̀ tó ya lára mi, èyí tó mú mi sá lọ sí ilé ìwòsàn fún ìtọ́jú"". Kìí ṣe ilẹ̀ Afíríkà ni mo wà nígbà tí mo kọ́kọ́ wá sílé ayé - àṣírí ọ̀rọ̀ tuntun rèé lẹ́nu Mummy G.O Dayo Kujore: Àgbà olórin juju dágbére fáyé pé ó dìgbòóṣe! ""Ṣùgbọ́n nígbà tí mo fẹ́ yọ ẹlẹ́kejì, mo ti kẹ́kọ̀ọ́ níbi ti àkọ́kọ́, mo ṣe é dada. Ẹnìkan ń wá bámi tọ́jú rẹ̀"". Ó ní ìgbàgbọ́ òun nínú ẹ̀sìn ni òun fi yọ ọ́ àti pé àláfíà ni òun wà.",0,yoruba "Ileesẹ ọlọpaa nilẹ Ghana ti wa fidi rẹ mulẹ pe awọn ti ri oku mẹtala lara awọn akẹkọ naa to ku sinu okun ti wọn ti n luwẹ letikun Apam lọjọ Aje, ọjọ Kẹjọ osu Kẹta. Atẹjade kan ti ileesẹ ọlọpaa ni Ghana fisita salaye pe meji ninu awọn akẹkọ naa ni wọn ri laaye leti okun ọhun, nigba ti wọn ri oku akẹkọọ mejila. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọga ọlọpaa Irene Oppong to wa ni ẹka to n gbọ ọrọ araalu nilu Cape Coast ni ọkunrin kan, Kwame Akono lo mu ẹsun nipa isẹlẹ naa tọ oun wa. ""Deede aago mẹsan ku ogun isẹju ni ọkunrin naamu ẹsun tọ wa wa pe ọmọ ẹgbọn oun, Joshua Annor, tii se ọmọ ọdun mẹẹdogun lo lọ gba bọọlu leti okun, to si ri sinu rẹ pẹlu awọn ọmọ miran. Idi niyi ta fi tete morile eti okun naa pẹlu ikọ ti yoo wa awọn ọmọ naa jade, Ọlọrun si ba wa se, a ri Simon Dadzie, ọmọ ọdun mẹẹdogun ati Gogffrey Apperetsie, ọmọ ọdun mẹrinla yọ laaye."" Oppong fikun pe awọn akẹkọ mejeeji yii lawọn tete gbe lọ sile iwosan ijọ Aguda ti Luke fun itọju to yẹ. Akomolede àti Asa: Mọ̀ si nípa àṣà ìsọmọlórúkọ́ nílẹ̀ Yorùbá àti ìtumọ̀ orúkọ̀ fún ìkókó O ni awọn oku awọn akẹkọọ tawọn ri ni aarọ ọjọ Aje ni ọjọ ori wọn wa laarin ọdun mẹrinla si mẹtadinlogun, ti oku ọmọbinrin meji si wa laarin wọn. O ni awọn oku awọn ọmọbinrin mejeeji naa lawọn gbe lọ sile igbokusi to wa nile iwosan fun ayẹwo to yẹ, ti iwadi si ti n lọ lọwọ lati mọ iru iku to pa awọn akẹkọ naa. Adebunmi Adeyeye: Mo jẹ gbèsè gbọ́múléláńtà, ìdí iṣẹ́ kabúkabú ni mo ti ri san Amọ sa, wọn ti sin oku awọn akẹkọ mẹtala ọhun lapapọ loni ọjọ Isẹgun, kutu hai si lawọn mọlẹbi wọn ti de sile iwosan katoliki Luke nibi ti wọn gbe oku awọn ọmọ naa si.",0,yoruba @user Ẹ nlẹ́ o. Ẹ kú ọjọ́ mẹ́ta. ṣé gbogbo ẹ̀ nlọ déédé?,0,yoruba "Lara awọn ohun manigbagbe to nii se pẹlu owo ẹru to wa ni Badagry ni ọpọ kanga ti awọn ẹru gbẹ. Lasiko irinajo wa naa, a ri kanga agboole Seriki Abass, ti wọn kọ lọdun 1847 eyi ti wọn pe ni Brazilian Barracoon. Bakan naa la tun ri kanga ti wọn gbẹ lọdun 1842, eyi ti ẹru meje pere gbẹ, ti wọn n pe ni omi iye, taa mọ si water of life abi Miracle water. Kanga ọhun si ni wọn gbẹ lati fi ri omi kọ pẹtẹsi akọkọ lorilẹede Naijiria to wa nilu Badagry, ta si tun gbọ pe kanga yii mọ ju ọpọ kanga ti wọn sẹsẹ gbẹ ni Badagry lọ nitori ko ni eroja iyọ ninu gẹgẹ bii awọn yoku. Kanga miran ta tun foju ri ni kanga to maa n ko ọpọlọ ẹru lọ, ki wọn to tẹkọ leti lọ soke okun. A gbọ pe awọn ẹrun naa ni awọn oyinbo yoo fun ni omi mu tẹrun, ki ori wọn ma baa pe, lati kọlu wọn loju omi.",0,yoruba "kún jú, àwọn ènìyàn ni ó pa Bàbá lo aye àìlẹ̀.",0,yoruba ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ẹkọ́: ti o ní wúlò.,0,yoruba lòdì Ìjẹ̀. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ẹkọ́: ti o nuni ti o jare.,0,yoruba "fi, Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba Igbéwọlé Kùnà,0,yoruba "A ṣe ọkunrin to n fi Hijab bori ni Imam gbe ni iyawo sile O ba Sheikh Mohammed Mutumba lojiji lẹyin ọsẹ meji igbeyawo wọn lati ri i pe ọkunrin ni iyawo oun, Swabullah Nabukeera to tin n wọ hijab lati ọjọ yii ati wi pe orukọ rẹ gangan ni Richard Tumushabe. Aṣiri yii tu sita nigba ti awọn ọlọpaa orilẹ-ede Uganda mu Tumushabe nigba ti wọn fura pe o ji ẹrọ amohunmaworan ati aṣọ awọn aladugbo wọn nile ti oun ati ọkọ rẹ n gbe. Gẹgẹ bi iṣe awọn ọlọpaa, ọlọpaa obinrin yẹ ara afurasi yii wo finifini ki wọn to mu u lọ si ẹwọn. Ṣugbọn iyalẹnu lo jẹ fun ọlọpaa naa lati ri i pe o di aṣọ sinu kọmu rẹ lati fi ṣe bii pe ọmu rẹ ni. Iroyin naa ni pe Sheikh Mutumba to jẹ Imam ni Mọṣalaṣi ilu Kyampisi ni Kampala, olu ilu orilẹ-ede Uganda ko tii ba iyawo rẹ lajọṣepọ kankan tori pe o ni oun n ṣe nkan oṣu lọwọ. Ifa Priest: ọdún mọ́kànlá ni mo fi ṣe iṣẹ́ agbejọ́rọ̀ kí n tó gbọ́ràn si Ifá lẹ́nu Nitori eyi, ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn ti fi ẹsun ki eeyan dibọn bii ẹlomiran, ole jija ati kiko nkan pẹlu idanimọ ẹlomiran. Iwe iroyin Daily Moitor royin pe Sheikh Abdul Noor Kakande to jẹ adajọ agba Musulumi (regional kadhi) fun ẹkun naa sọ pe iṣẹlẹ naa ṣe ni laanu jọjọ awn si ti n ṣewadi Imam naa. Bakan naa, wọn royin gẹgẹ bi Sheikh Isa Busuulwa to jẹ Imam Mọṣalaṣi ti Sheikh Mutumba ti n waasu pe wọn ti jawe lọ gbele ẹ fun un lati lee da abo bo ofin ẹsin Islam. Jide Kosọkọ: Isẹ́ tíátà yóò gòkè tíjọba bá gbówó kalẹ̀ láti seré Fun ọjọ mẹrin, iwe iroyin Daily Monitor fabọ jẹni pe Sheikh Mutumba ko tii si nile. Eeyan kan ti ko fẹ darukọ rẹ sọ pe ""iṣẹlẹ naa da a lagara gan o si nilo imọran gidi"". Eduardo: Mo ń jí mọ́tò pẹ̀lú àwọn ọ̀rẹ́ mi nítorí pé mo fẹ́ di 'Big boy'",0,yoruba Fi_déètì hàn,0,yoruba olupese ni oluwa oba ti ng pese fun eda ebi owuro ebi osan ati ale ma je ko paa mi loni ati gbogbo ojo aye mi,0,yoruba Ó kùnà láti rí pixmap %s,0,yoruba Awon idije t'oki lo daruko yen #yoruba https://t.co/8aXRXgGvt8,0,yoruba "RT @user: """"""""""""""""Ó dára, Jọkẹ́. Kí a pa Yẹ́misi tì. Délé ńkọ́? Kí ni èrò rẹ nípa Délé? Ǹjẹ́ lè jí alùmọ́gàjí náà gbé? Yorùbá Detective Fi…",0,yoruba Ọ̀yọ́ jẹ́ ìlú tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọba lo ni àṣà yorubá eyti o gbe lori àìmọ́ kọ.,0,yoruba O leè ká apá kejì ìròyìn náà níbí .,0,yoruba 2. Ọba ti Èkó ____ ti Àjàṣẹ́-ìpó (Kúwárà) Iba ti Kìṣí (Ọ̀yọ́) ____ ti Oǹdó Jagun ti Ayétòrò #Ibeere #Yoruba,0,yoruba àsa. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ài: ti o nuni ti o jare.,0,yoruba "lòdì Àbẹ́òkúta. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Nitori eyi, ara eni lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gblọ yóò ni Nitori eyi, ara eni lo.",0,yoruba "RT @user: Èdùmàrè dá mi dáa, mo dúdú dáa, ìpolówó ọjà orí amóhùnmáwòrán àti ìwé ìròhìn ti kó wọ àwọn èèyàn lórí. #arabibo #bleach #ad…",0,yoruba "Ní ibi ìfẹ̀hónúhàn ní Luanda , àmì náà sọ pé “ 30 . 500 Kwanzas kì í ṣe kékeré """""""" .",0,yoruba "Ní ní àìlẹ̀, Ìyá ri Nitori eyi, ara eni yi ojú òní. ti Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "lo mú. Nitori eyi, ara eni lo ni ẹ̀ká àwẹ eyti o gbe lori àìmọ́ kọ.",0,yoruba "Ilà ẹ̀rọ-ìbánisọ̀rọ̀ọ àti àwòrán jẹ́ méjì ń'nú ìwífún tí ó yẹ kí a fojú sí. Àwòrán, ní pàtàkì, lè yọ́ mínrín so ìṣàmúlò tí o fẹ́ jẹ́ ó dá wà pọ̀. Èyí wọ́pọ̀ ní ibùdó ẹni-tó-ń-wá-ọkọ-wá-aya àti àkáùntì onímọ̀.",0,yoruba "Kazeem Taimiyu ni igbakeji balogun ẹgbẹ agbabọọlu Remo Stars nigba aye rẹ Ẹni ọdun mọkanlelogun ọhun, to n gba bọọlu fun Remo Stars, ni ọkọ gba, to si gba ibẹ ku, ṣugbọn ẹgbẹ agbabọọlu rẹ sọ pe awọn ọlọpaa lo pa a. Ọrẹ rẹ kan naa to sọ pe iṣẹlẹ naa ṣoju ohun naa sọ fun BBC pe awọn ọlọpaa SARS lo ṣokunfa iku rẹ. Saani: Gbogbo egungun Tiamiyu ló kán lẹ́yìn tí wọ́n tì í jábọ́ nínú ọkọ̀ Nibi eto isinku na to waye ni Ọjọbọ, ọjọ kẹtadinlọgbọn, oṣu Keji, ni awọn ẹbi, ọrẹ ati akẹẹgbẹ rẹ ti kopa, wọn si wọ Tiamiyu ni aṣọ funfun, ti wọn si sin ni ilana ẹsin Islam. Agboole ẹbi rẹ to wa ni Ajaka nilu Sagamu nipinlẹ Ogun ni wọn sin si. Ṣe ko si obi to gbadura lati f'oju sunkun ọmọ, ẹ gbọ nkan ti awọn obi oloogbe Tiamiyu ba BBC Yoruba sọrọ nipa rẹ. 'Mo fẹ́ ìdájọ́ òtítọ́ àti òdodo lóríi ikú àìmọ̀dí tí wọ́n fi pa ọmọ mi' Aarẹ ẹgbẹ agbabọọlu Remo Stars, Kunle Soname, ati Aarẹ ajọ to n mojuto bọọlu gbigba ni Naijiria, NFF, Amaju Pinnick naa ti lọ ba ẹbi oloogbe kẹdun l'ọsẹ yii. Jakejado Naijiria ni awọn eniyan ti koro oju si iru iku to pa Tiamiyu, nitori bi iroyin ṣe sọ pe lasiko ti awọn ọlọpaa SARS da a duro sinu ọkọ wọn lo pade iku ojiji. Eyi si mu ki ọpọlọpọ olugbe ilu Sagamu ṣe iwọde, ti awọn eniyan fi n beere fun idajọ ati ipolongo pe ki wọn o pa ẹka ọlọpaa SARS rẹ. Eniyan mẹta si ni iroyin tun sọ pe o padanu ẹmi wọn nibi iwọde naa, ti awọn ọlọpaa si sọ pe awọn ṣi n ṣe iwadii awọn ẹsun yii. Ọpọlọpọ olugbe ilu Sagamu lo kopa nibi iwọde naa. Ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe ọlọpaa to lọwọ si iṣẹlẹ naa ti wa ni ihamọ, ati pe wọn ti gbe e lọ si ẹka ileeṣẹ ọlọpaa ti wọn ti n ṣewadi iwa ọdaran. Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa, Frank Mba sọ fun BBC pe ""iwadii ṣi n lọ lọwọ, ileri wa si awọn ọmọ Naijiria si ni pe a ko ni ṣe mago-mago tabi fi ohunkohun pams nipa iwadii naa"".",0,yoruba "Ọrọ lori ibo gomina Ọgagun Burutai ni awọn eeyan kan n gbero lati tajẹ silẹ, bẹẹ ni wọn si fẹ ju ado oloro lati da ibo iru lọjọ Satide. Ṣugbọn Burutai ni ile iṣẹ ologun ko ni gba wọn laye lati mu ipinnu wọn ṣẹ. Oyo Election: Makinde ní ìpínlẹ̀ Ọyọ kò fk ajẹ́lẹ̀ mọ́ Ọgagun BUrutai fọrọ yii lede nibi ipade to ṣe l'Abuja l'Ọjọru pẹlu awọn lọgalọga ninu iṣẹ ologun. Burutai salaye pẹlu ẹdun ọkan pe, awọn ọmọgun mẹta ati oṣiṣẹ eleto idibo kan padanu ẹmi wọn lasiko ibo aarẹ lọjọ kẹtalelogun oṣu keji to lọ. O fi asiko ipade naa kilọ fawọn ologun lati mase tẹle olosẹlu kankan lasiko idibo ṣugbọn ki wọn gbiyanju lati dẹkun iwa jagidijagan lasiko ibo.",0,yoruba "Ẹ̀ṣọ́ Ọ̀yọ́. Ìgbàgbọ́ ni wípé wípé, àwọn ẹ̀ṣọ́ bíi ológun kúrò ní Ọ̀yọ́, lábẹ́ ìṣàkóso àbúrò Aláàfin, pẹ̀lú ohun ìjà wọn, láti lọ tẹ̀dó sí ìletò ní tòsí Òwu. Wọn kò tíì tẹ Abẹ́òkúta dó ní ìgbà náà. Ẹ̀gbá Ìgbẹ̀yìn: the Ẹ̀gbá proper. The principal",0,yoruba "Bakan naa lo kede pe oun ti se alaye lori owo ti wọn ri ko jọ fun iwọde naa, ti apapọ rẹ jẹ miliọnu mẹtadinlaadọjọ naira. Ọjọbọ ni ẹgbẹ Feminist Coalition kede pe oun ko ni ni ohunkohun se pẹlu iwọde kankan mọ. O salaye pe asẹ ti aarẹ Muhammadu Buhari pa ninu ọrọ to ba awọn ọmọ Naijiria sọ, pe ki wọn fi opin si iwọde wọn, lo mu ki oun se ipinnu ọhun. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: O wa rọ awọn alatilẹyin ẹgbẹ naa nilẹ yii ati loke okun, lati dẹkun fifi owo sọwọ sinu apo asunwọn ẹgbẹ naa ti wọn fi n ko owo jọ, eyi towo inu rẹ bayii jẹ miliọnu lọna mẹtadinlaadọjọ naira. Bakan naa ni ẹgbẹ Feminist Coalition tun rawọ ẹbẹ sawọn ọdọ pe ki wọn dẹkun iwọde naa, niwọn igba ti aarẹ ti ba araalu sọrọ, ti ko si mẹnuba ohunkohun to nii se pẹlu ibọn yinyin to waye ni Lekki. O ni dipo bẹẹ, se ni aarẹ Buhari se atilẹyin fun ikede konile o gbele to wa lawọn ipinlẹ kan lorilẹede yii, to si rọ awọn eeyan lati dẹkun iwọde fun aabo ẹmi wọn. Ko tan sibẹ, ẹgbẹ Feminisit Coalition tun pẹlu alaafia ni awọn oluwọde EndSARS fi n se iwọde wọn yika Naijiria, ti wọn si safihan iwa ọlọgbọn. ""Amọ nibi ti ọrọ de bayii, a gbọdọ daabo bo ẹmi ara wa ati tawọn ọmọ ẹgbẹ wa pẹlu."" Nipa ti owo ti wọn ri kojọ, tii se miliọnu lọna mẹtadinlaadọjọ naira fun iwọde naa, o ni awọn ti na miliọnu lsna ọgọta ninu rẹ laarin ssẹ meji, gẹgẹ bi alaye to wa lori ayelujara wọn. Alaye bi wọn si se na owo naa ree: Super Eagles, ẹ máṣe gbá bọ́ọ̀lù fún Nàìjíríà mọ́ nítorí ìhà tí ìjọba kọ sí ìwọ́de EndSARS - John Ogu Atamatase ẹgbẹ agbabọọlu Super Eagles, John Ogu ti ke si awọn akẹgbẹ rẹ, lati maṣe kopa ninu ifẹsẹwọnsẹ Naijiria to n bọ lọjọ iwaju. O ni oun n pe ipe naa nitori iha ti ijọba apapọ kọ si iwọde End SARS. Agbabọọlu naa, to ti gba bọọlu fun Naijiria ni igba mẹrindinlọgbọn sọ pe, ṣiṣe bẹẹ yoo jẹ ki ijọba apapọ mọ bi ọrọ ṣe gbona si lara wọn. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: O ni kawọn oloselu kesi awọ̀n ọmọ wọn lati maa lọ soju Naijiria ninu ifẹsẹwọnsẹ Super Eagles to n bọ Kii ṣe Ogu nikan ni ọmọ Naijiria to jẹ agbabọọlu to bu ẹnu atẹ lu ọwọ ti ijọba fi mu iwọde naa, paapaa lẹyin ifẹmiṣofo to waye ni Lekki. Ṣaaju ni Odion Ighalo, to n gba bọọlu fun Manchester United nilẹ Gẹẹsi, ti kọkọ sọ pe ""itiju nla gbaa"" ni ijọba Naijiria jẹ lẹyin ikọlu Lekki. Ajọ ajafẹtọ ọmọniyan lagbaye, Amnesty International sọ pe ko din ni eeyan mejila to ku nibi iṣẹlẹ naa. Ṣugbọn ileeṣẹ ologun ti sẹ pe ohun ko mọ ohun nipa iṣẹlẹ to waye ni Lekki, bẹẹ na ni ijọba ipinlẹ Eko naa ni oun ko mọ ohunkohun nipa rẹ, ti Aarẹ Muhammadu Buhari naa ko si sọrọ. Iwọde End SARS bẹrẹ lati pe fun opin si ẹka ileeṣẹ ọlọpa to n ri si iwa idigunjale, SARS, lori iwa aṣemaṣe ti wọn n wu ati bi wọn ṣe n tẹ oju ẹtọ awọn eeyan mọlẹ. #EndSARS : Àwọn ọ̀dọ́ dáná sun tírélà akẹ́rù tẹrùtẹrù ní Ekiti",0,yoruba ( CC BY - NC - ND 2 . 0 ),0,yoruba ronu oju lalakan fin sori,0,yoruba lòdì Ìjẹ̀. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọba lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó.,0,yoruba "onà.. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "ASUP Strike: Gbogbo ilé ìwé gbogbonìsẹ di títì pa Olóri ẹgbẹ́ ASUP, Usman Dutse tó bá BBC sọ̀rọ̀ sàlàyé pé, ìyàṣẹ́lódì yìí wáye nitori etí ọ̀gbọin tí ìjọba àpapọ̀ kọ sí ṣíṣe àmúlò àdéhùn ọdún 2009 àti 2017 tí wọ́n bá àwọn ọmọ ẹgbẹ́ ṣe. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ASUU Strike: Bí àwọn kan se dunnú, làwọn kan fajúro Àwọn ọmọ ẹgbẹ́ ASUU fẹnukò láti gùnlé ìyanṣẹ́lódì yìí, léyìn ìpàdé àwọn ìgbìmọ aláṣẹ ẹlẹ́kẹtàléláàdọ́rún rẹ̀ tó wáyé ní ọjọ́ kọkàndílọ́gbọ̀n oṣù kọkànlá ọdún yìí. Dutse sàlàyé pé, ẹgbẹ́ nírètí pé gbogbo ọmọ ẹgbẹ́ pátápátá láwọn ilé ẹkọ́ ìjọba jákèjádò orilẹede yii ni yóò kópa nínú ìyanṣẹ́lódì náà. Tẹ ò bá gbàgbé, ìyáṣẹ́lódì yìí tún ti kún àwọn ẹgbẹ olùkọ́ ti Fasiti tó gùnlé ìyanṣẹ́lódi láti ọjọ́ kíní oṣù kọkànla.",0,yoruba "Ọwọ́ọ wa yóò ma jí sówó, ajé á máa bá wa gbé láti ònìí ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ Ajé lọ, títí láí #ase #yoruba",0,yoruba "Àìmọ́ ni ó pa Alàji lo ni ìgbà mi owó àkokò, Ọba ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn.",0,yoruba "Keyamo dójú ti ara rẹ̀ àti ìjọba tó ń sìn bó ṣe kéde ìtàkurọ̀sọ rẹ̀ pẹ̀lú Eedris fáyé - Amofin Ẹpọ̀n àgbò kàn ń mì lásán ni lórí ètò ààbò Nàíjíríà tó mẹ́hẹ, kò ní já - Obasanjo Iyabo Ojo àti Foluke Daramola tako ara wọn lórí ọ̀rọ̀ Baba Ijesha Lati fi idi ọrọ naa mulẹ, Keyamo fi gbogbo itakurọsọ lori ẹrọ ilewọ wọn sita loju opo Twitter. O fi kun pe Abdulkereem bẹ oun lati mu u mọ minisita eto irinna, Rotimi Amaechi ati akọwe ijọba Boss Mustapha, to fi mọ agbejọro ijọba Naijiria Abubakar Malami. Lẹyin eyi ni Abdulkareem sọ loju opo instagram rẹ pe lootọ ni oun ke si Keyamo nigba ti ara iya oun ko ya nitori oun ro pe ẹbi oun ni Keyamo. O dabi ẹni pe eyi ko tẹ akọrin naa lọrun lo fi tun pada lọ se awo orin fun Keyamo to pe akọle rẹ ni Jagajaga Ti Get E fun Keyamo to jẹ amofin agba Naijiria. Ni ibẹrẹ orin naa ni Abdulkareem ti kọ pe ""Keyamo, o gba ipo ni ọdun 2018. ""Mo ro pe akẹgbẹ kan naa ni wa, mo lero pe iyatọ yoo wa ninu iṣejọba rẹ nitori naa ni mo se kọ orin 'Obasanjo Write Buhari Letter' lati ran o lọwọ ninu nkan ti o n ṣe. ""Lootọ ni ọpọ lo fẹran Buhari ti wọn si gbaruku tii, sugbọn a kaba mọ rẹ."" Ni ipele akọkọ orin naa ni Abdulkareem ti kọ pe, ""Keyamo ijoba rẹ kun fun abosi. Ko si ifọkanbalẹ lorile-ede yii mọ, wọn n ji awọn ọmọ gbe nile iwe wọn, ẹjẹ n san lawọn igberiko, iwa alakatakiti lo kun inu ijọba, abi o fẹ faṣọ bo ọrọ Pantami pe ko niṣe pẹlu awọn agbesumọmi?"" Eyi si lo mu ki Senior Advocate of Nonsense maa tan ka loju opo Twitter ti ọpọ awọn ọmọ Naijiria si n sọ ero okan wọn. Diẹ lara nkan ti wọn sọ ree.",0,yoruba Dúrọ́wà tó ta síta láti fi àwọn wúnrẹ̀n mìíràn pamọ́,0,yoruba "Sunday Igboho ke gbajare sita pe gende mẹẹdogun mu iwe wa sile oun pe Ọga ọlọpaa fẹ ri oun. Akọwe agba fẹgbẹ YCE, Dokita Kunle Olajide lo fi atilẹyin rẹ han wipe, o dara bi Igboho ṣe kọ ipe naa, nitori ejo lọwọ ninu. Olajide ni Igboho lasẹ lati mase tẹwọ gba iru lẹta bẹẹ lọwọ awọn ti ọga agba ọlọpaa fi ran nitori bi nkan ṣe ri lorilẹede Naijiria. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ''O buru jai ki Ọga agba ọlọpaa fi iwe pe Igboho lati ilu Ibadan wa si ilu Abuja pẹlu bi oju ọna ṣe ri lorilẹede Naijiria. Sunday Igboho latest: Sunday Igboho kò gba 'Award'ti a fún un ní Ogo Yorùbá nítorí inú rẹ̀ ''Ti awọn ọlọpaa ba ni ibeere fun Igboho, awọn ọga ọlọpaa to wa ni ilu Ibadan le ṣoju Ọga ọlọpaa, lai si wi pe wọn rin irinajo lọ si ilu Abuja."" Akọwe ẹgbẹ awọn agbaagba ni ilẹ Yoruba naa ni ki ọga agba ọlọpaa tẹle ilana awọn ọlọpaa nitori o ni awọn kọmiṣọna ni abẹ rẹ, to le ṣiṣẹ fun un ni ilu Ibadan lai de Abuja. ''Nitori to ba jẹ emi naa, n ko ni gba lẹta ọhun, nitori a ti ri awọn to gba lẹta saaju ri, to jẹ ado oloro to bu gbamu lo wa ninu rẹ'' ''O tilẹ lewu ki eniyan gbera lati ilu Ibadan lọ si ilu Abuja pẹlu bi awọn oju ọna ṣe lewu lati gba lasiko yii.'' Pure Water Lylon Art: Adejoke ní ohun èlò ta fi ọ̀rá ṣe ń ní àlòpẹ́, kìí tètè jẹ Bakan naa lo kesi ẹka eto aabo lorilẹede Naijiria lati ṣiṣẹ wọn bi iṣẹ, ki wọn ye e fari apa kan, da apa kan si ni idi iṣẹ wọn. Kunle Olajide fikun wi pe, ọpọ igba ni ẹgbẹ awọn Fulani darandaran, Miyetti Alah ti n sọrọ kubakugbe lori afẹfẹ, ti ko si si ẹni to fi iwe pe wọn, ki wọn wa jẹjọ. Àwọn èèkàn ọmọ Yorùbá tí ìràwọ̀ Sunday Igboho bo tiwọn mọ́lẹ̀, ló ń dọdẹ rẹ̀ - Fani-Kayode Awọn ọmọ Yoruba kan ti n fesi lori iwe ipe ti ọga agba ọlọpaa fi ransẹ si ile Oloye Sunday Igboho lọjọbọ. Sunday Igboho lo pariwo sita pe awọn eeyan kan, ti wọn pe ara wọn ni ọlọpaa, mu iwe kan wa si ile oun. O ni awọn gende mẹẹdogun to wa sile oun naa sọ pe ọga agba ọlọpaa lorilẹede Naijiria lo n pe oun. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Amọ nigba to n fesi lori isẹlẹ yii, Minisita feto irinna ofurufu tẹlẹ, Fẹmi Fani Kayode ke si ijọba apapọ pe ko ṣe pẹlẹ lori ọrọ Sunday Igboho. Fani-Kayode, ẹni to se ikilọ naa loju opo Twitter rẹ ni ko ni dara ki ijọba apapọ fi ọwọ ara rẹ da wahala ti ko ni lee pari silẹ. Fani Kayọde ṣalaye pe, o daju pe awọn eekan ọmọ Yoruba kan to woye pe, okiki ati ọla ti Sunday Igboho n ni lojoojumọ, ti fẹ bori tiwọn, lo wa nidi ọrọ yii. O ni awọn ọmọ Yoruba naa, ti wọn ri pe irawọ Igboho ti fẹ bo irawọ tiwọn mọle ni wọn n ko si ijọba aarẹ Buhari ninu pe ko fi panpẹ ofin gbe Sunday Igboho. ""...fifi papnpẹ ofin gbe Igboho ko lee ran awọn eeyan wọnyi lọwọ ninu ilepa oṣelu wọn. Yoo kan tun tubọ jẹ ko ṣoro fun wọn lati mu erongba oṣelu ti wọn ni ṣẹ ni."" O fi kun pe ni ilẹ to mọ loni yii, oun ko lero pe Sunday Igboho tii ṣe ohunkohun to tapa si ofin orilẹede Naijiria. Ohun kan to ṣe naa ko ju wi pe o duro fun erongba ati ilepa awọn ọmọ Yoruba to le ni aadọrin miliọnu. O ni Igboho ni ọpọ ọmọ Kaarọ oojire n wo gẹgẹ bii akinkanju ilẹ Yoruba, lẹyin Oduduwa to tẹ ilẹ naa gan do. Oloye Fẹmi Fani Kayọde wa ke si ijọba aarẹ Buhari pe, dipo wiwa ọna ati mu Igboho tabi ṣeku paa, o yẹ ki wọn wa ọna ati joko baa jiroro lori ohun to n ja fun ni. O ni erongba rẹ naa ko si sẹyin didẹkun gulegule awọn ọdaran darandaran Fulani to n da hilahilo silẹ lẹkun ilẹ Yoruba. ""Maa sọ ọ lẹẹkan yii pe, ohun kan to fẹ ti igi bọ oju alaafia ati iduro ṣinṣin orilẹede Naijiria loni yii ni bi awọn eeyan kan Ni ijọba Buhari ṣe n gbero lati pa, tabi fi panpaẹ ofin mu ọrẹ mi ati eeyan mi, Oloye Sunday Adeyẹmo, ti ọpọ mọ si Sunday Igboho.""",0,yoruba "ni ìlú tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba ìwájú. Bàbá lo ni ẹ̀ká àwẹ eyti o gbe lori iwa rere.,0,yoruba Ọba mú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "'Láti ojú orun, ohùn kan máa ń tọ́ka ewé àti ègbòogi sí mi, báyìí la ṣe ń ṣe agbo fún ǹkan ọmọ ọkùnrin'",0,yoruba ilera ṣẹlẹ ni Lagos ti gbogbo eniyan sọ o ṣe pataki. (2002),0,yoruba ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.,0,yoruba "BBC ṣe ìwádìí lóri àbajade ìwádìí ti àjọ yiìí ṣe, láti le mọ àwọn ìgbéléwọ̀n ti wọn lò láti yọri si ohun ti wọn gbé jáde. Igbakeji adari àjọ SERAP, Ọgbẹni Oluwadare, tó ba BBC yoruba sọ̀rọ̀ sàlàyé pé, àjọ náà ṣe ètò ìwádìí naa ní ẹkun mẹfẹfà to gbé orilẹ̀-èdè Nàìjíríà ro láàrin àwọn eeyan ti ọjọ ori wọn jẹ méjìdínlogun sóke ní ìpínlẹ̀ mẹ́fà àti olulu orilẹ̀-èdè Naijiria ti ṣe Abuja. Ipele ti ìwà jẹgudujẹra dé ni Naijiria O ní nínú ìwádii òhun ní àwọn ti beerè ìwoye àwọn ara ilú lóri àwọn kókó tí o fi han bóya ìwa jégudu jẹra ń lọ silẹ̀ tàbí ò ń lọ sókè sí. Awọn ẹka ti wọn fi ṣe gbèdége ayẹwo ni ẹka ọlọpàá, ẹka ètò iná ọba, èto idajọ àti ètò ẹkọ́ Kidnapped Girl: Iyá Ikimot ní lẹ́yìn ọ̀pọ̀ ìdààmú àti owó láti wá ọmọ náà, òun sọ ìrètí nù SERAP: Ìwàdìí ní ẹ̀ka iṣẹ́ ọlọ́pàá àti ìdájọ́ ló kúndùń ìwà àjẹbánu jùlọ Ibèèrè náà gẹ́gẹ́ bi ó ṣe sọ ni pé, Ẹ̀ka wó ni àwọn ènìyàn léro pé wọn le gbà rìbá ni ọwọ wọn? Iyé ènìyàn to sọ pe ""ọlọpàá"" jẹ ìdá mẹ́tà lé lọgọta nínú ida ọgọrun tí ìbèrè míràn tún sọ pé, ẹka wo ni àwọn ènìyàn ti san rìbá jùlọ? Ọlọpàá náà lo tun jẹyọ, tí o si tó ìdá mẹ́rìnlelọgọrin nínú ìdá ọgọrún. Oluwadare fí kún pé ẹka eto ìdajọ náà tún jẹ ohun to yani lẹnu bí wọn ṣe ri pé ìdá ti ohun náà ko kìí ṣe kèrèmí rárá. Igbésẹ̀ ti SERAP ń gbe láti ṣe àdínku ba ìwá jegudujẹra SERAP ni ẹ̀ka ìdájọ ló gbégba oróke sìkeji",0,yoruba "joko, Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé.",0,yoruba "RT @user: Abi oo. T'oba pe taa rira,eku ati lan k'ira """"""""""""""""@user: Ẹ kú àti ẹ̀yin èèyàn mi. Ṣé gbogbo ẹ̀ ń lọ déédé? ó tó'jọ́ mẹ́t…",0,yoruba Bẹ́ẹ̀ là ń lo epo fún ẹ̀rọ̀; à ń fi si orí eéwo kí ó ba tú. #Epopupa #Yoruba #Remedy #boil,0,yoruba Tẹ bọ́tìnì yìí láti rọ́ọ̀nù ìṣàmúlò-ètò tí a yàn tàbí àṣẹ inúààyè wúnrẹ̀n àmúwọlé àṣẹ.,0,yoruba Iṣẹlẹ yii waye nigba ti ogiri wo pa wọn nile ijọsin ti wọn ti n kopa ninu ijọsin ọjọ ọjọbọ mimọ rere lasiko ọdun ajinde. Awọn oṣiṣẹ pajawiri ni eeyan mọkandilogun miiran lo farapa ti awọn si ti gbe wọn lọ si ile iwosan. Awọn alaṣẹ lagbegbe KwaZulu Natal fi idi ọrọ yii mulẹ ti wọn si ni ojo arọda lagbegbe Empageni lo jọ bi ẹ ni ṣe okunfa bi ogiri ile ijọsin ijọ igbalode naa ti ṣe wo lulẹ. Agbẹnusọ ile iṣẹ ọlọpaa KwaZulu Natal Thembeka Mbele sọ pe atẹgun ojo lile fẹ ni agbegbe naa lalẹ ọjọbọ. Iroyin lati agbegbe naa so pe awọn eeyan kan n sun lọwọ nigba ti ogiri naa ya lu wọn. Awọn olori ijọ ti ba awọn eeyan agbegbe naa kẹdun iṣẹlẹ laabi ọhun.,0,yoruba "Awọn ọmọ Naijiria lo n fajuro lori ọpọ aifararọ eto aabo lawọn agbegbe kan Ile ni o kuna lati koju ipenija eto aabo to n waye ni Naijiria, paapa julọ, iwa isekupani awọn darandaran Fulani nipinlẹ Benue ati aifararọ eto aabo nipinlẹ Kano. Awọn asofin naa fohun sọkan bẹẹ lẹyin ijiroro wọn lori aba meji, eyi to nii se pẹlu iwa isekupani awọn darandaran nipinlẹ Benue ati idi to fi yẹ lati pinwọ iwa janduku lagbo oselu nipinlẹ Kano ati lorilẹede Nigeria lapapọ. ""A n fẹ ki aarẹ Buhari tete yọ ọga agba ọlọpa bii ẹni yọ jiga, ko si paarọ rẹ pẹlu ọga ọlọpa to kunju iwọn."" Bakanaa ni ile tun kesi Idris lati tọrọ aforijin lọwọ Gomina Ortom Nigba to n kadi ijiroro naa nilẹ, olori ile, Ọgbẹni Yakubu Dogara ni ""taa ba fi fọwọsi atunse awọn aba mejeeji yi, itumọ rẹ ni pe gbogbo awọn asoju-sofin n panupọ kede pe awọn ko nigbẹkẹle ninu ọga agba ọlọpa lorilẹede yi."" Bakanaa ni ile tun pasẹ fun ọga agba ọlọpa pe ko tọrọ aforijin lọwọ gomina ipinlẹ Benue, Ọgbẹni Samuel Ortom lori bi agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpa orilẹede yi, Jimoh Yusuff ti sapejuwe gomina Ortom bii ẹni to n ri lagbo oselu.",0,yoruba nípa àìkú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìṣẹ̀: ti o ní wúlò.,0,yoruba gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ẹkọ́: ti o nuni ti o nuni ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo.,0,yoruba lo ni àṣà yorubá eyti o gbe lori àìmọ́ kọ.,0,yoruba "Yoruba ni ọmọ ti yoo ba jẹ Aṣamu, kekere ni yoo ti maa jẹ ẹnu ṣamu-ṣamu. Ọmọ ọdun mẹtadinlogun ni ọdọbinrin Zulfah Abdulazzes to si n lo iboju tawọn ẹlẹsin musulumi tawọn mọ si Hijab. Amọ eyi mu ki Zulfah da yatọ lori papa gẹgẹ niwọn igba to jẹ pe isẹ bọọlu gbigba fawọn obinrin lo yan laayo. Lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, ọmọdebinrin naa ni ọmọ ọdun kan ati aabọ ni oun ti n gbe lọdọ iya oun agba, ki onitọun to jade laye lọdun 2017. Akẹkọọbinrin agbabọọlu naa ni igbe aye le diẹ fun oun amọ afojusun oun ni pe lọjọ iwaju, ki oun di obinrin agbabọọlu to pegede julọ bii Azzezat Oshoala. Amọ ti ko ba si lori papa lati gba bọọlu, obi, orogbo ati suti ni Zulfah maa n ta labẹ afara Ojota, ko le ri ọwọ mu lọ si ẹnu. O wa salaye ọpọ ipenija to n koju lati awọn akẹẹgbẹ rẹ gẹgẹ bi agbabọọlu obinrin to n lo Hijab.",0,yoruba loni ojo ogbon osu kini odun atunji sayo eba mi patewo fun kabiesi oba mi edumare aà jí bí gbogbo,0,yoruba èèyàn ò ṣe kúkú mu àgbo,0,yoruba "Ohun ti a gbọ ni pe Kembi, ọmọ ogun ọdun ṣabẹwo si ọrẹkunrin rẹ ni Ikorodu eyi to sọ pe miliọnu meji owo naira loun gba lati fi ọmọdebinrin naa joogun. Kembi to n gbe pẹlu awọn obi rẹ lagbegbe Tabon Tabon l'Agege pade iku ojiji lọjọ kejilọgbọn oṣu keje ọdun 2020 yii nigba to lọ sun nile Yusuf. Yusuf ẹni ọdun mẹtalelọgbọn ni iroyin sọ pe o pa Kembi ti o si ge wẹlẹwẹlẹ lati fi ṣe oogun owo. Ẹbi ọmọdebinrin ọhun sọ fun awọn akọroyin pe ileeṣe ọlọpaa ẹkun Elere l'Agege ko ti gbe oku akẹkọọ naa fawọn. Lẹyin ọsẹ mẹta ti Yusuf ṣiṣẹ laabi yii tan lọwọ awọn agbofinro too tẹẹ lẹyin to ti sa lọ siluu Ilorin nipinlẹ Kwara. Àṣìṣe ọlọ́pàá àti Adájọ́ sọ mí di ẹni tí wọ́n dájọ́ ikú fún, ọpẹ́lọpẹ́ Fayoṣe tí ko buwọlu Afurasi ọhun ni a gbọ pe o jẹwọ fawọn ọlọpaa wi pe oun gbimọ pọ pẹlu awọn mẹta mii ninu eyi ti babalawo kan ti wọn n pe ni Owonikoko wa. O ni babalawo ọhun gan an lo ni ki oun fi ọmọ oodo lu akẹkọọ naa pa to ba ti ṣabẹwo si i. Kembi to ṣẹṣẹ kẹkọọ gboye ''ND'' nile ẹkọ giga gbogbonṣe n mura lati lọ fun ẹkọṣẹ ohun to lọ ṣe nile ẹkọ giga fun ọdun kan ki o tun ṣagbako iku ojiji. Oluwatoyin Kembi to jẹ baba akẹkọọ naa sọ fawọn akọroyin pe awọn tiẹ ro pe ọmọ naa ti sọnu ni nigba ti ko pada wale lọjọ naa lai mọ pe awọn oniṣẹ ibi ti gee wẹlẹ wẹlẹ. Yusuf sọ pe babalawo nikan lo mọ ibi ti oku Kembi wa. Ẹwẹ, agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko, Muyiwa Adejobi ti ṣalaye pe iwadii si n lọ lọwọ lati mu awọn mẹta yoku ti gbimọ pọ pẹlu Yusuf lati pa Kembi. Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá",0,yoruba "Akọwe agba ati alukoro ẹgbẹ oṣelu PDP, Kola Ologbondiyan to ba BBC Yoruba sọrọ ṣalaye pe aimọ eyi to kan lo jẹ ki ijọba gbe igbesẹ naa. Ọgbẹni Ologbindiyan sọ pe kii ṣe asiko ti ijọba ṣe afikun owo ina ati owo epo bẹntiro yii lo yẹ ki ijọba tun maa na ẹgbẹlẹgbe biliọnu owo dọla sori ojuurin reluwee lati Kano si orilẹede Niger. ''Nisinyii ti ijọba n ṣe oju ọna reluwee lọ si Niger lati ran wọn lọwọ, iranlọwọ wo lawọn ọmọ Naijiria gan an tii riu lati ọdọ ijọba yii,'' Ologbondiyan lo sọ bẹẹ. Ologbondiyan ni ọgbọn ati ko owo jẹ naa ni gbogbo ohun ti ijọba apapọ n ṣe pẹlu ṣiṣe ojuurin lọ si ilẹ Niger. Akọwe agba ati alukoro ẹgbẹ oṣelu PDP ni kii ṣe nitori araalu ni wọn fi n ṣe ohun ti wọn n ṣe lori reluwee lọ si Niger. Ologbondiyan ni ẹgbẹ PDP ko tako ojuurin ti ijọba yii ṣe lati Eko si Ibadan nitori awọn mọ pe anfaani lo wa nibẹ fun araalu. O ni nkan to ba yẹ ki ijọba Buhari fi si iwaju lo n fi sẹyin. O ṣalaye pe ọkọ ojuurin ti ilu Eko si Ibadan ti ijọba Muhammadu Buhari fẹ ṣi gan an, ẹgbẹ PDP naa lo bẹrẹ rẹ. Nibi ipade igbimọ alasẹ ijọba apapọ ti Aarẹ Muhammadu Buhari dari l'Ọjọru ni wọn ti fi ontẹ lu owo naa. SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike Minisita fun eto irinna, Rotimi Amaechi, gẹgẹ bi iwe iroyin The Punch ṣe jabọ, sọ fún awọn akọroyin pe ijọba buwọlu owo naa fun idagbasoke oju ọna ọkọ reluwe ti yoo so bẹrẹ lati ipinlẹ Kano-Dutse-Katsina-Jibia, titi de Maradi lorilẹ-ede Niger Republic. Oju ọna irin naa, tó jẹ kilomita 248 ni ireti wa pe yoo sisẹ fun gbigbe eporọbi. Yatọ si eyi, Amaechi tun sọ pe igbimọ naa tun buwọlu isẹ agba ṣe ti owo rẹ le ni biliọnu mẹta Naira ₦3.049bn, fun ṣíṣe, ayẹwo ati ikojade ẹ̀rọ ti yoo ma a gbe reluwe to ba ni ijamba kuro loju ọna. Ẹwẹ, laarin oṣu kẹsan ọdun 2020 yii ni ileeṣẹ ọkọ ojuurin sọ tẹlẹ pe ọkọ reluwe yoo bẹrẹ si ni ṣiṣẹ lati ilu Eko si Ibadan. Oludari ileeṣẹ reluwee lorilẹede Naijiria, Fidet Okhiria lo sọrọ naa niluu Ibadan nigba ti minisita eto irinna, Rotimi Amaechi n ṣe abẹwo ibi ti iṣẹ de lori ojuurin reluwee lati Eko si Ibadan ninu oṣu kẹjọ. Okhiria sọ pe ibudokọ reluwee to wa ni Yaba ni irinna naa yoo ti gberasọ niluu Eko si Ibadan. Ọgbẹni Okhiria ṣalaye pe awọn ọkọ reluwee naa yoo maa na Eko si Ibadan ni igba mẹrindinlogun lojoojumọ.",0,yoruba wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìwà: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ìyá lo tun se lọ.,0,yoruba fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Alàji lo lọ.,0,yoruba "Oluwo wa ṣapejuwe Alaafin gẹgẹ bi baba fun gbogbo ọba nilẹ Yoruba. O ni ẹni ti eeyan n fi igbe aye rẹ tọrọ ni Alaafin, to si jẹ ẹni ti eeyan gbọdọ kọ ọgbọn lọdọ rẹ. ""Ti gbogbo ọba ba le ṣe, alaafin jẹ ẹni to yẹ ki wọn o ma a lọ si ọdọ rẹ lojoojumọ, lati ma a gbọ itan nipa ilẹ Yoruba. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ""Mo nifẹ baba laiṣẹtan, gẹgẹ bi ọmọ."" O wa gbadura pe ki Alaafin tubọ pẹ laye ninu ilera to peye. Bakan naa ni Minisita fun idagbasoke awọn ọdọ ati ere idaraya ni Naijiria, Sunday Dare ti ki Alaafin ku oriire aadọta ọdun lori itẹ. Ninu ọrọ ikini to fi sita, Ọgbẹni Dare ṣapejuwe Ọba Adeyẹmi gẹgẹ bi ẹni to n mu iṣọkan wa nilẹ Yoruba, to tun n gbe aṣa larugẹ. O ni kii ṣe idagbasoke, iduroṣinṣin ati ilọsiwaju nikan ni asiko rẹ ti mu wọ ipinlẹ Ọyọ, amọ o tun mu ki iṣọkan, ifẹ ati ireti jọba ni ipinlẹ naa ati Naijiria lapapọ. Wo ọ̀pọ̀ àṣeyọrí tí Aláàfin ṣe láti àádọ́ta ọdún tó ti jọba Yoruba ni ariṣe larika, arika si ni baba iregun. O pe aadọta ọdun ti Ọba Lamidi Adeyẹmi kẹta ti di Alaafin ilu Ọyọ, ko si ṣe e ṣe lati ṣami ajọdun naa lai tọka si diẹ lara awọn nnkan aritọkasi to gbe ṣe. Ta ba ni ka maa ka ni eni, eji, ilẹ kun nidi ọpọ aseyọri ti Alaafin ti gbe se ori oye, amọ diẹ lara awọn aseyọri naa ree, se bi ọmọ ko ba ba itan, yoo ba arọba. Idasilẹ ipinlẹ Oyo tuntun: Lasiko ti ipe jade lati da ipinlẹ Ọyọ silẹ lọdun 1975, ipa kekere kọ ni Alaafin ko, pẹlu ajọṣepọ awọn eeyan mii, to mu ki idasilẹ ipinlẹ Ọyọ, Ogun ati Ondo dohun. Ipa to si ko ninu idagbasoke Naijiria lo mu ki Aarẹ ologun, Murtala Muhammed yan oun nikan gẹgẹ bi ọba lati ilẹ Yoruba, lati kọwọrin pẹlu rẹ lọ si ilu Mecca fun Hajj. Yatọ si eyi, ijọba tun fun ni ami ẹyẹ apapọ, CFR, lọdun 1975. Baba isalẹ fasiti to lo saa mẹta: Lọdun 1980, ijọba apapọ yan Ọba Adeyemi Kẹta gẹgẹ bi Baba isalẹ akọkọ fun Fasiti ilu Sokoto, to ti di Uthman Dan Fodio University bayii, fun ọdun mẹrin. Lẹyin to pari saa akọkọ naa, igbimọ alaṣẹ fasiti naa tun fi orukọ rẹ silẹ fun saa keji. Ijọba naa si fi aṣẹ si i. Ko tan sibẹ o, wọn tun damọran saa kẹta fun, ti ijọba si tun fi ontẹ lu u bakan naa. O jẹ apapọ ọdun mejila ti alaafin lo gẹgẹ bi Baba'salẹ fasiti naa. Iru eyi ko ti i ṣẹlẹ ri ninu iyansipo Baba'salẹ ni Fasiti kankan ni Naijiria. O yan Aarẹ Ọna Kakanfo meji sipo Ọba Adeyẹmi lo yan oloogbe, Oloye MKO Abiola gẹgẹ bi Aarẹ Ọna Kakanfo ilẹ Yoruba l'oṣu Kinni, ọdun 1988. Oun naa lo tun yan ẹlomii, Iba Gani Adams, lati rọpo Abiola lọdun 2017. O ṣe idasilẹ ilana irinajo Hajj ti Naijiria n lo Lọdun 1990, ijọba apapọ labẹ iṣakoso Ọgagun Ibrahim Babangida yan Ọba Adeyẹmi Olayiwola gẹgẹ bi Amiru Hajj, lati dari awọn musulumi ni gbogbo ipinlẹ mọkanlelogun to wa ni Naijiria nigba naa, fun irinajo Hajj. Abajade aṣeyọri Hajj ọdun naa si lo duro gẹgẹ bi osuwọn ti wọn fi n wo aṣeyọri irinajo Hajj ni Naijiria titi di oni. O sagbatẹru bi awọn ọba kan nilẹ Yoruba ṣe di ọba alade Ṣaaju akitiyan Alaafin Adeyẹmi, awọn ọba kan nilẹ Yoruba kii de ade ilẹkẹ. Amọ pẹlu akitiyan rẹ, awọn kan lara wọn di ọba to n de ade ilẹkẹ, ti wọn si gba igbega lori igbelewọn awọn ọba nipinlẹ Ọyọ, ati ni awọn ipinlẹ bi Ọṣun ati Ondo. Lara wọn ni: Onjo ti Okeho, Onitede ti Tede, Asẹyin ti Iṣẹyin, Timi ilu Ẹdẹ nigba kan, Ọba Oyelusi Tijani Agbaran II Lọdun 1980 si 1981, Ọba ilu Kisi, Okere ilu Saki, ati Sabi ti Iganna gba igbega. Baalẹ Ile-Ogbo di ọba, Olu ti Ile-Ogbo lọdun 1995, Olubu ti Ilobu nigba naa gba ade lọdun 1986. Ọba Olutayọ: ìgbésẹ̀ Ọọni àti Alaafin ti ń mú ìṣọ̀kàn dé sáàrin àwọn Ọba Yorùbá Alayegun ilu Ọdẹ-Omu, Akire ilu Ikire, Akirun ti Ikirun, Aree ti Ire, Olunisha ti Inisha (gbogbo wọn wa nipinlẹ Ọṣun) gba ade nipasẹ Alaafin. Nipinlẹ Ogun, Ọba ilu Ipokia di ọba alade ilẹkẹ. Koda, Alaafin adeyẹmi lo gbe ade le gbogbo wọn lori nilu ẹnikọọkan wọn O ma n bu ẹnu ẹtẹ lu ijọba ti ko se daadaa Ọjọ ti pẹ ti Alaafin Adeyẹmi ti n kọ lẹta lati bu ẹnu ẹtẹ lu awọn igbesẹ ijọba ti ko dara, koda ko to o jẹ ọba. Ni nkan bi ọdun 1960, yatọ si awọn ọrọ to ma n kọ nipa ara rẹ sinu iwe iroyin, o kọ lẹta lati bu ẹnu ẹtẹ lu bi ijọba ṣe n ṣe awọn olukọ, lẹyin to ri ọkan lara awọn olukọ to kọ nileewe, to wọ akisa aṣọ. O tun kọ lẹta mii to pe ni Ominira awọn obinrin: Nkan ti ko wọpọ nilẹ Yoruba. Ọpọlọpọ igba lo si ti kọ lẹta si awọn olori ijọba bi gomina ipinlẹ Ekiti, Kayọde Fayẹmi, lasiko ti Fayẹmi ba awọn mẹrindinlogun wi nipinlẹ rẹ, fun pe wọn ko fọwọsowọpọ pẹlu ijọba. Lẹta ibawi ati ikilọ lori aṣa ati iṣe ilẹ Yoruba ni lẹta naa. Bakan naa lo ti kọ lẹta si Aarẹ Muhammadu Buhari lori eto aabo nilẹ Yoruba, ninu eyi to ti sọ fun aarẹ pe ko fi opin si bi awọn kan ṣe n kọlu ilẹ Yoruba.",0,yoruba "Àwọn kan ò sanwó (bí ìyá Fẹlá), wọ́n bára wọn látimọ́lé, síbẹ̀ wọn ò bojú wẹ̀hìn fífẹ̀hónú wọn hàn síjọba. #IseleAtijo #Yoruba #Kirikiri",0,yoruba ẹ̀ẹ̀mẹ́ta là á pajé ajé ajé ajé gbére tèmi kò mí ajé olókùn yóò bá wa rẹ́ láṣẹ,0,yoruba "Ẹgbẹlẹgbẹ awọn eeyan kaakiri agbaye ni yoo wo igbeyawo naa Ọkẹ aimoye awọn eeyan lo da orun mọju lawọn opopona ilu Windsor lọna ati lee duro si ọgangan ibi ti iran yoo ti dun un wo lasiko ti igbeyawo naa baa n waye lọjọ abamẹta. Ọsan gangan ni igbeyawo naa yoo waye ni ileejọsin St George's Chapel Ọsan gangan ni igbeyawo naa yoo waye ni ileejọsin St George's Chapel to wa ni Windsor ki wọn to gunle irinajo ẹyẹ lori kẹkẹ ẹ'sin kaakiri ilu naa ni nkan bii aago kan ssan. Ọmọọba Charles to jẹ baba ọkọ iyawo, Harry ni yoo tẹwọ gba iyawo lọ siwaju awọn alufaa lẹyin ti baba iyawo, arakunrin Thomas Markle ko lee farahan nibi igbeyawo naa nitori ailera rẹ. Ọmọọba Harry àti omidan Sparkle yóò ṣe ìgbéyàwó Ni oojọ, igbeyawo ku ọla, Ọmọọba Harry sọ f'awọn ero to peju si Windsor pe ko si ifoya fun oun lori igbeyawo naa, bakanna si ni omidan Markle pẹlu ni ṣẹṣẹ ni inu oun n dun. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:",0,yoruba "Ẹgbẹ agbaboolu obinrin Naijiria, Super Falcons yoo wako pẹlu ikọ Atlas Lionesses ti orlẹede Morocco. Loni, ọjọ Aje, ọjọ kejidinlogun, oṣu Keje, ọdun 2022, ni ifigagbaga naa yoo waye fun ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ to kangun si asekagba idije WAFCON 2022. Papa ìṣeré Prince Moulay Abdellah ni ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ naa yoo tì waye laago mẹsan-an alẹ n'ilu Rabat. Iko Super Falcons lo gbọdọ bori ifẹsẹwọnsẹ yii lati wọ ipele aṣekagba idije naa. Lionesses of Atlas ile Morocco ni o bori ninu gbogbo ifẹsẹwọnsẹ ti wọn ti kopa ninu idije naa, ti iko Super Falcons si padanu ẹyọ kan ninu ifẹsẹwọnsẹ wọn ti wọn gba pẹlu iko Bayana Bayana ti ile South Africa. Ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ yii ni yoo gbe ẹgbẹ́ agbabọọlu Super Falcons de ipele aṣekagba idije naa, ti wọn ba fi borí Morocco. Bakan naa ni yoo jẹ fun Morocco, to ba jẹ pe awọn lo bori. Ki wọn o to koju ẹlòmíì ni aṣekagba idije. Orile-ede Naijiria n ja lati gba ife idije bọọlu àwọn obìnrin ni Africa, WAFCON, fun igba kẹwaa, ninu ìgbà mejila to ti waye. Morocco n jà lati gba a fun igba akọkọ. Botilẹ jẹ pe Super Falcons ni ọpọ n fi ojú si lara gẹgẹ bi akọni, ẹgbẹ́ agbabọọlu Atlas Lionesses naa kò ṣe e fi ọwọ rọ́ sẹyin. Idi ni pe lati igba ti idije WAFCON 2022 ti bẹ̀rẹ̀, ni wọn ti n fakọyọ. Wọn ò si tíì padanu ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ kankan. Yatọ si eyi, Morocco lo gbalejo idije naa, wọn o si ni fẹ ki ife ẹyẹ bọ wọn lọwọ. Nitori naa ẹgbẹ́ agbabọọlu Super Falcons nilo lati fi ọkàn si nkan ti wọn n ṣe lori papa lati ìbẹ̀rẹ̀ ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ naa. Iye igba ti Morocco ati Super Falcons ti pade lori papa Ọdun 1998 ni ẹgbẹ́ agbabọọlu mejeeji kọkọ pade ni WAFCON 1998. Iya kekere kọ ni Super Falcons fi jẹ Atlas Lionesses ni ilẹ baba wọn. Ami ayo mẹjọ si odo ni wọn fun wọn. Ọdun 2000 ni wọn tun pade ni WAFCON 2022 to waye ni South Africa. Ami ayo mẹfa si odo ni Naijiria tun fi lù wọ́n ni aludojubolẹ. Sugbọn laarin ìgbà naa si asiko yii, ẹgbẹ́ agbabọọlu Morocco fihan pe nkan ti yatọ, paapaa lati igba ti WAFCON 2022 ti bẹ̀rẹ̀. Nigba ti o gba ni yanju, Aarẹ, ajọ to risi kokari ere bọọlu nile wa, NFF, Amaju Pinnick ni gbogbo nkan ni iko Super Falcons ni lati ṣe lati gba ifẹyẹ ijide naa gba kẹwa. Amaju ni oun kọkọ ki awọn agba bọọlu naa fun bi wọn ṣe fakọyọ ninu awọn ifẹsẹwọnsẹ ti ko pa ninu, ti wọn si bori awon akẹẹgbẹ wọn. “Mo kọkọ ki awọn agbabọọlu naa fun bi wọn fakọyọ ninu ifẹsẹọnsẹ pẹlu awọn akẹẹgbẹ wọn.” “Wọn ti fi ran wa pe orilẹede Naijiria ni oga ti a ba sọrọ ere bọọlu obinrin ni ile adulawọ, bi wọn ṣe fakọyọ ninu awọn ifesewọn wọn,” “Ifẹsẹweọnsẹ pẹlu ikọ Morocco ko le yipada sugbọn yoo lagbara pupọ gan nitori ikọ Morocco naa jẹ ẹgbẹ agbabọọlu ti muṣemuṣe wọn da muṣe.” “Mo ni igbagbọ pe a bori wọn, mo ti sọ fun awọn agbabọọlu naa lati ranti ibi ti wọn wa, ki wọn si fi ọkan gbe orilẹede Naijiria larug\]e nibi ijide WAFCON.” “Ninu mi dun si awọn agbabọọlu pupọ.” Aarẹ, ajọ to risi kokari ere bọọlu nile wa, NFF, Amaju Pinnick ni oun ni igbagbọ ninu iko Super Falcons lati bori orilẹede Morocco to ba di ago mẹsan oni ni papa iṣerẹ Prince Moulay Abdellah Stadium, Rabat lorilẹede Morocco. Amaju ni awọn agbabọọlu Naijiria ti sẹtan lati jẹ orilẹede Naijiria bọ si oke nibi ti o ko wa. O ni o ti ṣeṣe fun Ikọ agbabọọlu Super Facons lati kopa ninu ifẹsẹwọmsẹ aṣe kagba to ba di ọjọ aiku ọse to bo yi Bi ẹgbẹ́ agbabọọlu Super Falcons ti Naijiria ṣe n gbaradi lati koju Swallow ti Burundi lonii, ẹ jẹ ka ṣe agbeyẹwo ipa ti ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ naa ni. Ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ naa ni eyi to kẹhin ni abala akọkọ fun awọn orile-ede to the wa ni ipin C ninu idije WAFCON 2022 to n lọ lọwọ ni Morocco. Ẹgbẹ agbabọọlu to ṣe ipo kinni, ikeji, ati ikẹta ni ipin C, yoo bọ si ipele quarter finals. Ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ pẹlu Burundi si ni yoo sọ ibi ti ori n gbe Super Falcons lọ, ti Burundi ba fi lu wọn. South Africa ati Botswana lo na Burundi. Ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ti ọjọ́ Aiku, ti yoo waye ni papa ìṣeré Prince Moulay El Hassan, Rabat, ni igba àkọ́kọ́ ti orile-ede mejeeji koju ara wọn nilẹ okeere. Orile-ede Burundi ti padanu ninu ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ wọn meji akọkọ, Naijiria padanu ẹyọkan sọwọ South Africa. Ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ laarin orile-ede mejeeji la le fi we ija laarin Dafidi ati Golayaati. Igba àkọ́kọ́ re e ti Burundi n kopa ni idije WAFCON, àmọ́ Naijiria ti kopa ninu mọkanla, o si ti gba ife ni igba mẹsan-an. Ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ mẹta ni orile-ede kọọkan to n kopa ni idije bọọlu àwọn obìnrin ni Africa to n lọ lọwọ ni Morocco, WAFCON 2022, gbá ni abala akọkọ. Ninu meji to ti kọkọ gbá, Naijiria padanu ẹyọkan sọwọ South Africa, o bori ikeji nigba to na Botswana ni ami ayo méjìlá si odo. Lọwọlọwọ, Naijiria lo wa ni ipo keji ni ipin kẹta (C), pẹlu ami mẹta. Orile-ede Burundi lo wa ni ipo to kẹhin, ko ni ami kankan lẹyin ti South Africa ati Botswana lu u. Botilẹ jẹ pe ami mẹta ni Naijiria àti Botswana ni lori tabili igbelewọn, wọn fi Naijiria si ipo kejì, nitori 'iru' goolu ti wọn gbá wọ awọn. Sugbọn o, dandan ni fun wọn lati bori Burundi, ki wọn o le bọ si ipele quarter final. Olukọni ẹgbẹ́ agbabọọlu obìnrin Naijiria, Randy Waldrum, sọ fun awọn akọroyin n'ilu Rabat, lọjọ Abamẹta pe, àwọn ko le foju kere Burundi. O ni ""ao le foju di ẹgbẹ́ agbabọọlu Burundi."" A n gbaradi lati tun ṣe daadaa ju bi a ṣe ṣe lọ ní ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ wa to kọja. Erongba wa si ni lati wọ ipele quarter finals lọjọ Aiku.""",0,yoruba a ó gbo ewé ifin sínú igbá a ó fi ẹfun sí í obìnrin olóyún á máa mu ún ń wákàtí wákàtí,0,yoruba "tí Ìyá fè lọ, Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.",0,yoruba "Ohun tí àwọn èèyàn ò mọ̀ ni wípé àṣàa kí a máa se oúnjẹ nílé bá oúnjẹ àṣaralóore tan. Ìyẹn ni wípé, àwọn tó máa ń se oúnjẹ nílé, máa ń jẹ oúnjẹ àṣaralóore àti lọ́nà kejì, ìjẹkújẹ oúnjẹ á dínkù,...",0,yoruba Ìbéèrè Fún Amúgbálẹ̀gbẹ́ Àká-ẹ̀gbẹ́,0,yoruba àmọ́ nkan ń bẹ o gbogbo òórùn ẹran sísun tí mo ń gbọ́ yìí tèmi dà àbí ẹ fẹ́ dá a jẹ tán ni,0,yoruba "Olùwo lọ. Nitori eyi, ara eni lo je gbogbo ise ibile tèmi.",0,yoruba "Kò pẹ́ tí a gbé orin George jáde , Montano fèsì pẹ̀lú orin tí a pe àkọlée rẹ̀ ní “ Dr .",0,yoruba "RT @user: Aase o. Ohun Orun ti gbaa. """"""""""""""""@user: Ẹ káàárọ̀ o. Ṣé dáadáa la jí? Ọjọ́ Ìṣẹ́gun rèé. Ìṣẹ́gun rẹ ń dúró dè ọ. #eka ...",0,yoruba "Awa PDP a kò lẹ́bọ lẹ́ru rara, ipinnu Amerika yii tẹ PDP lọrun Igbesẹ naa ti wọn kede laipẹ yi ko yọ awọn to kopa tabi ti wọn ṣe agbatẹru dida ibo Naijiria ọdun 2019 to kọja ru. Kola Ologbondiyan to jẹ akọwe ipolongo fẹgbẹ oṣelu PDP sọ pe rẹgi ni igbeṣẹ naa ba ẹgbẹ awọn lara mu nitori pe awọn ko lọwọ ninu iwa to kọdi si eto ijọba awarawa. O ni awọn to lagbara lati dari eto idibo ati awọn ọmọ ogun bo ti ṣe wu wọn lo le máa foya pe ijiya Amẹrika yi yoo kan awọn. ''Awa o ni ibẹru kankan nipa eto ti ilẹ Amẹrika fẹ ṣe ṣugbọn awọn to fi agidi gba ipo, awọn ti wọn gun awọn eeyan lada ati lọbẹ ni Kanoni ẹru ma ma ba'' O ṣalaye pe igbeṣẹ yi jẹ oun to dun mọ awọn ninu ati pe awọn fẹ ki awọn orile-ede miran naa tẹle apẹrẹ Amerika yi. ''Amẹrika nikan kọ lo yẹ ki wọn gbe igbeṣẹ yi, ni Yuroopu ati ilẹ Gẹẹsi,awọn na ay ki wọn ṣe bẹ'' Ologbondiyan wa fi ifarajin ẹgbẹ oṣelu PDP han lati ma mu idagbasoke ba eto oṣelu ni Naijiria Kini APC sọ? Ninu idibo to kọja ẹgbẹ oṣelu APC lo gbegba oroke ninu idibo gbogboogbo to waye. Gẹgẹ bi PDP awọn naa a ma saaba na ika abuku si gbẹ alatako pe awọn ni wọn wa nidi magomago tabi iwa to le mu ifasẹyin ba eto oṣelu ni Naijiria. Ninu idibo to kọja ẹgbẹ oṣelu APC lo gbegba oroke ninu idibo gbogboogbo to waye. Amọ ṣa nigba ti a kan si akọwe ipolongo ẹgbẹ naa lori ẹrọ alagbeka lori ohun ti ẹgbẹ ri si igbesẹ yi,o ni ohun ko ti le fesi si bayi. Dele Momodu : Lẹ́yìn Buhari àti Atiku, èrò ọjà làwọn olùdíje yóòkù ní ìdìbò 2019 Mallam Lanre Issa Onilu ṣalaye pe atẹjade ṣi ni Amerika gbe jade ati pe wọn ko tii darukọ awọn ti wọn fi ofin de lati ma gba iwe irinna lọ si Amẹrika. O ni bayi ti ko tii si ẹkunrẹrẹ alaye, ohun ko tii le sọrọ nipa ilana tuntun naa. Awọn woo gan an ni ọrọ yi kan? Atẹjade ti Agbẹnusọ fun ileeṣẹ Amerika, Morgan Ortagus fi sita ni Washington lorilẹ-ede Amerika ni lati ọjọ kẹrinlelogun, oṣu kinni ọdun ni Amerika ti n gbiyannju lati gbe igbesẹ yii. O ni paapaa lori awọn oloṣelu ti ko fẹ ilọsiwaju eto oṣelu ni wọn ṣe fẹ gbe e. Ilẹ Amẹrika ko gbe orukọ awọn ti ọrọ naa kan sita tabi ki wọn sọ igba ti wọn yoo fi orukọ naa sita.",0,yoruba kí ìyàtọ̀ ọ̀gẹ̀dẹ̀ àgbagbà ọ̀mìnì àti páráǹtà,0,yoruba "Dokita fi ye eto BBC ''La a han mi'' pé abẹrẹ ajẹsara maa n dena Hepatitis A ati B ṣugbọn ko si eyi to le dena C Bakan naa ni Dokita ṣalaye awọn ọna ti eeyan fi le ko arun jẹdọjẹdọ yii lawujọ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ni afikun, Dokita Afeez ṣalaye ni kikun lori awọn ọna ti eeyan ko fi le ko arun jẹdọjẹdọ yii ati nipa ki a maa ma dẹyẹsi awọn to ti nii. Imọ toto lo le bori arun gbogbo ninu ile, lẹnu ounjẹ, fun itọju ara ati gbigba abẹrẹ ajẹsara lasiko le dena awọn arun kọọkan.",0,yoruba Ìjọba wà níbẹ̀. Sọ̀rọ̀ dídún,0,yoruba Ọlọ́run má jẹ́ a r'ogun ní Nàìjá o! Ogun ò kí nṣe nkan kékéré o!,0,yoruba tí gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ìyá lo tun se lọ.,0,yoruba Àìmọ́ ni ó ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Alàji lo ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba ọ̀yẹ̀kú a ní kí wọn,0,yoruba ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "Irọ́ lẹ pa, àwa kọ la ju àwọn ọmọ Naijiria sínú òṣì - Ẹgbẹ́ àwọn gómìnà",0,yoruba Oro Kabiti. What do you guys think? . . 👉 Yorùbátv ẸGBẸ ỌMỌ OLÚWA BÍ GBOGBO ÀGBÁYÉ Ojú òpó ìkànsíraẹni 🇳🇬🇹🇬🇧🇯🇧🇷🇨🇴🇨🇺🇬🇭🇨🇮______________________________□ Yoruba TV 🥰😘🔥 #yoruba #yorubatv #yorubaweddings #ebi #asoebi… https://t.co/GnzUDdwGZe,0,yoruba "RT @user: Who read this before? """"""""""""""""""""""""""""""""In-depth Yoruba Phonology and Grammar"""""""""""""""""""""""""""""""" 😁 Ìwé pàtàkì fún ẹni tí ó fẹ́ kọ́ gírámà èdè Yorùbá fún sí…",0,yoruba four pictures one word àwòrán mẹ́rin ọ̀rọ̀ kan what is it kíni ọ̀rọ̀ náà,0,yoruba "Agbẹnusọ fún ẹka ìròyìn ilé - isẹ́ ọ̀hún , ọ̀gágun John Enenche sọ pé “ ọkọ̀ ogun òfurufú bẹ̀rẹ̀ sí ní máa ju àdó olóró sí àwọn agbègbè tí adarí ikọ̀ ọlọ́tẹ̀ Boko Haram wà nípasẹ̀ ìròyìn tí àwọn gbọ́ pé agbègbè náà ni ó farapamọ́ sí """""""" .",0,yoruba má sú ìfé ńnú òòrùn èyí ń fa ìgbóná tàbí má súùfé lálẹ́ bí kò bá nídí bí kò bá ṣẹlẹ̀ rí kí wá ló mú wọn sọ bẹ́ẹ̀,0,yoruba @user @user Àwa mà nìyẹn o. Àfi kí Elédùà kówa yọ. Gbàù! lónìí gbòsà! lọ́la yìí fẹ́ pọ̀ díẹ̀.,0,yoruba "Ṣebí abẹ́ ìṣàkóso Àfọ̀njá ni Ìlọrin (Aréwá Ọ̀yọ́) wà nígbàa ni, èyí ò tó o, ó fẹ́ gun orí àpèré ń tipátipá. #ItanFulani #Darandaran",0,yoruba ẹ̀ká ojú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba nípa ài: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọba lo ni iwa rere.,0,yoruba otito oro ni se daadaa le wa bee sini awo pele ki ya,0,yoruba "Nitori naa, ni a ṣe ṣe akojọpọ diẹ lara awọn iṣẹlẹ ti ẹ le fojusọna fun l'ọdun 2020. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Bẹrẹ lati agbo oṣelu, sagbo faaji, Naijiria si Cameroon, Ghana, ati gbogbo agbaye. Eyi ni diẹ lara awọn nkan ti ẹ le fojusọna fun l'ọdun 2020. Eto idibo 2020 John Mahama ati Nana Akufo Addo n fi oju pa ara wọn rẹ Eto idibo Ghana: Ọdun yii jẹ ọdun ibo didi, a o si bẹrẹ pẹlu orilẹede Ghana nibi ti wọn yoo ti ṣe eto idibo aarẹ wọn l'ọdun yii. Aarẹ Nana Akufo-Addo n dije fun ipo naa fun igba keji, ṣugbọn o ni iṣẹ pupọ lati ṣe lati mu ki awọn eniyan o wo ọdọ̀ rẹ, bakan naa ni yoo maa fi iga-gbaga pẹlu aarẹ tẹlẹ, John Mahama t'oun naa n ṣẹju si ipo naa. Ibeere to wa n gba ọkan awọn eeyan ni pe, ṣe iṣẹlẹ to waye l'ọdun 2016 yoo tun waye bi lọdun 2020? Eto idibo America: Oriṣiriṣi iṣẹlẹ lo ti ṣẹlẹ ni orilẹede America lati igba ti wọn ti d'ibo yan Donald Trump sipo aarẹ l'ọdun 2016. Lọwọlọwọ, pipa ti wọn pa ọgagun kan lorilẹede Iran, Ọgagun Qasem Soleimani ti olu ileeṣẹ ologun America, Pentagon, sọ pe AArẹ Trump lo paṣẹ fun awọn lati pa, ni iroyin to gbaju-gbaja ju l'agbaye. Ṣugbọn, Donald Trump ti bẹrẹ ipolongo ibo fun eto idibo aarẹ ti yoo waye l'oṣu Kọkanla, ọdun 2020. O ku ki a mọ boya yoo wọle saa keji si 'White House' abi bẹẹ kọ. Opin iyọnipo nilẹ America Yatọ s'eto idibo, ile aṣofin America wa laarin gbungbun igbesẹ lati yọ Aarẹ Trump nipo, nitori ipe kan to pe aarẹ Ukraine. Ti wọn si fi ẹsun kan Trump pe, o ṣi ipo rẹ lo. Ile aṣofin kekere ti yọ ọ nipo, Aarẹ Trump si ni aarẹ kẹta ti orukọ rẹ wọ inu iwe itan awọn aarẹ America ti wọn yọ nipo. Amọ nkan ti ọpọlọpọ n duro o de ni boya ile aṣofin agba yoo fi ontẹ lu iyọnipo rẹ. Eto idibo orilẹede Somalia: Orilẹede Somalia yoo dibo aarẹ miran l'ọdun yii. Ohun to mu ki eto idibo naa o ṣe e tọka si ni pe, igba akọkọ niyii lati aadọta ọdun sẹyin ti awọn ọmọ orilẹede naa yoo l'anfaani lati dibo yan ẹni to wu wọn, dipo bi awọn aṣoju ṣe maa n ba wọn dibo tẹlẹ. Presido Nkuruziza ti wa n'ipo fun ọdun mẹrinla IGBEYAWO TI YOO MI IGBORO TITI NI NAIJIRIA !!! Oya, ẹ maa palẹmọ fun #Assurance2020 Gbaju-gbaja olorin takasufe e, Davido, ti ṣetan lati gbe ololufẹ rẹ, to tun jẹ iya ọkan ninu awọn ọmọ rẹ, Chioma, niyawo l'ọdun yii, lẹyin to fun un ni oruka adehun nilu London l'ọdun 2019. Igbeyawo gbajumọ miran ti ifojusọna tun wa fun ni laarin Khafi Kareem ati Ghedoni Ekpata. Davido fun Chioma l'oruka nilu London lẹyin to kede pe awọn ti ṣe mọmi-n-mọ ọ Idije ere idaraya l'ọdun 2020: African Nations Championship Oṣu Kẹrin ọdun yii bakan naa ni orilẹede Cameroon yoo gbalejo idije ife ẹyẹ awọn akọni nilẹ adulawọ, African Nations Championship. Idije naa ni yoo duro gẹgẹ bi idanwo fun igbimọ to ṣeto idije naa lori bi igbalejo idije African Nations Cup yoo ṣe ri l'ọdun 2021. Euro Cup Idije ere idaraya miran ti oju tun wa lara rẹ ni Euro 2020, ti yoo waye l'oṣu Kẹrin bakan naa. Idije naa yoo ko gbogbo orilẹede ilẹ Yuroopu pọ lati gba bọọlu. Pẹlu bi orilẹede Britain ṣe dibo ninu idibo to kọja, o da bi ẹ ni pe wọn n fẹ Brexit. Brexit Iṣẹlẹ nla miran ta tun maa foju sọna fun lọdun 2020 tun ni bi orilẹede Britain ṣe fẹ ẹ kuro ninu ajọ iṣọkan ilẹ Yuroopu. Igbesẹ naa ti bẹrẹ lati ọdun 2016 nilẹ Gẹẹsi, ti wọn si ti pinnu pe awọn yoo kuro. L'ọdun yii, o yẹ ki gbogbo rẹ yanju paapa lẹyin ti Boris Johnson wọle gẹgẹ bi Olootu ijọba lasiko idibo gbogboogbo to kọja. Awọn iroyin nipa eto ọrọ aje Eco currency L'opin ọdun 2019, Aarẹ France, Emmanuel Macron kede pe l'ọdun 2020, awọn yoo ṣe owo 'ECO currency' fun awọn orilẹede Africa to n sọ ede Faranse, to si n na cefas yoo ma a na. Orilẹede Ghana naa ni oun n'ifẹ si eto yii, nitori pe awọn orilẹede to wa ni Iwọ Oorun Africa ti n jiroro lati maa na owo kan naa, gẹgẹ bi ọna lari ran eto okoowo lọwọ. Visa Free Wiwọ Naijiria lai ni 'visa' Aarẹ Muhammadu Buhari kede l'ọdun to kọja pe oun yoo jẹ ki awọn ọmọ ilẹ Africa o maa wọ Naijiria, ti wọn yoo si gba iwe irinna 'visa' ti wọn ba wọle. O ni eyi yoo fi aaye gba kata-kara. Lati igba naa ni wọn ti ṣe alaye lọpọlọpọ lori ọna ti wọn yoo gbe e gba, ṣugbọn awọn eniyan ṣi n wo bi yoo ṣe ri. Afikun owo ori Ọpọlọpọ ọmọ Naijiria lo n wo bi nkan yoo ṣe ri l'ọdun 2020 fun awọn nkan bi i ọja rira lori ayelujara, ati fifi owo ranṣẹ nilana igbalode, ti afikun de ba owo ori wọn. Aarẹ Paul Biya ṣe ipade ijiroro lori wahala to n waye ni ẹkùn Anglophone Rogbodiyan Anglophone ni Cameroon Kini yoo ṣẹlẹ nipa rogbodiyan to n waye ni Cameroon, ati ni agbegbe Anglophone , eyi to ti bẹrẹ lati ọdun 2017, to si yọri si iku ọpọ eniyan? Lọdun to kọja, Aarẹ Paul Biya ṣe ijiroro gbogboogbo, ati awọn nkan miran to tun ṣe lati ri pe alaafia jọba ni agbegbe naa. Awọn kan sọ pe bo ṣe yẹ ki nkan o ri niyẹn, ṣugbọn awọn kan ṣapejuwe rẹ gẹgẹ bi nkan ti oloyinbo n pe ni 'smoke and mirrors'. 'Vision 2020' Ọpọlọpọ ijọba kaakiri agbaye ninu ikini ọdun tuntun wọn lo ṣe ileri awọn nkan ti wọn yoo ṣe lati mu idagbasoke ba orilẹede wọn. Fun Naijiria, Aarẹ Buhari ṣeleri pe oun yoo pari awọn oju ọna, kọle fun araalu, ati awọn nkan miran l'ọdun 2020. Afojusun Aarẹ Nana Akufo-Addo ni pe orilẹede Ghana yoo de ipo giga ni 2020. Aarẹ Cameroon naa ṣeleri lati koju awọn to ya ara wọn kuro ni Cameroon, to si kọ lati yọnda nkan ijagun wọn. O sọ pe Cameroon tuntun ti yoo faramọ bi nkan ṣe ri lasiko yii, ati afojusun fun ọjọ iwaju, ti n bẹrẹ.",0,yoruba àmọ́ olè iná tó kú níjọ́sí ṣèbí olè eérú ló fi bojú àbí jàndùkú ọ̀gẹ̀dẹ̀ tó kú níjọ́oníìí jàndùkú ọmọ rẹ̀ kó fi rọ́pò ni,0,yoruba "ni òun tí a kọ eḳọ nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Nitori eyi, ara eni lo ni ìgbà mi owó àkokò,.",0,yoruba Tí A Bẹ̀wò Jù,0,yoruba "Ní igba mi owó àkokò, Ọba ri Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú. ti Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "Ẹgbẹ agbabọọlu Real Madrid ti n gbaradi lati ko aadọrin miliọnu pọun le atamatase ikọ Machester United, Paul Pogba lori. Ọmọ ile Faranse ọhun ti sọ pe oun ko ni tọwọ bọwe adehun tuntun mii pẹlu ikọ Man United mọ lẹyin ti saa bọọlu yii ba ti pari. Pogba ni oju oun ti kuro ni Machester United, ati pe yoo wu oun lati kẹru oun lọ si orilẹede Spain ki saa tuntun mii to bẹrẹ. O ni ko si iye owo yowu ti Man United ba fi lọ oun, oun ko ni duro. Ṣaaju ni Madrid ti gbiyanu lati ra agbabọọlu naa lọdun to kọja ṣugbọn idunadura ọhun fori ṣọpọn. Everton tí bẹnu àtẹ lù bí ọkan lára àwọn agbabọọlu wọn Moise Kean ṣe yọ lọ sí apejẹ kan lásìkò tí òfin konile o gbélé wà níta. Iwe iroyin Daily Star Sunday lo gbe ìròyìn síta pe agbabọọlu náà tó ẹni ogún ọdún ya fidio ará rẹ níbi to tí n ṣe fàájì apejẹ nínú ilé rẹ. Everton sọ pé ọrọ náà ṣe àwọn ní kàyéfì bí ọkan ninu ogbontarigi agbaboolu àwọn yóò ṣe tapa sí òfin ìjọba àti ìlànà ẹgbẹ náà lásìkò àjàkálẹ̀ Covid 19 yí. ""Ẹgbẹ wà fí ìbínú ṣàfihàn ifehonuhan wà sí agbabọọlu yi"" Wọn fi kun ninu atẹjade pé àwọn tí sáájú tẹpẹlẹmọ pàtàkì titẹle alakalẹ ìjọba tó fi mọ dideju mọlé lásìkò ta wa yí nípa atẹjade orisirisi fawọn oṣiṣẹ wà"" Wọn wà tun so pe awọn ""gbosuba káre fawọn oṣiṣẹ ilera fún ifaraji wọn. Ẹgbẹ́ náà sọ pé ọnà ati fi im'oore hàn ní kí oníkálukú bọwọ fún wọn nípa ṣíṣe ohun tó tọ"" Iye èèyàn tó ti tọwọ àrùn Covid 19 lo tí tó ẹgbẹrun ogun nilẹ gẹẹsi. Kean ko se dáadáa ni saa akọkọ rẹ ni Premiership toun ti owó iyebiye tí wọn fi ra wa sí Everton lati Juventus,mílíọ̀nù meedogbon lè diẹ ní wọn rà tí kò sí ti gbá ju bọ́ọ́lù kan sáwọ̀n lọ ni sáà bọọlu yí. Orúkọ rẹ ti kun àwọn agbabọọlu Premiership miran to tí tapa sí òfin konile o gbele lasiko yìí Kyle Walker tí Man City n duro dè abajade iwadii eléyi tó n tọ pinpin bi o ti ṣe pé apejẹ nínú ilé rẹ pẹlu awọn obinrin oníṣẹ́ nàbì méjì kàn.Jose Mourinho ẹgbẹTottenham, Serge Aurier ati Musa Sissoko náà tapa sí òfin lọnà kan tabi omiran.",0,yoruba owo yin ama rokea ma se opolopo odun laye amin ase,0,yoruba yi yi ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Ní.,0,yoruba "Ìjàgbara. K'á jára wa gbà lọ́wọ́ọ ìdárú-dàápọ̀ ńlẹ̀ yìí. Kí a sọ fún un pé """"""""""""""""ó tó gẹ́!"""""""""""""""" #Nigeria2015",0,yoruba kò lè mọ ohun tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba "Ekiti: Ìjọba gb ìgbésẹ túntún láti fí ìyà jẹ ẹni tó bá bá ọmọdé lòpọ̀ Bákan náà ní wọn ó gbe orúkọ wọn jáde lóri ayélujara ile iṣẹ́ ìodájọ, àti pé wọn ó kéde orúkọ lóri rẹdíò àti tẹlẹfísọn, bẹ́ẹ̀ ni olóri tàbi ọba ìlú wọn yóò mọ̀ si pẹ̀lú ojú pátakó ni ilé iṣẹ́ Komisọna fún ètò ìdájọ ní ìpínlẹ̀ Ekiti ọgbẹ́nu Wale Fapohunda lọ fìdí ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀ ní ìlú Ado Ekiti lọ́nìí. Ekiti: À máa fi ojú àfipa bọ̀mọdé lòpọ̀ hàn lóri móhùnmáwòrán ''Àwọn ètò tí a ti ní nílẹ̀ ní pe à ó máà lẹ fótò àwọn ọdaran káàkiri ojú gbaaara ní àwọn ìlú tàbi ìletò wọn àti ìjọba ìbil.ẹ̀ ti wọn ti wá'' ""À ó sàlàyé fún àwọn ọba tàbi adari ìlú wọn ẹsẹ̀ ti wọn ṣẹ, gbé àwòrán wọn sóri ẹ̀rọ alátagbà ilé ìṣẹ́ ìdájọ ti ìpínlẹ̀ Ekiti"" À ó ṣe àyẹ̀wò ọp;ọlọ tipátipá fún, pà'pàá jùlọ ẹni ti ilé ẹjọ ba ti ni ó jẹ̀bi ẹsun fífí ipí bá ọmọde sùn tó fi mọ́ ẹni tó bá ń jẹ́jọ lọ́wọ́ Ọgbẹ́ni Fapohunda ni ìdí ti àwọn fi ń gbé irú ìgbéṣẹ̀ yìí ni pé irú ìwà ìbàjk yìí ti ń pọ̀ jù, bótill jẹ pé òun mọ pé àwọn ìgbéṣẹ̀ yìí jẹ èyí to lágbára, síbẹ̀ ìgbàgbọ́ wà pé yóò ràn àwọn lọ̀wọ́, ọ̀pọ̀ ará ìlú ní yóò sì ni àǹfàní láti sọ èrò ọkàn wọn. Gbogbo ẹni tó ba ti ṣẹ si òfin ní à ó lẹ orukọ wọn àti foto ''A tí ṣe ìpìdé pẹ̀lú àwọn tọ́rọ̀ kàn ní ǹkan bii ọ̀ṣẹ̀ méjì, sùgbọ́n à ń pinu láti pé gbogbo àwọn ènìyàn láti wa sọ èrò ọkàn wọn lóri ọ̀rọ̀ àwọn tó ń ba ọmọ dé lòpọ̀ tipátipá.'' Fapohunda ni ohun ìbànújẹ ló jẹ fún òun bí ẹsùn ìbọ́mọde lòpọ̀ ṣe ń pọ̀ si lójojúmọ́ p[llú gbogbo àwọn ti ilé ẹjọ ti ń dájọ fun ní ìpínlẹ̀ Ekiti àti pé ìnú gómìnà Fayemi ń bajẹ gidigidi lóri ọ̀rs náà O ní ìgbésẹ tuntun yìí àwọn lérò pé yóò jẹ ki àsírí àwọn ọdaràn yiìí máa tu tí yóò si fún ìjọba láǹfani láti maá yọ orúkọ àwọn irú ọdaran kúrò nínú àwọn ti wọn lé sàànú lagbà ẹwọn.",0,yoruba "ìbàdandun àtọ́wọ́dá, àwọn oníṣẹ́ ìṣẹ́ ni ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba òun tí a ní láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó ṣe pàtàkì.,0,yoruba _Ìwọ̀n Déédéé,0,yoruba "♫ Ẹ jẹ́ k'á so 'wọ́ pọ̀, k'á f'ìmọ̀ ṣ'ọ̀kan, gbé e, kí èmi gbé e!"""""""""""""""" - ni ohùn Sunny Adé. #NigeriaAt56",0,yoruba "wáyé.. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "friendly time"" string for the current day, strftime format. like ""Today 12:34 am",0,yoruba "RT @user: """"""""""""""""@user: Lọ́jọ́ òní ijó àjólọsíwájú ni, a ò ní jó àjórẹ̀hìn. Lágbára Olódùmarè. #adura"""""""""""""""" Amin oh! Mo se amin, mo ...",0,yoruba "tí Ọba fè mú, Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "Olùwo se. Nitori eyi, ara eni lo ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba "Fífì lẹpọ̀n àgbò ń fì lásán, ẹpọ̀n àgbò kìí já #Yoruba #oroyoruba @user",0,yoruba se fi. Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.,0,yoruba ... IYO (Salt) Tii O Ndun OBE (Soup) ... O Tun Lee Baa OBE Jee ...! ... E Jee Kii A Maa See Gbogbo N Kan Nii Iwon ...! #Yoruba. #OKAY.,0,yoruba òru àti ọ̀sán ọmọdé àti àgbà òrùlé àti àlejò olówó àti tálákà fún wa ní àpẹẹrẹ àwọn àjùmọ̀rìn ọ̀rọ̀ méjì mìíràn tí o bá mọ̀,0,yoruba "se fi. Nitori eyi, ara eni lo ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..",0,yoruba "Bi orilẹ-ede Naijiria ti darapọ mọ gbogbo agbaye lati ṣe ayajọ didena gbigba ẹmi ara ẹni, akọsilẹ ti fihan pe ọta le lugba eeyan o le mẹrin ni wọn ti ṣekupa ara wọn lorlẹede yìí lọdun mẹrin ṣẹyin. Nigba ti akori ti ọdun yìí jẹ́ ṣiṣiṣẹ pọ lati dena iwa pipa ara ẹni, eeyan 264 gbẹmi ara wọn laarin oṣu kinni ọdun 2017 sí oṣu kẹjọ ọdun 2020 yii. Ipinlẹ Eko lo wa loke tente, eeyan mẹtalelogun lo gbẹmi ara wọn lọdun mẹrin ṣẹyin nibẹ. Akọsilẹ fihan pe eleyii yatọ si awọn eeyan mii to pa ara wọn ṣugbọn ti awọn akọroyin ko gbe sita. Bẹẹ si ni iwa gbigba ẹmi ara ẹni lodi si ofin orile-ede Naijiria, koda ẹwọn ọdun kan ni ẹnikẹni to ba gbiyanju lati pa ara rẹ yoo fi gbára. Ipo kẹwaa ni Naijiria wa nilẹ Afrika ninu awọn orilẹ-ede ti iwa ipara ẹni tí wọ pọ julọ. Akọsilẹ fihan pe ogunlọgọ awọn eeyan yii lo mu kẹmika ""sniper"" rọrun nigba t'awọn miiran pokun so. Iwadii tiẹ tun fihan pe niṣe lawọn mii dana sun ara wọn ti wọn sì gba ibẹ dero ọrun. Dokita Maymunah Yusuf Kadiri to jẹ onimọ nipa aarun ọpọlọ sọ pe ibanujẹ ọkan, ijakulẹ, airiṣẹṣe, ọti mimu ati oogun oloro wa lara awọn idi to n mu ọpọ gba ẹmi ara wọn.",0,yoruba "Mekong Watch tẹ àwọn ìtàn wọ̀nyí jáde sórí ìwé ìròyìn pélébé àti sórí ẹ̀rọ ayárabíàṣá , wọ́n sì tún lò ó ní ìdánilẹ́kọ̀ọ́ nípa àyíká ní àwọn ìlú náà .",0,yoruba "Orilẹẹde metadinlogbon lo fowo si karakata lai si idiwo laarin awọn orilẹẹde Adehun naa ni wọn ro wipe yoo ṣe iranwọ fun ọja tita laarin awọn eniyan to le ni biliọnu kan pẹlu ireti pe owo to le ni trilion meji dọla. Alaye ti ile isẹ iroyin orileede Rwanda kan sọ wi pe ọrilẹẹde mẹtadinlọgbọn lo fọwọ si karakata lai si idiwọ laarin awọn orilẹẹde. Awọn ti o'n ṣagbatẹru adehun naa n lero wi pe aadọta orilẹẹde ni yoo la'nfaani karakata ti wọn ba fọwo si adehun naa. Saaju ki wọn to fọwọ bọ adehun naa ni Aarẹ orilẹẹde Naijiria Muhammadu Buhari ti yọwọ ninu re. Bi Naijiria ni ti o je okan gbogi lara awọn orilẹẹde ti karakata re munadoko nile Afrika ko se kopa je ipenija nla fun adehun naa. Olootu iroyin lori eto ọrọ aje fun ile isẹ BBC, Mathew Davies, ni iwoye wa pe adehun yi yoo mu adiku ba ainise to peleke laarin awọn ọdọ ti lawon orilẹẹde Afrika. Awọn iroyin miran ti ẹ le nifẹ si: Sugbọn o ni ipenija nla ni eleyi jẹ fun awọn ti yoo mu ala naa se.",0,yoruba "Ọ̀jọ̀gbọ́n Barber Karin ti ilé ìwé Birmingham ló rọ ẹ̀yà Yoruba bẹ́ẹ̀ láti fóju àsà yanjú ìsoro tó ń ṣẹ̀lẹ̀ láwùjọ. Ewi Yoruba maa n kilọ iwa ibajẹ, o maa n gbani nimọran, o maa n yonbo iwa rere, o tun maa n jẹ ki ori ẹni wu. Plateau: Àsìkó tó láti fi káádì ìdìbò yanjú ọ̀rọ̀ Buhari Asiko ti to ki awọn ọmọde mọ pataki ewi kike ati oriki ki ede Yoruba ma baa parun. Ọ̀jọ̀gbọ́n Barber Karin ti ilé ìwé Birmingham ló rọ ẹ̀yà Yoruba bẹ́ẹ̀ láti fóju àsà yanjú ìsoro tó ń ṣẹ̀lẹ̀ láwùjọ. Àyàn: Ti mo bá ti gbọ́ ohùn ìlù ni àárẹ́ mi ma ń lọ! Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Óhún nínú ọ̀rọ̀ àpilẹkọ rẹ̀ níbí ayẹyẹ kan nílù Oshogbo. Ó ní kí àwọn Yorùbá máà kó ẹyin àsà Yoruba sínú agbọ̀n kan, nítori fífi onírúurú ojú wo àsà Yoruba lọ̀nà àbáyọ. Ọ̀jọ̀gbọ́n Barber ní tí wọn ba fi ojú pàtakì àsà ilẹ̀ Afíríkà àti àwọn ìtan wọn sínu ìṣèṣe, yóò ràn wọn lọ́wọ́ láti rí ojúutu sí àwọn ńkan to ti ṣẹlẹ̀ sẹ́yìn. Bákan náà ọ̀nà àbáyọ yóò wà fún àwọn nkan tó ń ṣẹlẹ̀ lásìkò yìí àtí ìsòro àgbáye lọ́jọ́ iwájú.",0,yoruba agba a yi gbe ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọba lo aye àìlẹ̀.,0,yoruba àwọn ìkòkò tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa iṣẹ́: ti o pẹ jú nìlọ̀ ni ọ̀nà tí ẹ̀ọ́ kan máa ń gbé ìyẹ̀ alẹ́.,0,yoruba dídì yìí ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Bàbá lo aye àìlẹ̀.,0,yoruba "Nígbà tí ó máa fi di ìdájí ọjọ́ Ajé, ìròyín ti kàn wípé àwọn ọ̀tá ti ń sún mọ́. Nígbà tí ọ̀sán pọ́n, ìró ìbọn ti gba afẹ́fẹ́, èyí ti kéde wípé ogún ti bẹ̀rẹ̀. #OgunDahomeyAtiEgba",0,yoruba "Nínú àtẹ̀jáde kan tí olùrànlọ́wọ́ abẹnugan lórí ìròyìn àti ìkéde , , Lanre Làsísì fi síta láti ọwọ́ abẹnugan ilé ìgbìmọ̀ asojú , , Fémi Gbàjàbíàmílà láti fi kí àwọn òṣìṣẹ́ fún àjọ̀dún ayẹyẹ tí wọn ń ṣe àti láti fi gbósùbà fún àwọn òṣìṣẹ́ ọ̀hún lórí ipa ribi - ribi tí wọn ń kó láti bí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọdún ,",0,yoruba "Ọdún méjì ni ó gba àwọn ọmọ ogun orílẹ̀ èdè Nàìjíríà láti gba ọmọdébìnrin kan sílẹ̀ , nínú oṣù Òkúdù ọdún - un 2016 .",0,yoruba Ọba lọ. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé.,0,yoruba Lucian Kendel Hippolyte’s pẹ̀lú orin - in ti wọn láti ṣe àrídájú wípé iṣẹ́ náà dé ibi tí ó yẹ kí ó dé .,0,yoruba "onà.. Nitori eyi, ara eni lo ni ìgbà mi owó àkokò, Ọba ri A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..",0,yoruba Ìpènijà márùn ún tí yóò kojú olóòtú ìjọba tuntun ní UK,0,yoruba "O ṣalaye pe ọgba ẹwọn ti oun lọ ""jẹ ibi ti kii ẹ ibi too ti le jẹ́un to wu ẹ tabi ri iyawo abi ọmọ. O jẹ ibi ti ẹni ti ko ṣẹ ti lee ba ara rẹ boya tori Ọlọpaa ko ṣe ẹjọ daadaa"". BBC Yoruba gbera lọ si ile ati ijọ gbajugbaja Wolii ti wọ́n dajọ́ ẹwọn ọdun kan gbako fun amọ ti gbogbo eeyan dede gbọ pe o ti kuro lọgba ẹwọn lai tii lo ọdun meji oloṣu mejila naa pe. Wolii Genesis ni ṣugbọn ẹni to ba ni Kristi a kan mọọmọ gba fun Ọlọrun ni pẹlu ohun toju rẹ yoo ri lọgba ẹwọn. Genesis Global: Sáká lara Woli Israel Ogundipe dá, kìí ṣe àìlera ló mú kí wọn fi sílẹ̀ lẹ́wọ̀n Mo máa ń dédé ṣubú lulẹ̀, tẹ́ẹ bá fi ọwọ kàn mí lásán, kódà lójú ọ̀nà márosẹ̀ - Fatimah Aderounmu Ṣé o mọ̀ pé o leè rí omira abẹ́ obìnrin míì rà tàbi yọ̀ǹda tìrẹ fún lílò? 'Èmi ọmọ Ikorodu ọ̀ga, ọmọ aṣalẹ̀ jẹ́jẹ! Wo bí àwọn ọmọdé ṣe ń fi Oríkì Yorùbá dábíra ní Children's Day Ìgboro ayélujára ń gbóná lọ́wọ́lọ́wọ́ mọ́ Remi Tinubu lẹ́yìn tó pe obìnrin kan ní Tọ́ọ̀gì Ẹsun jibiti to to miliọnu mọkanla naira ni wọn fi kan Wolii Genesis eyi to pa ohun ati arabinrin kan, Laide Oni Williams to n gbe ni UK pọ. Wolii Genesis sọ ohun toju ri ati ohun to ba bọ lati ọgba ẹwọn to lọ bọ tori wọn da a silẹ lẹyin oṣu mẹrin to bẹrẹ ijiya ẹsun naa dipo ọdun kan to yẹ ko lo nibẹ. Ọrọ naa wa dabi owe kan to sọ pe igba gbogbo ni ọrọ kii ṣi lori alabahun tori bi ọpọlọpọ eeyan ṣe maa n wo awọn iranṣẹ Ọlọrun to ba ti ni iru idojukọ yii. TAMPAN pàṣẹ pé 'director' kankan kò gbọdọ̀ pe Nkechi Blessing àti Adams Kehinde sí iṣẹ́ mọ́ Pé mo gba ìwọ́de lááyè kò túmọ̀ sí pé mo faramọ́ Oduduwa Nation - Akeredolu Àwọ̀ ọmọ mi máa ń ṣípẹ̀ẹ́pẹ́ bíi ti ẹja ni, ẹsẹ̀ ń dùn ún kódà, kò tún ríran dáadáa - Ìyá Hameeda Wo àwọn orílẹ̀èdè tí ìbálòpọ̀ akọsákọ ti lòdì sí òfin",0,yoruba ẹ̀kọ́ dídì yìí ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Bàbá lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "ọ̀ṣun ìlú. Nitori eyi, ara eni lo ni ẹ̀ká àwẹ eyti o gbe lori iwa rere.",0,yoruba "Sammie Okposo: Torí mo bá obìnrin kan ní àjọṣepọ̀ l‘Amẹ́ríkà, mó ń wá ojú Ọlọ́run",0,yoruba Orúkọ míràn wo la npe ẹ̀gẹ́ #ibeere,0,yoruba àkerekere. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé.,0,yoruba "Àbájáde tí ipa wọn kó ni pé Twitter di pápá ìròyìn ayédèrú tí ó ń ṣe ẹlẹ́yàmẹyà àti ìsọkiri láti mú èrò àwọn olóṣèlú ṣẹ ṣáájú àsìkò ìdìbò , ní àsìkò ìdìbò àti lẹ́yìn ìdìbò ọdún - un 2019 lórílẹ̀ - èdèe Nàìjíríà .",0,yoruba ìwé ṣe pàtàkì ó ṣe kókó láyé tí a wà yìí ṣùgbọ́n o ọ̀kan lára ohun tí ọmọbìnrin nílò fún ọjọ́ iwájú ni ẹ̀kọ́ ilé,0,yoruba "Títúmọ̀ rẹ̀ sí """""""" yam flour """""""" dín agbára ìpèdè náà kù — yóò sọ """""""" ipò Yorùbá nù . """"""""",0,yoruba Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ìmọ̀ iṣẹ́ ìròyìn náà ṣe ètò alálàyé oníṣẹ̀ẹ́jú 5 tí ó dá fìrìgbagbòó lóríi pàtàkìi ẹ̀rọ - ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ fún ìmúṣẹ àwọn ìlépa ìmúdúró ìdàgbàsókè .,0,yoruba bákan náà a ń tọ pẹpẹ eré ẹ̀yọ̀ láti sàmì ayẹyẹ ìrántí èkó bí i tí ó mú ìjọba gbé e kalẹ̀,0,yoruba "Bí ọmọ kò bá ba ìtàn, o di dandan kó ba àrọ́bá to jẹ baba ìtàn. Orilẹ-ede Naijiria ṣeto idibo to yaranti ni ọjọ kejila, oṣu kẹfa, ọdun 1993 eyi ti Ọgagun Ibrahim Babangida to n tukọ Naijiria nigba naa wọgile. Babangida gbe ijọba kalẹ fun Oloye Ernest Ṣonẹkan labẹ ijọba fìdíhẹẹ́ ni èyi ti Ọgagun Sani Abacha gba ijọba lọwọ rẹ̀ lọjọ kẹtadinlogun, oṣu kọkanla, ọdun 1993. Èrò àwọn ènìyàn lórí Abacha lẹyin ogun ọdun to ti kú Awọn kan gboriyin fun un nipa eto ọrọ aje ṣugbọn ọpọ eeyan lo bẹnu atẹ lu Abacha pé iṣẹ ọwọ rẹ buru jai nigba aye rẹ. Yoruba ni: ìgbẹ̀yìn lójù nitori pe ohun gbogbo tóo ba ṣe loni, ọrọ itan ni lọla. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:",0,yoruba Penis in Padlock: Ọkùnrin tó fi nǹkan ọkùnrin rẹ̀ sínú àgádágodo torí adùn ìbálòpọ̀ wọ gàù,0,yoruba Ìle-Ìfẹ̀. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó wáyé..,0,yoruba "Adari ileeṣẹ Aṣa ni ipinlẹ Ekiti, Wale Ojo sọ fun BBC Yoruba pe awọn n ko awọn aṣa awọn jade lati ṣe afihan rẹ faraye ni. ""A sọ ijó di owó, ohun t'ọ́kùnrin ń ṣe l'Ekiti, obìnrin lè ṣe é"". Ọgbni Wale sọ pe Ekiti Festival ti mú ọlá àti oríire wọ ìlú Ekiti, ""o n gbe ọgbọn inu ati imọ awọn ọdọ jade sita"". O tẹsiwaju pe gbogbo ìlú tó wà ní Africa ló kù tí Ekiti máa fìwé pè lọ́dún 2020 lati wa wo ọgbọ, imọ ati oye ti Ọlọrun fi sọlẹ si ilu Ekiti. Lóòtọ́ lóòtọ́, kò sí àṣàdànù nínú àwọ́n afihan ohun agbaṣa ga to waye nibi EKiti Festival 2019. Marlian, òfégè ìgbéyàwó Buhari, Fatoyinbo àtàwọn ìṣẹ̀lẹ̀ ńlá tó mi ìgboro tìtì ní 2019 Bukola Saraki fi 'Gbas Gbos' ọ̀rọ̀ ránṣẹ́ lórí 'ilẹ̀ bàbá rẹ̀' tí ìjọba Kwara gbà padà Oluwo àti Olorì àná, Chanel Chin tahùn síra Lórúkọ ìdílé Diya, a gbúdọ̀ ti ẹsẹ̀ òfin bọ ìkú tó mú ọkọ àti ọmọ méjì lọ - Agbẹjọ́rò Ṣé ẹ mọ̀ pé Ekiti ni ìlú tí Ògún Lákááyé wọlẹ̀ sí? Ilu Orunmila naa, Ekiti ni. Eṣu tó ma ń dá àbò bo àwọn èèyàn tirẹ̀, Eṣu Ẹlẹ́gbẹ̀rà to maa n gba awọn eeyan lọjọ ibi ba de, ilu Ekiti ni gbogbo wọn ti wa gẹg bi adari aṣa ipinlẹ naa ṣe sọ ọ. Iyawo gomina ipinlẹ Ekiti, Erelu Bisi Fayemi kadi eto ajdun naa pẹlu rọ̀ iwuri nipa Ekiti pe ""Orin Ekiti dá yàtọ̀, ijó wọn, oke nla nla atawọn nkan to jẹ pe owo lawọn eeyan fi lọ n wo wọn nibomiran"".",0,yoruba Àwọn ènìyàn ti gba wa wey o ṣe.,0,yoruba "Ọrọ yii ni wọn lo jẹyọ lasiko ti ẹgbẹ NANS lọ se abẹwo si aarẹ Buhari nile ijọba Aso Rock nilu Abuja. Ninu fọnran aworan to lu sita lẹyin abẹwo naa, ni Akpan ti salaye pe awọn akẹkọ Naijiria pọ pupọ, ti wọn si fẹẹ to ọgọrin miliọnu niye. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Akpan wa rọ aarẹ Muhammadu Buhari pe to ba lee lo ẹka yii bo se yẹ, oun n fi da loju pe, yoo ri ibo ti yoo to ogun miliọnu laarin awọn ọdọ naa. Bakan naa ni awọn asaaju ẹgbẹ akẹkọ lo anfaani abẹwo wọn ọhun si ọdọ Buhari, lati ki ku ayẹyẹ oriire ọjọ ibi ọdun mẹrindinlọgọrin to pe loke eepẹ. Rashidat Fawẹhinmi: Sísọ èdè Yorùbá kò leè ba Gẹ̀ẹ́sì jẹ́ lẹ́yìn odi Akpan tun gbadura fun Buhari pe, aseye ni yoo se ninu eto idibo aarẹ ti yoo waye losu keji ọdun yii. Sugbọn ẹyin lohun, to ba ti jabọ, ko tun se ko mọ, awọn ọmọ orilẹede yii ti n sọ ero ọkan wọn lori ọrọ ti ohun ti aarẹ ẹgbẹ akẹkọ ilẹ wa naa sọ. Lero tawọn eeyan kan, ohun ti Akpan ba lọ si Aso Rock kọ lo kọju mọ, kaka ko si maa bẹ Buhari pe ko dahun awọn ibeere tawọn olukọ fasiti n beere lọwọ ijọba, ọrọ oselu lo mojuto. Lawọn oju opo ikansiraẹni, paapa Twitter, awọn ọmọ Naijiria kan ni, bi ẹgbẹ awọn olukọ fasiti se n wo isẹ niran lo yẹ ko mumu julọ laya awọn akẹkọ yii, ki wọn si wa ọna ti ijọba ati ASUU yoo se fi eegun otolo to aawọ aarin wọ. Koda, awọn miran tiẹ foju laifi wo kaadi ọjọ ibi ti ẹgbẹ akẹkọ naa gbe fun Buhari lati fi ki ku oriire ọjọ ibi. Jikan Sabo, @Usmern_ssg, o ni se ẹgbẹ NANs to n dun mahuru-mahuru laipẹ yii lati tẹsẹ bọ sokoto kanna pẹ́lu Buhari, lo wa n pada fun ni kaadi ọjọ ibi yii? Ogeadiro_official, @ogeadiro1 naa kin Jikan lẹyin pẹlu afikun pe Naijiria yoo maa bajẹ si ni. Coker Pẹlumi, @ cokeroluwapelu2 woye pe ileri ibo ti aar ẹgbẹ NANS se fun Buhari yii, lo se afihan bi ẹka asaaju ẹgbẹ NANs ti bajẹ, to si jẹra si. @mrtsmilez lero tiẹ ni orilẹede Naijiria ree, nibi ti gbogbo wa ti jẹ ọdaran, ti aarẹ ẹgbẹ akẹkọ si ti gba owo. Ogunranti Abiodun, @Wonder_11 sọ loju opo Twitter rẹ pe, ọkan aarẹ ẹgbẹ NANs ti daru, to si n mu idarudapọ wa gẹgẹ bi orukọ rẹ ti fihan, o ni ko yara tete yọ orukọ toun kuro ninu ogun miliọnu akẹkọ ti yoo dibo fun Buhari.",0,yoruba @user jọ̀wọ́ gbìyànjú kí o mọ̀ ọ́ #translation pls make an attempt to know #Yoruba ;-) #learnyoruba,0,yoruba wáyé. ti Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa aráyé: ti o jare.,0,yoruba "Ojú larí, ọ̀rẹ́ ò dénú #Yooba #Yoruba",0,yoruba "Adajọ Oluwatoyin Taiwo, ti ile ẹjọ giga ipinlẹ Eko, lọjọ isẹgun, da ẹjọ iku fun pasitọ kan ati amugbalẹgbẹ rẹ. Orukọ awọn ọdaran mejeeji ni pasitọ Erinmole Adetokunbo ati Adedoyin Oyekanmi. Adajọ ni wọn jẹbi fun bi wọn ṣe pa ọmọde kan, Kazeem Rafiu, ẹni ọdun meje ni agbegbe Ikorodu ni ipinlẹ Eko. Adajọ Taiwo lo gbe idajọ naa kalẹ, lẹyin ti awọn olujẹjo ni awọn jẹbi ẹsun naa. Oyekanmi ati Adetokunbo ni iwadi awọn ọlọpaa safihan pe, wọn lẹdi apo pọ lọjọ keje oṣu kẹfa lọdun 2017, ni agbegebe Odekekere, lati gba ẹmi ọmọdekunrin naa. Iwadi fi han awọn mejeeji bẹ ori ọmọdekunrin naa, ti wọn si sin ori naa si abẹ ile ijọsin pasitọ naa fun etutu. Awọn eeyan adugbo naa lo kẹfin wọn , ti wọn si ransẹ si ọlọpaa lati wa mu pasitọ ati amugbalẹgbẹ rẹ. Lẹyin ọdun mẹrin ni ahamọ, wọn bẹrẹ igbẹjọ lori wọn lọdun 2021. Ninu idajọ rẹ, Adajọ Taiwo ni iṣẹlẹ naa lo bani ninujẹ bi awọn olujẹjọ ṣe pa ọmọ kereke lati fi ṣe etutu. “Ẹsẹ ti awọn olujẹjọ da lo jẹ ẹsẹ nla pẹlu iwa ọdaju, ti wọn fi mọọmọ pa ọmọdekunrin naa lai wo ti awọn obi ọmọ naa, ti o le wulo fun wọn ni ọjọ waju.” “Idajọ mi ree, mo pasẹ ki wọn yẹ igi fun iwọ Adedoyin Oyekanmi ati iwọ Erinwole Adetokunbo fun bi ẹ dijọ ṣeku pa Kazeem Rafiu, ki Ọlọrun wa pẹlu yin.” Ajọ to n gbogun ti egboogi oloro ni Najijiria, NDLEA, ti fi ṣikun ofin mu pasitọ kan, Okon Effiong, ti wọn ka agba mẹta egboogi crystal methamphetamine mọ lọwọ. Egboogi oloro yii naa tun ni wọn tun n pe ni ti ọpọ mọ si “Mkpuru Mmiri” mọ lọwọ.” Ajọ naa ni awọn gbabọ pe orilẹ-ede India ni wọn ti gbe egboogi naa wọle. Ninu atẹjade kan ti agbẹnusọ ileeṣẹ naa,  Femi Babafemi fi lede lo ti ṣi aṣọ loju ọrọ naa. O ni “Inu ẹru kan ti iwọn rẹ to aadọrun kilo ni wọn gbe egbogi oloro naa si lagbegbe Ojuelegba, niluu Eko. Amọ akara wọn to tu sepo loju ọna marosẹ Umuahia si Ikot Ekpene nipinlẹ Akwa Ibom. “Egboogi naa, ti wọn di ni iwọn ọgbọn sinu agba kọọkan ni wọn n gbe lọ fun ọkunrin kan to jẹ pasitọ, iyẹn Anietie Okon Effiong.” Gẹgẹ bii ohun ti Babafemi sọ, orilẹ-ede Cameroon ni wọn n gbe egboogi naa lọ. Eyi lo n waye lẹyin ti ajọ yii kan naa ti kọkọ gbẹsẹle egboogi oloro ‘crystal meth’ yii kan naa, ti awọn kan n gbe lọ si orilẹ-ede Australia, Indonesia ati Philipines. NDLEA tun gbẹsẹle egboogi igbo, ti ileeṣẹ kan to maa n fi ẹru ranṣẹ n gbe lọ si Dubai, ni United Arabs Emirates. Yatọ si awọn egboogi ti NDLEA gbẹsẹle niluu Eko yii, wọn tun fi ṣikun ofin mu awọn eeyan mii to n pin egboogi oloro kaakiri Naijiria. Lara wọn ni baba agba kan, to jẹ ajagunfẹyinti, Usman Adamu ti wọn mu ni Sokoto lori ẹsun pe o n ta agboogi oloro fun awọn janduku. NDLEA ni ẹni aadọrun ọdun ni baba agba naa.",0,yoruba "Ọ̀sun náà bínú lọ, ó di odò Ọ̀sun nílú Oṣogbo, bákannáà ni Ọbà pòórá wọ nnú odò Ọbà. #worldsangofestival #Sango #Oyo",0,yoruba "Ní ọdún 2017 , ìgbìmọ̀ àgbà àti àjọ ìpínlẹ̀ lábẹ́ ẹgbẹ́ olóṣèlú Communist ìlú China kọ ìwé àṣẹ kan tí a pe àkọlée rẹ̀ ní “ Ìmọ̀ràn lórí imúdiṣíṣẹ iṣẹ́ ìgbélárugẹ àti ìdàgbà àṣà ìbílẹ̀ China dé ibi gíga “ .",0,yoruba nilo ayẹwo wey ti o nuni ti o nuni ti o nuni ti o ní wúlò.,0,yoruba àkerekere. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó ṣe pàtàkì.,0,yoruba "Ẹyin ni wọ́n fi n gba ìbále ẹlòmiran lára wa ki a to lọ pàde àwọn oníbara Lasiko to n kopa lori akanse eto BBC Yoruba, Adeola ni iṣẹ aserunlọsọ ni oun kọ nilu Abuja, ki wọn to sọ fun oun pe, awọn eniyan kan wa to lee gbe oun lọ silu oyinbo fun bii oṣu mẹta, lati le ri owo kojọ fun idasilẹ isẹ tara oun. Akanse eto naa lori Facebook BBC Yoruba ree: Content is not available End of Facebook post, 1 Arabinrin naa gbera lati ilu Abuja wa si ilu Eko ni ibi ti wọn ti fi aworan awọn ọmọ Naijiria ti wọn n ṣiṣẹ pẹlu oyinbo lọhun han, eyi to mu ki ori rẹ wu lati tẹle wọn lọ silẹ Yuroopu. Kí lo tíì rí nípa Amotekun? Ẹ sùnmọ́bí, ẹ wo gbankọgbì! Adeola ko ni iwe irinna kankan, amọ o ni awọn to mu ohun lọ sọ wi pe, Côte d'Ivoire ni wọn yoo ti se iwe irinna ọhun fun oun, ti wọ̀n si sekilọ fun pe ko gbọdọ fi ọrọ naa to ẹnikẹni leti, titi ti yoo fi lọ. Mercy Aigbe, Lateef Adedimeji, Ayoola Ayolola kó sọ́wọ́ ìbéèrè kàbìtì, ó di gbọin!!! Ọmọbìnrin Adeola, ẹni ọdún mẹ́ẹ̀dọ́gbọ̀n sọ ìrírí rẹ̀ lásìkò tí wọ́n fi ṣe òwò ẹrú lọ sí òkè òkún. Ọmọbinrin ti wọn fi ṣe owo ẹru naa kuro ni ile ni Osu Kẹwa ni ọdun 2017, ti oju rẹ si ri to loju ọna ko to de Cote D‘ivoire, ti ẹni to mu lọ si faa le obinrin kan lọwọ nibẹ. Nigba ti wọn de Côte d'Ivoire, ni wọn mu Adeola lọ si ile obinrin ti o sọ wi pe ki oun bura pe oun ko ni salọ, to si gbe omi silẹ́ lati bura lẹyin to kede pe isẹ asẹwo ni oun yoo maa se fun oun. Arabinrin ọmọ Côte d'Ivoire sọ fun Adeola pe ninu iṣẹ naa ni ẹni to ra a lẹru yoo fun un ni miliọnu meji Cefas, amọ o kọkọ kọ jalẹ, ko to di wi pe o gba lẹyin ti wọn ran an leti pe wọn ti mulẹ. ""Ọkunrin mẹta ni wọn kọkọ fi bẹrẹ owo naabi fun mi, ti maa si lọ kowo fun ọga lẹyin ti mo ba ti ṣiṣẹ tan. O si kere tan ọkunrin mẹẹdogun lo n ba mi lopọ ni ojoojumọ."" Orilẹede Libiya ti jẹ ọnọ pataki awọn aṣikiri ti n gbiyanju lati de okun gusu ilẹ Yuroopu lati ori okun. Adeola ni ""ẹyin ni wọn fi n gba ibale obinrin ti wọn ba fẹ fi ṣowo nabi, a ko si ri ounjẹ asaara loore kankan jẹ nibẹ. Koda, ori ẹni ni wọn ko awa obinrin mẹrin si ninu yara kan, ti awọn ọkun yoo si wa lati ba wa lopọ lasiko kannaa"" Lẹyin ọpọlọpọ iya ati iṣẹ, ọga Adeola le e kuro pe o ti san owo oun tan, ti Adeola si di ẹni ti n sun ita, ki obinrin kan to jẹ ọmọ Naijiria to seranwọ lati gbaa sile, nibẹ si lo ti foju han si pe o ti ko aisan to nii se pẹlu nini egbo loju ara. Ogunlogo awọn eniyan lo n gba ori okun Libya k'oja si ile Yuroopu Ajọ Alaanu kan ti Arabinrin Motilola Adekunle n dari rẹ ni Adeola pade ni ori ẹrọ ikansiraẹni Instagram nibi ti o ti ke sita, ti wọn si seranwọ fun lati pada wa si orilẹede Naijiria ni Osu Kejila, Osu 2019. Adeola wa n rọ awọn obi, alagbatọ ati ijọba lati dena iwa fifi ọmọ Naijiria sowo ẹru loke okun nitori ọpọ ewu to rọ mọ.",0,yoruba láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó ga jù.,0,yoruba mo ní awôn èroakonanpamónpélébé powerbanks fún títà tē àtèjísé sí fún iwadi tàbí ibeere,0,yoruba Signs of covid-19: Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ àwọn tó ń ṣe ayédèrú abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 ní South Africa àti China,0,yoruba "ni ìbàdandun àtọ́wọ́dá, àwọn oníṣẹ́ ìṣẹ́ ni a ní nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn aláìì lẹ̀.",0,yoruba odò ilẹ̀ yorùbá wo ni à tún ń pè ní àgbóṣòkun,0,yoruba "Ẹkun omi ni Ghana Lalẹ ọjọ Aiku lojo ọhun bẹrẹ ti o si rọ fun wakati mẹta gbako. Nibi ti ajọ to n ri si ọrọ pajawiri lorilẹ-ede Ghana (NADMDO) ti n doola ẹmi awọn eeyan ni wọn ti ri oku eeyan mẹrin lagbegbe Ashaiman, bẹẹ ni wọn tun ri omiran lagbegbe Odorna. Colorado ni Amẹrika àti odò Awaye ní Naijiria nikeji àdágún órí àpáta ní gbogbo àgbáyé! Igbakeji adari ajọ to n ri si ọrọ iṣẹlẹ pajawiri, Seji Saji to ba BBC sọrọ, fidi rẹ mulẹ pe awọn ri oku eeyan mẹrin to ku ninu ọkọ awọn ologun lagbegbe Adjei-Kojo. Omíyalé gbẹ̀mí èèyàn méje, o tún ba dúkìá púpọ̀ jẹ́ O ṣalaye pe awọn eeyan naa sa wọ inu ọkọ ologun lati sa asala fun ẹmi wọn ni, ṣugbọn eyi ko da iku wọn duro. JAMB 2019: A ó fagi lé ìdànwò ẹni tó bá ṣe aṣemáṣe Iroyin kan tiẹ sọ pe ina mọnamona gbe awọn kan ninu awọn eeyan to ku nigba ti awọn mii si rì somi. Segalink:ìkùnsínú pọ̀ láàrin àwọn agbófinró bẹ́ẹ̀ wọn kò ni agbẹnusọ Ṣugbọn ajọ NADMDO ni iwadii si n lọ lọwọ lori iṣẹlẹ ẹkun omi naa. Ọ̀dọ́kùnrin tó kọ́kọ́ ṣe ẹ̀rọ tó ń tu ìyẹ́ lára adìyẹ",0,yoruba ẹ̀kó. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba "Mbah fi kún pé yàtọ̀ sí iroyin ti wọn ń tàn kálẹ́ pé àwọn òpó iná tó ń gbéna kiri ló bajẹ àwọn ibùdó àmúsagbara ni ọ̀rọ̀ náà kan Nínú àtẹ̀jáde tí agbẹnusọ ilé-iṣẹ́ ọ̀hún Ndidi Mbah, fi síta pé àwọn ohun àmúṣagbára mẹ́fà ló ti dẹnukọlẹ̀ káàkiri. Ó ní àwọn ilé-ìṣẹ́ Gáàsì Nàìjíríà ( NGC) tí fi léde ní ọjọ́ kẹẹ̀dógún osù yìí pé gbogbo rẹ̀ ti jẹ́ra tan, atipe àwọn kanga àfẹ́fẹ́ tí Shell náà ti ní ìsòro ní ọjọ́ kẹrìndínlógún oṣù yìí bákan náà. Èyí ní wọn ló ṣokùnfà ẹgbẹ̀rún kan lé méjìlélọ́gọ́rin mẹgawaati tó já kúro nínú iná àmúṣagbára Nàìjíría. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Abiola: Mínístà Adewole jẹ nínú ànfààní ọ̀la rẹ̀ Àtẹ̀jáde ọ̀hún ní àwọn ibùdó àgbara tí ọ̀rọ̀ ọ̀hún kan ní Ihovbor, Azura, Omotosho gas, Geregu gas, Olorunsogo gas, Sapele àti ibùdó àmúsagbára Egbin to ń gbiayànjú àti sàkójọ ọgọ́ta mẹgawaati, ibùdó àmúsagbara Afam VI. Mbah fi kún un pé yàtọ̀ sí iroyin ti wọn ń tàn kálẹ́ pé àwọn òpó iná tó ń gbéna kiri ló bajẹ àwọn ibùdó àmúsagbara ni ọ̀rọ̀ náà kan. Ó ní àwọn NGC ń ṣiṣẹ̀ takuntakun láti ríi dájú wípe ọ̀rọ̀ níyanjú.",0,yoruba "Biṣọbu ọhun sọ fun BBC Yoruba pe adura nikan ṣoṣo lo le dẹkun arun Coronavirus, kiiṣe titi ile ijọsin pa. O ni ""A ko le sọ pe ka ti ile ijọsin nitori Coronavirus, nitori ori bibẹ kọ ni ogun ori fifọ."" Opayinka sọ pe Ọlọrun mọ si gbogbo ohun to n ṣelẹ patapata, ati pe Ọlọrun nikan lo le yanju gbogbgo iṣorọ ati aisan to ba n ba aye finra lọwọ yii. Aṣoju PFN naa sọ pe ohun to yẹ ki awọn ọmọlẹyin Kristi ṣe ni pe ki wọn gbohun adura soke ju ti atẹyinwa lọ. Alufa naa tẹsiwaju pe Ọlọrun lo le aisan Ebola lọ, nitori naa Ọlọrun nikan naa lo le ṣegu arun Coronavirus. Nipa pe ọna ti ajakalẹ arun fi n tan kalẹ ni kikorajọ ọpọ eeyan, o ni ẹmi eṣu ko le raye laarin awọn ọmọ Ọlọrun. Opayinka sọ pe ""Ẹmi eṣu to n kaakiri ninu afẹfẹ ni Coronavirus, ti ẹni to ba ni arun ọhun ba ti n wọle sinu ile ijọsin, ẹmi naa ko ni ba wọle. ""Ti eeyan ba wọle sinu ile ijọsin pẹlu ẹmi naa, ẹmi naa ko ba iru ẹni bẹ jade, bẹẹni ko ni ko arun naa ran elomiran."" Nigba to n sọrọ lori pe ti ijọba ba paṣẹ pe ki wọn ti awọn ile ijọsin, Opayinka sọ pe ijọ yoo tẹlẹ aṣẹ ti ijọba ba pa lori arun naa. Opayinka rọ ijọba ni ipari ọrọ rẹ pe, ko ma gbe agadagodo ṣenu ọna ile ijọsin latari arun Coronavirus nitori ijọ nikan ṣoṣo ni ọna abayọ si araun naa to n tan kaakiri agabaye. Elebuibon: Àwọn àṣà àtọ̀húnrìnwá ló fa títa ẹ̀jẹ̀ nítorí ògùn owo",0,yoruba "Ní gbogbo ilẹ̀ #Yoruba, enìkan ṣoṣo ni kì í dọ̀-bá-ilẹ̀ (dọ̀bálẹ̀) fún ọba, ta ni ẹni náà? #Ibeere #Yoruba",0,yoruba "ni ìgbà mi owó àkokò, Baàlè ri Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba wúlò. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ àti ìbi tí wọn wà.,0,yoruba "vidíò yorubá tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "ìwájú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba daadaa ni odua a gbe wa o,0,yoruba tìkẹ́ gbé joko yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba mo napá nasẹ̀ ara mi yá gágá,0,yoruba Fi ààyè-iṣẹ́ lọ́wọ́lọ́wọ́ nìkan hàn,0,yoruba ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa iṣẹ́: ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ àti ìbi tí wọn wà.,0,yoruba 1960 ni Abàmì-ẹ̀dá fẹ́ ìyàwó àkọ́fẹ́; Rẹ̀mílẹ́kún Taylor ní ìlú Lọ́ńdọ̀nù. #Fela #NiIranti #Egungun #Yoruba,0,yoruba "Odò #Ikorodu já sí odò Agboi, tí ó já sí odò #Ogun. Bẹ́ẹ̀ làwọn #CMS ṣe gbà á níjọ́hun àná. #Yoruba",0,yoruba "RT @user: @user ope, iyin,ati ogo, fun Eledumare oba to ni kokoro aanu lowo, iba fun oba awon oba, HELLO Eledumare oba aj ...",0,yoruba "Sunday Igboho woye ọrọ yii nigba to n sọ ero rẹ lori oniruuru atako to n waye nipa agbekalẹ ikọ alaabo ọhun, tawọn gomina mẹfẹẹfa lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria da silẹ. Igboho, nigba to n fesi si ọrọ asaaju ẹgbẹ Miyetti Allah nipinlẹ Bauchi, Alhaji Sadiq Ahmed, to ni ki ijọba wọgile ikọ naa nitori pe, ko si aabo mọ lati gbe nilẹ Yoruba nitori agbekalẹ ikọ Amotekun. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ahmed ni ikọ Amotekun jẹ idunkooko nla mọ isọkan orilẹede Naijira, lasiko to ba bẹrẹ isẹ aabo ẹmi ati dukia lẹkun naa. O fikun pe, wọn se agbekalẹ ikọ Amotekun lati ba okoowo awọn ara oke ọya jẹ ni, ko si tun lee da wọn lọwọ kọ lati se ọrọ aje wọn lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria. Amọ nigba to n fun Ahmed lesi ọrọ rẹ, Sunday Igboho se apejuwe ọrọ yii bii iwa anikanjọpọn ati eyi ti ko boju mu. ""Gbogbo eeyan lo mọ awa Yoruba pe a ko ni mọra, ta si tun ni ifarada nipa awọn ara oke ọya, paapaa lasiko ti wọn ba tọ wa nija. Nitori naa, asisọ ọrọ ni ki eeyan kan ni Amotekun n dunkooko mọ oun tabi jẹ ewu fun aabo ẹmi ati dukia, ọrọ naa ko ye mi."" Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife Igboho tẹsiwaju pe, wọn se agbekalẹ ikọ alaabo ọhun lati daabo bo ẹmi ati dukia nilẹ Yoruba ni lai naani ẹya, ẹsin ti ẹni kọọkan n se. ""Amọ ki eeyan kan wa woye pe agbekalẹ ikọ alaabo Amotekun to wa lati gbe ijọba nigbọnwọ, ni yoo ba ọrọ aje awọn eeyan kan jẹ, jẹ iwa aimọkan ati ọna lati ba erongba rere agbekalẹ ikọ Amotekun jẹ."" Sunday Igboho gba àwọn èèyàn Soka n'Ibadan sílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ọmọ onílẹ̀ tó wá ṣọṣẹ́ Ọrọ di boo lọ, ko yago fun mi ladugbo Soka nilu Ibadan lasiko ti gende meji to gbe ohun ija oloro lọwọ, ti wọn pe ara wọn ni ọmọ onilẹ ya bo agbegbe naa. Owurọ ọjọ Isẹgun ana niroyin gba igboro Ibadan kan, tawọn eeyan si n pe sori redio gbogbo nilu naa pe ẹmi awọn eeyan to n gbe ladugbo naa ko de tori awọn gende agbebọn to ya bo wọn. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: A gbọ pe se ni iro ibọn n dun lakọ-lakọ, tawọn eeyan si n sa asala fun ẹmi lasiko ti awọn ọmọ onilẹ ọhun ni ki awọn onile gbe ile wọn kuro lori ilẹ awọn. Se lawọn ọmọde ati agba, alaboyun ati awọn iyalọmọ, to fi mọ awọn arugbo n sa asala fun ẹmi wọn, ti awọn to si laya lati beere pe ki lo fa isẹlẹ naa, jẹ ajẹkun iya. Ẹnikan ti isẹlẹ naa soju rẹ salaye pe ọpẹlọpẹ asaaju ọmọ Yoruba kan, Oloye Sunday Adeyẹmọ, ti gbogbo eeyan mọ si Sunday Igboho to tete de sadugbo ọhun lasiko ti laasigbo naa gbona janin-jani. A gbọ pe Igboho ati ọkunrin kan ti wọn pe orukọ rẹ Babatunde Arowolo, ti gbogbo eeyan mọ si Bako, lo de lasiko lati gba awọn eeyan adugbo naa silẹ, ni kete ti aawọn ọmọ onilẹ naa si foju gaani rẹ, ni wọn ba juba ehoro. Sunday Igboho, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ salaye pe, lootọ ni oun lọ si adugbo Soka lana lati gba awọn eeyan adugbo naa silẹ lọwọ ijẹgaba awọn ọmọ onilẹ. Sunday Igboho: Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọ̀n bàbá wa O ni ni kete tawọn ọmọ onilẹ foju kan oun ati Bako ni wọn fẹsẹ fẹ, eyi to mu kawọn doola ofo ẹmi ati dukia ti ko ba waye latipasẹ isẹlẹ yii. ""Adugbo Soka nilu Ibadan ni mo n gbe, ti awọn agbegbọn kan si ya wọ adugbo mi lati maa dunkoko mọ awọn eeyan mi, n ko si lee la oju mi silẹ, ki n wa larọwọto, kawọn eeyan kan maa se awọn eeyan mi lese tabi pa wọn ni ipakupa. Osogbo Photographer: Bakan naa ni Igboho ni o ti to ẹẹmẹfa ti awọn ọmọ onilẹ naa ti ya bo awọ̀n eeyan adugbo naa, ti wọn si n yinbọn ti wọn n pa awọn mẹkunnu, ti ọpọ wọn si ti ku lai jale, to si n beere pe se gbogbo mẹkunnu lo ni owo lọwọ lati tun ilẹ ra. Awọn ara adugbo naa ti wa rọ ijọba ipinlẹ Ọyọ lati tete da si ọrọ naa tori kii se igba akọkọ ree ti awọn ọmọ onilẹ yoo wa maa dun mahuru-mahuru mọ wọn lori ilẹ ti wọn ti ra lati ọdun gbọọrọ. Gẹgẹ bi iroyin naa ti wi, nigba ti BBC Yoruba kan si agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpa nipinlẹ Ọyọ, Olugbenga Fadeyi lati gbọ tẹnu rẹ, o ni ka pe oun pada laipẹ.",0,yoruba "jú, àwọn ènìyàn ni ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ẹkọ́: ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó wáyé..",0,yoruba Ìyá ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó ga jù.,0,yoruba Ọmọọ rẹ̀ Al-Salihu tó lọ sí Ṣókótó láti lọ kọ́ nípa ìmọ̀ ẹ̀sìn lọ́dọ̀ Shehu Usman Dan Fodio ló mú ẹ̀sìn ìmàle wá sílẹ̀ Yoòbá. #ItanFulani,0,yoruba "Nítorí COVID-19, ìjọba ìpínlẹ̀ Kwara kó ọ̀dọ́ 50 tó lọ sí ilé ijó sí gbaga Igbimọ amusẹya lori ajakalẹ arun COVID-19 ni ipinlẹ Kwara lo ko wọn si gbaga. Igbimọ naa ni wọn tapa si ofin to de ile ijo lasiko COVID-19 yii ni Atẹjade kan ti igbimọ naa fi sita, eyi ti agbẹnusọ fun gomina ipinlẹ Kwara fi ọwọ si lo yọju ọrọ yii sita. Gẹgẹ bi atẹjade naa ṣe sọ awọn eeyan kan lo sin igbimọ to n ṣe kokaari eto igbogun ti ajakalẹ arun coronavirus ni ipinlẹ naa ni gbẹrẹ ipakọ. Nítorí COVID-19, ìjọba ìpínlẹ̀ Kwara kó ọ̀dọ́ 50 tó lọ sí ilé ijó sí gbaga Eyi lo jẹ ki igbakeji gomina nibẹ fi ọwọ ofin ko awọn awọn ọmọ igbimọ naa sodi lọ sileejo naa. Dokita Ọladiji to jẹ alaga igbimọ igbaninimọran lori arun naa sọ pe o ṣeeṣe ki wọn ran gbe awọn ọdọ naa lọ sile ẹjọ fun titapa si ofin to wa nilẹ pe ẹnikẹni ko gbọdọ ṣi tabi lọ si ile ijo lasiko yii. Black women live matters: Ọdún 2015 ní àwọn ọlọ́pàá pa India Kager láìní ìdí- Gina Best Gbogbo wọn ni wọn si ti ko lọ si ibudo iyasọtọ titi ti esi ayẹwo wọn yoo fi jade Eeyan marundinlaadọrun lajọ NCDC kede pẹlu arun naa ni ipinlẹ Kwara lọjọ Abamẹta",0,yoruba A gbọ́ wípé: Òkè ibi tí a ti ṣẹ̀ wá ni ìtumọ̀ Òkè Ìtaṣẹ̀. #Ife #OdunIfaAgbaye #Orunmila #IfaNewYear,0,yoruba "Iroyin yi lu sita lỌjọbọ pe ọjọgbọn Peter Ogban ti fasiti Uyo yoo fi aṣọ penpe roko ọba nitori yiyi iwe esi idbo . Labẹ ofin INEC ẹwọn ọdun mẹta lo wa fun ẹnikẹni to ba jẹ adari idibo to mọọmọ yi iwe tabi abajade ibo. Ko si owo itanran kankan lori ẹsun yi bi kii ṣe pe ki onitoun ṣẹwọn. Loju opo Twitter awọn eeyan ti n sọrọ lori idajọ yi ti wọn si n beere pe ki wa ni yoo ṣẹlẹ si ẹni to jẹ anfaani wuruwuru ibo yi botilẹ jẹ wi pe ko pada jawe olubori. Die ree ninu ọrọ wọn yi. Lopin igba ti ko ti si ẹri to ṣafihan ilẹdiapopọ laarin Ọjọgbọn naa a ti Ṣẹnẹtọ Akpabio eyi to sunmọ ko ṣẹlẹ ni pe Ọjọgbọn yi yoo da jẹ iya rẹ ni. Ka ni pe makaruru ibo yi gbe Akpabio wọlẹ ni a o ba tiẹ maa sọ pe ki wọn gbe ipo rẹ fun ẹni ti wọn jijọ dije dupo amọ ọrọ ko ri bẹẹ. Ki ni ẹkọ to wa fun wa lori ẹjọ Ọjọgbọn yi nipa oṣelu INEC ki ba maa ba Ọjọgbọn to yiwe idibo fun Akpabio ṣẹjọ ṣugbọn ọjọgbọn yi fun ara rẹ lo ni ki agbẹjọro rẹ kan si INEC pe ki wọn maa ṣe ni koun wa jabọ eto idibo to yi. Oun nikan kan ni INEC pe ti awọn mii ninu wọn naa si kọ lati wa jabọ esi idibo. Abalọ ababọ, INEC pinu lati gbe ọjọgbọn yi lọ si ileẹjọ ti adajọ si pada dajọ ẹwọn oṣu mẹrindinlogoji fun. Ninu gbogbo ohun to ṣẹlẹ yi, o fi n han pe ireti wa fawọn to n beere idajọ to yẹ fun ẹnikẹni toba ṣe makaruru eto idibo.",0,yoruba RT @user: Oluwa loni disco...,0,yoruba "Gómínà ìpínlẹ̀ Rivers, Nyesom Wike ti fèsì sí àwọn awuyewuye tó ń jẹyọ nínú ẹgbẹ́ òṣèlú Peoples Democratic lásìkò àti lẹ́yìn ètò ìdìbò abẹ́nú ẹgbẹ́ náà. Nyesom Wike nígbà tó bá àwọn akọ̀ròyìn sọ̀rọ̀ ní pápákọ̀ òfurufú Rivers lẹ́yìn tó dé láti orílẹ̀ èdè Spain ní irọ ló kún gbogbo ọ̀rọ̀ tí olùdíje sípò Ààrẹ ẹgbẹ́ PDP, Atiku Abubakar ń sọ kiri lórí ayélujára. Ó ní ti àsìkò ọ̀rọ̀ bá ti tó dada òun ma ṣàlàyé bí iṣu ṣe kú àti bí ọ̀bẹ ṣe bẹ́ lórí àwọn ohun tó wáyé nínú ẹgbẹ́ náà lásìkò ètò ìdìbò abẹ́nú náà. Ó ní ó pọn dandan fún òun láti sọ bí ọ̀rọ̀ ṣe jẹ́ gan nítorí tí òun bá kọ̀ láti sọ̀rọ̀, ó ma dàbí wí pé gbogbo irọ́ tí wọ́n ń pa mọ́ òun jẹ́ òótọ́. Wike ní tí stún bá sọ̀rọ̀, ó pọn dandan kí òsì náà wí ti ẹnu ẹ̀ jáde fáyé àti pé ojoojúmọ̀ ni ọjọ́ orí àwọn ń dàgbà si. Ó ní ìdí nìyí tí òun ma fi fès]i sí gbogbo àwọn ẹ̀sùn tí wọ́n ń fi kan òun lórí ìṣẹ̀lẹ̀ náà àti pé ó máa jẹ́ ẹ̀rí jẹ́mi nìṣó wí pé òun sọ ipa òun. Bákan náà ló ní òun pinnu láti dákẹ́ láti ìgbà tí àwọn ti parí ìdìbò abẹ́nú àwọn àmọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú PDP jẹ́ ẹgbẹ́ tí òun ní ìfẹ́ sí. Wike ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìgbà ni àwọn ènìyàn ń bèrè lọ́wọ́ òun wí pé ṣe òun má fi ẹgbẹ́ PDP sílẹ̀. Ó fi kun pé gbogbo àwọn ni àwọn jọ ni ẹgbẹ́ òṣèlú PDP nítorí náà òun kò ṣetán láti fi ẹgbẹ́ náà kalẹ̀ fún ẹnikẹ́ni. Ó ní kí àwọn ènìyàn gbàgbé gbogbo àwọn ariwo tí àwọn ènìyàn Atiku ń pa kiri, òun kò ní ohunkóhun láti bá wọn sọ nítorí ariwo ọjà lásán ni wọ́n. Ó tẹ̀síwájú pé ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ọ̀rọ̀ tí Atiku sọ lórí ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò tó ṣe pẹ̀lú ilé iṣẹ́ ló jẹ́ irọ́ paraku. Wike fi kun wí pé ó ṣeni láàánú wí pé tí òun kò bá sí láyé ni, gbogbo irọ́ náà ni àwọn ènìyàn kò bá máa gbà ní òótọ́. Nígbà tó ń fèsì lórí ọ̀rọ̀ wí pé Atiku ni òun ti ń kàn sí Wike fún ìpẹ̀tùsááwọ̀, ó ní kò dára tó wí pé ẹni tó ń wá ipò Ààrẹ Nàìjíríà ń parọ́ “Àwọn sẹ́nétọ̀ kan pè mí wí pé Atiku ní òun rán Saraki sí òun, àma irọ́ ni” “Mo wà ní Spain, Saraki wá bá mi wí pé báwo la ṣe ma ṣe ọ̀rọ̀ tó wà nílẹ̀ yìí, mo sì bí léèrè wí pé ṣe Atiku ló rán ẹ sí mi, ó ni rárá.” “Mo ní kí ló fẹ́ ki n ṣe, ó ní òun kò mọ̀ wí pé ọ̀rọ̀ náà le tó báyìí, fún ìdí èyí kò lè ní òun rán ẹnikẹ́ni sí mi.” Wike fi kun pé tí òun bá ṣetán òun á sọ gbogbo tẹnu òun láìní bìkítà gbogbo àwọn tí ọ̀rọ̀ náà kàn nítorí òun kìí ṣe ẹrú ẹnikẹ́ni.",0,yoruba ìwájú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò.,0,yoruba Ènìyan ti nilo iyalẹnu fun ìwà tabi alada.,0,yoruba se joko. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó ṣe pàtàkì.,0,yoruba rere. Ọba lo ni ìgbà àkerekere ye ka yè.,0,yoruba "Ó di ọjọ́ kan, ọ̀rẹ́ Òkòló tímọ́tímọ́ fẹ́ gbéyàwó, àwọn ànaa rẹ̀ wá bi í léèrè pé tani ojúlùmọ̀ọ rẹ̀. Leléyun-ùn bá ní Òkòló. #ItanDowe",0,yoruba Èèyàn mẹsan an pàdánù ẹ̀mi wọn nínú ìwọ́de tako Hijab ní Iran,0,yoruba pe jẹ́ pàtàkì wey ti o nuni ti o dun.,0,yoruba "Alàji fè joko, Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba Ọ̀RỌ̀ ỌJỌ́ ÒNÍ / WORD OF THE DAY: GBAJÚMỌ̀ ÌTÚPALẸ̀: Ẹni/ǹkan/ìṣe tí igba ojú mọ̀. TRANSLATION: POPULAR Someone/something/act that 200 faces/people know.,0,yoruba Ó ti ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bí akọ́ni àti olùgbé - lárúgẹ ìdásílẹ̀ àyè ọ̀tọ̀ fún àwọn ará ìlú àti àwọn àkànṣe eto ìgbóhùn sáfẹ́fẹ́ tí kò lọ́wọ́ ìjọ̀ba nínú .,0,yoruba "Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ní kí sẹnẹtọ Ovie Omo-Agege padà sílé Eleyi lo mu ki ile asofin gbẹ́sẹ̀ kúrò lóri òfin tó fi de Omo-Agege, tó lè padà sẹ́nu iṣẹ́ rẹ̀. Alaga igbimọ ile to n ri si ọrọ iroyin ati ipolongo Sẹnẹtọ Sabi Abdullahi, lo sọrọ naa di mimọ l'Abuja lọjọ Iṣẹgun. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: O fi kun ọrọ rẹ pe, ile ko ni di sẹnẹtọ naa lọwọ lati pada s'ẹnu iṣẹ rẹ. Sẹnẹtọ Abdullahi wipe, ile ti ṣetan lati duro de idajọ ileẹjọ ko tẹmilọrun, ki ile to gbe igbesẹ miran.",0,yoruba ri pe nilo ayẹwo wey ti o nuni ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó wáyé.,0,yoruba Central European (_MacCE),0,yoruba "Èwo ni k'á fini joyè #Abobaku tí a ò le è bọ́bakú! Ẹyẹlé ì í bá onílé jẹ, b'ónílé mu kí ó dọjọ́ ikú kó yẹrí. #AbobakuOoni #Yoruba",0,yoruba fun ipilẹ̀ ti o nuni ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Alàji lo ni ẹ̀ká àwẹ eyti o gbe lori àìmọ́ kọ.,0,yoruba "Kòsíná, a gbé ẹ̀rọ fakafìkì sí wájú'lé. Kòsómi a gbẹ́ kànga sí ẹ̀hìnkùlé. Ijọ́wo la ó wa ṣèyí dà? #Ìjọba #ìranù #yoruba",0,yoruba yìí ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìṣẹ̀: ti o nuni ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba Ganase gbà wípé ọ̀ràn náà gba àtúnṣe ní kíákíá .,0,yoruba "Ọgbẹni Tillerson lo ọdun kan pere lẹnu iṣẹ Lẹyẹ o sọka si ni o yan Mike Pompeo to jẹ ọgaagba ileeṣẹ alami ilẹ Amẹrika, CIA lati rọpo rẹ. Aarẹ Trump dupẹ lọwọ ọgbẹni Tillerson fun iṣẹ rẹ lori opo ayelujara Twitter rẹ, o sọ pe akọwe titun yoo ṣe ""iṣẹ ti o tayọ"". Ọgbẹni Rex Tillerson n pada si America lojo isegun Ọgbẹni Tillerson, ti o figbakan jẹ oludari ati alakoso ileeṣẹ ExxonMobil, wa ni ipo fun ọdun kan pere. Aarẹ America naa tun yan Gina Haspel lati di alakoso obinrin akọkọ ọgaagba ileeṣẹ alami ilẹ Amẹrika (CIA). Ọgbẹni Tillerson wa lori isinmi lẹyin abẹwo rẹ si ile Afirika nigbati ko ro wipe ọgbẹni Trump yoo yọ oun nipo, ati wipe Aarẹ Trump gba aba lati ṣe ijiroro pẹlu olori orilẹede North Korea, Kim Jong-un. Aarẹ Buhari ni aarẹ ti Rex Tillerson ṣe ipade pọ pẹlu gẹgẹ bi aṣoju ati akọwe ijọba orilede America. Awọn iroyin miran ti ẹ le nifẹ si:",0,yoruba Atnaf Berhane rántí wípé òún jẹ ìyà oró di aago méjì òru tí òún padà sí lẹ́yìn oorun díẹ̀ .,0,yoruba Àkójú ọ̀rọ̀ yi kún fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde sí ara ilẹ̀. (Item 144),0,yoruba RT @user: @user Emi ti se tan. Sugbon emi month ti awon elemiran.,0,yoruba "E gbayii jare""""""""""""""""@user: Ma je kin ku, kin to ku, ma je kin fi ara gba awe,ma je kin bawo de o do lai pon mi —RT""""""""""""""""@user: Baba ka",0,yoruba "Ọjọ́ Ẹtì. A ò ní wá nǹkan tì, a ò sì ní di àwátì. Àṣetì ò ní jẹ́ ti wa, a ò ní ṣe é tì. #Amin",0,yoruba àkerekere. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó ṣe pàtàkì.,0,yoruba wúlò. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Bàbá lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́.,0,yoruba "Adìẹ tí ò ṣu, tí ò tọ̀, ara rẹ̀ ló wà. #Owe #Yoruba",0,yoruba iṣẹ́ ṣẹlẹ ni Eko ti gbogbo eniyan sọ o dara. (1993),0,yoruba @user Ó mà ṣe o. Ẹ máa báwa sọ̀rọ̀ kí ẹ má fi gbàgbé Yoruba o.,0,yoruba "Àwọn tí ìṣẹ̀lẹ̀ iná náà ṣe ojú rẹ̀ ní ó bẹrẹ ní déédé ago márun un ní Ọjọ́ Eti kí àwọn panapana to dé. Awọn ti ọrọ naa ṣe oju wọn ni wn n sun ina ni ilẹ kan ni agbeegbe naa, ki o to di wi pe ina naa wa bẹrẹ si ni ran. Arabinrin Funmilayo Taiwo ti ina naa ran ile itaja rẹ sọ wi pe oun ati awọn ara agbeegbe lo ja ilekun ile naa lati lọ pa ina naa ki awọn panapana to de. Ni bayii awọn panapana ti dawọ ina naa duro, ti ohun gbogbo si ti pada si ipo. Ti a ko ba gbagbe, ọmọ ọdún márùn-ún àti àgbà mẹ́rin ló bá ìṣẹ̀lẹ̀ ọ̀pá epo bẹntiróò tó gbiná ní Abule Egba lọ láìpẹ́ yìí. Sanwo-Olu pèsè ìpàgọ́ tó wà ní Igando fáwọn tí iná jólé wọn ní Abule Egba láti gbé Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ti paṣẹ ipese eto iranwo fun awọn olugbe agbeegbe ijọba ibilẹ Agbado/Oke Odo nilu Eko, lẹyin ti wọn lugbadi ọpa epo bẹntiroolu to gbina. Ọmọ ọdún márùn-ún àti àgbà mẹ́rin ló bá ìṣẹ̀lẹ̀ ọ̀pá epo bẹntiróò tó gbiná ní Abule Egba lọ láìpẹ́ yìí. Ajọ eleto pajawiri ni ipinlẹ Eko, Lasema ni, gomina Sanwo-Olu gbe igbeṣẹ yii lẹyin ti awọn Alaga ijọba ibilẹ naa ke gbajare si fun ipese eto iranwọ. Lasema ni awọn eniyan ti wọn nilo iranwọ ni agbeegbe naa to ọọdunrun eniyan, ti awọn obinrin ati ọmọde si wa ni ara wọn. Wọn fikun pe Gomina Sanwo-Olu ti buwọ lu ki wọn fun awọn eniyan to lugbadi iṣẹlẹ naa ni ipagọ to wa ni Igando Relief Camp, Igando ni ipinlẹ Eko, ki wọn maa gbe fun igba diẹ na. Ọmọ ọdún márùn-ún àti àgbà mẹ́rin ló bá ìṣẹ̀lẹ̀ ọ̀pá epo bẹntiróò tó gbiná ní Abule Egba lọ láìpẹ́ yìí. Bakan naa ni wọn ṣeleri pe awọn yoo ma a fito awọn ara ilu leti bi o ba ṣe n lọ, lori eto iranwọ fun awọn eniyan agbeegbe naa. Ọmọ ọdún márùn-ún àti àgbà mẹ́rin ló bá ìṣẹ̀lẹ̀ ọ̀pá epo bẹntiróò tó gbiná ní Abule Egba lọ láìpẹ́ yìí. Bakan naa bii eeyan ogun lo fara pa ṣugbọn ti wọn tọju wọn loju ẹsẹ nibi iṣẹlẹ naa. Ile bii mẹfa, ile itaja mẹtadinlogun ati ọkọ akoyanrin mẹtalelọgbọn, ọkọ ayọkẹlẹ mẹta ati kẹkẹ NAPEP alupupu mẹta naa ba iṣẹlẹ naa lọ. Àwọn olùgbé Tarkwa Bay ń fọ́ ọ̀pá epo, jí epo ta, la ṣe lé wọn - Iléeṣẹ́ Ológun Ileesẹ ologun oju omi ti salaye ohun to faa ti wọn fi n fi tipa-tikuuku le awọn olugbe Tarkwa Bay to wa ni erekusu Eko, eyi ti eeyan le gba oju omi nikan wọ ibẹ. Osu Kejila ọdun 2019, paapa lati ọjọ aisun ọdun Keresi ni awọn ologun ti ya bo agbegbe Tarkwa Bay, ti wọn si n le awọn eeyan tipa tikuuku. Nigba to n bawọn akọroyin sọrọ, agbẹnusọ fun ikọ ologun oju omi to lewaju igbesẹ lile awọn eeyan agbegbe ọhun, Ọgagun Thomas Otuji salaye pe, awọn ọpa epo to n gbe epo wa silu Eko ati awọn etikun lo gba agbegbe ọhun kọja eyi ti wọn maa n fọ lojoojumọ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Otuji ni ""Afojusun wa ni lati daabo bo awọn irinsẹ to jẹ ti ajọ elepo rọbi nilẹ wa lọwọ awọn eeyan to n fọ ọpa epo kiri. Wọn ti kọ ile sori awọn ọpa epo naa, ti wọn si n fa epo ta lọna aitọ."" Amọ Otuji ko sai fikun pe bi o tilẹ jẹ pe kii se gbogbo awọn eeyan to n pe ni agbegbe naa lo n ji epo ta, sugbọn ẹni to gbe epo laja ko jale, bi ẹni to gbaa silẹ, nitori ti wọn ko ba tu asiri awọn eeyan to n ji epo fa lọna aitọ ni ayika wọ, gbogbo wọn ni wọn jọ jẹbi. Nibayi naa, awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ lorisirisi lo ti n bu ẹnu atẹ lu igbesẹ tawọn ologun naa gbe ati igbiyanju wọn lati le awọn olugbe erekusu Tarkwa Bay ni erekusu Eko. Ẹgbẹ kan to pe ara rẹ ni Nigerian Slum/Informal Settlement Federation, ninu atẹjade kan to fisita lọjọ Isẹgun oni, koro oju si igbesẹ ijọba lati le ẹgbẹrun mẹwa eeyan to n gbe ni erekusu ọhun pẹlu ipa. Gẹgẹ bo se jẹyọ ni oju opo ikansiraaẹni ẹgbẹ ajafẹtọ ẹni kan, @justempower, jei, ẹgbẹ naa ni ọna ipa ti ijọba apapọ n gba le ogunlọgọ ero kuro ninu ile wọn lai bọwọ fun ofin to yẹ. Iroyin naa ni igbesẹ lile awọn eeyan to wa ni agbegbe Badagry keji pẹlu awọn agbegbe miran to wa ni adugbo Ajegunlẹ lo kọkọ saaju, ti wọn si fi ọba le pẹlu lile awọn olugbe adugbo mẹrinlelogun miran to wa ni erekusu Eko. ""Pẹlu ibanujẹ la fi n wo ijọba apapọ lati ipasẹ ileesẹ ologun oju omi, ti wọn n le awọn eeyan to n gbe ni adugbo Abagbo, Abule Ẹlẹpa, Abule Glass, Ajakoji, Akaraba, Bobukoji, Ebute Oko, Fashola, Idi Mango, Ilajẹ, Inangbe/Ilado, Kopiamy, Ogunfẹmi, Oko-Kate, Okun Alfa, Okun Babakati, Okun gbogba, Okun Ilasẹ, Okun Kobena, Sankin, Sapo Okun ati Tokunbọ, titi de Tarkwa Bay."" ""Ẹnu ya wa nipa awijare ileesẹ ologun lori igbesẹ lile awọn eeyan yii, niwọn igba ti wọn mọ pe ko si ofin kankan lorilẹede Naijiria to fi aaye gba igbesẹ wiwo ile awọn araalu tabi fifi iya jẹ wọn lọna to lodi sofin."" Ẹgbẹ Ajafẹtọẹni naa wa n rọ awọn asaaju wa leti pe awọn ilana aatọ wa nilẹ to jẹ itẹwọgba lawujọ agbaye eyi to de sise amojuto agbegbe kọọkan, ti yoo si tun mu agbega ba idagbasoke aabo ati awujọ. Ìbọn, àfẹ́fẹ́ atajú àti katakata ní àwọn ológun fi lé àwọn olùgbé Tarkwa Bay ní erékùṣù Eko Iroyin kan to gba ori ayelujara kan salaye pe awọn ọmọ ologun ti n fi tipa le awọn eeyan to n gbe ni adugbo Tarkwa Bay nilu Eko. Gẹgẹ bi awọn iroyin to gba oju opo ikansiraẹni Twitter ti wi, awọn ọmọ ologun oju omi, Nigerian Navy lo n le awọn eeyan naa kuro ni agbegbe ọhun to wa ni erekusu ipinlẹ Eko. Iroyin naa ni lati osu kejila ọdun to kọja, paapa lati ọjọ aisun ọdun Keresi ni awọn ologun ti ya bo agbegbe naa, ti wọn si n le awsn eeyan naa tipa tikuuku. A gbọ pe pẹlu ọta ibọn, afẹfẹ tajutaju ati ẹrọ katakata ni wọn fi ni ki awọn olugbe agbegbe ọhun kuro ni ibugbe wọn naa. Iroyin naa fikun pe awọn ọmọ ologun yii lo n yin ibọn soke soju ofurufu, lati fi dẹru ba awọn olugbe erekusu naa, ki wsn lee tete ko aasa wsn kuro lagbegbe naa. Wọn ni wakati kan pere ni wọn fun awsn eeyan to n gbe ni agbegbe ọhun lati ko ẹru wọn, eyi to mu ki ohun gbogbo dojuru. Lọwọlọwọ bayii, o seese ki erekusu Tarkwa Bay, ti ọpọ eeyan maa n lọ lati gbafẹ lee ma si mọ nitori isẹlẹ to waye yii. Ìjọba Èkó yóò ṣètò ààbò àti àtúnṣe Abúlé Ẹgba tí iná jó - Igbákejì gómìnà Igbakeji Gomina ipinlẹ Eko, Obafemi Hamzat ti ṣe abẹwo sawọn adugbo ti o farakasa iṣẹlẹ ijamba ina lagbegbe'Abule Egba ,nilu Eko. Lasiko to n ba awọn ara adugbo kẹdun, Hamzat fi ifarajin ijọba han nipa mimu atunṣe ba agbegbe naa ati pipese aabo to peye. Hamzat to ṣoju fun Gomina ipinlẹ Eko,si wa lara awọn eekan ijọba, to ti ṣe abẹwo si abule Egba lẹyin ijamba ina to ṣakoba fun dukia nibẹ. Ẹwẹ, ọga agba ileeṣẹ to n risi ọrọ epo rọbi ni Naijiria, Mele Kyari, naa ti ṣe abẹwo si Abule Egba ti o si ni ileeṣẹ NNPC ti brẹ si nigbe epo gba inu ọpa to gba Abule Egba kọja . Kyari ninu ọrọ rẹ nibẹ, rọ awọn ara adugbo lati maa ta awọn agbofinro lolobo, bi wọn ba ti ko firi awọn to n bẹ ọpa epo. Bakanna ni o tun ṣe abẹwo si Oba ilu Eko, Akiolu Rilwan nibi to ti beere iranwọ lọdọ awọn lọbalọba nipa mimu aabo to peye ba awọn adugbo to wa labẹ wọn.",0,yoruba owo ṣẹlẹ ni Lagos ti gbogbo eniyan sọ o dara. (2004),0,yoruba "Agba amofin to n duro fun gbajumọ oṣere tiata, Ọlanrewaju James Omiyinka, ti ọpọ mọ si Baba Ijesha, Amofin agba Babatunde Ogala SAN, ti sọ idi to fi n gbẹjọ ro fun Baba Ijesha. Ninu ifọrọwerọ kan pẹlu iwe iroyin The Punch, Amofin Babatunde Ogala ṣalaye pe ko si ohun kan to jẹ koriya fun oun lati duro fun Baba Ijesha ju wi pe wọn fi ẹjọ rẹ lọ oun oun si tẹwọgba. Amọfin agba naa ṣalaye siwaju sii pe niwaju ofin ko si ipo, bakan naa lọrọ si jẹ niwaju oun pẹlu. O ni ofin nikan loun mọ, nigba ti wọn gbe ẹjọ naa tọ oun wa, oun woo daradara ti oun si rii pe awọn ọna kan wa ti a fi lee ti ipasẹ ẹjọ naa mu ilanilọyẹ jade lori ofin. Ni oṣu kẹrin ọdun 2021 ni iroyin jade pe Baba Ijẹsha lọwọ ninu aṣemaṣe kan pẹlu ọmọdebinrin kan. Lẹyin asiko diẹ ni ahamọ ọlọpaa ni wọn gbe lọ si ileẹjọ to si n jẹjọ bayii niwaju Onidajọ Oluwatoyin Taiwo nile ẹjọ giga kan ni ilu Eko. Wọn si ti sun igbẹjọ rẹ si ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu kẹsan ọdun 2021.",0,yoruba "Jó ní ìgbà kan, a ri ọ̀rọ̀ ìlú to ba nìkan.",0,yoruba ènìyàn ni ó pa Ọmọ lo aye àìlẹ̀.,0,yoruba pe ṣe iyalẹnu wey ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ àti ìbi tí wọn wà.,0,yoruba ilera ṣẹlẹ ni Lagos ti gbogbo eniyan sọ o ṣe pataki. (2021),0,yoruba "Igba ẹrun ati ọgbẹlẹ ti de kaakiri orilẹede Naijiria bayii ti ooru si mu pẹlu oju ọjọ to gbona paapaa ni awọn agbegbe ariwa orilẹede Naijiria ati agbegbe Niger Republic. Eleyiii mu ki a bere lọwọ awọn onimọ nipa eto ilera lori ohun ti eniyan le jẹ ati mu lasiko ẹrun, ti gbogbo ibi si gbona. Oju ọjọ gbigbona yii le e fa aisan bii ki o ma a rẹ eniyan lati inu, ki oungbẹ ma a gbẹ eniyan. Ẹ wọ aṣọ fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ láti kojú ooru gbígbóná lásìkò yìí - Dokita Nitori naa, ara nilo omi nigba gbogbo ati agbegbe to tutu, nitori pe ara eniyan ma n padanu omi to le ni mita meji ni ojoojumọ ti eniyan ba n laagun, ti oun mi eemi, to n ṣegbọnsẹ tabi tọ ni ojoojumọ. Omi mimu ṣe pataki ni gbogbo igba, eniyan si gbọdọ ma a mu o kere tan ike omi mẹjọ ni oojọ ati awọn ohun mimu miran. Omi ọsan Lemon: O dara lati ma a mu omi ọsan lemon nitori o ni eroja ara Vitamin C ati B , ti eniyan si lee fi omi si tabi Sugar, bi o ba ṣe fẹ ẹ si. Eso watermelon: Ida marundinlaadọrun eso watermelon lo jẹ omi, ti o si n pa oungbẹ ni kiakia, nitori naa eso to dara lati mu ni lasiko ọgbẹlẹ. Omi agbọn: Omi agbọn naa ṣe pataki fun agọ ara ti o si pọndandan ki eniyan mu u ni asiko ẹrun nitori awọn eroja aṣeraloore to wa ninu ẹ. Ibẹpẹ: O tun pọn dandan naa ki eniyan ma a jẹ ibẹpẹ lasiko ẹrun nitori o ma n jẹ ki ounjẹ ati omi tete da ni inu. Tomatoes: O dara lati jẹ tomato nitori o ni ọpọlọpọ omi ninu, ti eniyan si le jẹ ẹ ni titu tabi ki wọn fikun ounjẹ. Ẹfọ: Ida ọgọrin si aadọrun ẹfọ lo ni omi ninu, to si ma n jẹ ki o tete da ninu eniyan lati ṣe iṣẹ to yẹ ni agọ ara ti eniyan ba ti jẹ tan. Lara awọn ẹfọ naa ni mọringa, lettuce ati bẹẹ bẹẹ lọ.",0,yoruba jíyìn ìròyìn náà .,0,yoruba "Ọba Akanbi, mẹnuba ọrọ yii lasiko to n ba BBC Yoruba lori ohun to gbe re aafin Oyo lati fikunlukun pẹlu Alaafin lọjọ Aje. Ọba alaye naa ni kii se asiko to kan iran Yoruba lati fa oludije fun ipo aarẹ kalẹ, la maa wa lọgun pe a fẹ da orilẹede Oduduwa silẹ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Oluwo ni lootọ oun ko ni oludije kankan lọkan amọ gbogbo ọmọ Yoruba to ba jade pe oun yoo du ipo aarẹ lọdun 2023, ni oun yoo gbaruku ti lati de ipo naa. O fikun pe ki ẹya Yoruba gba ipo aarẹ nikan lo le tan iya to n jẹ wa, agbara si wa ninu ki Yoruba fi ohun sọkan lati gbe eeyan wọn sipo aarẹ. ""Kii se igba ti Yoruba fẹ jẹ aarẹ yii lẹ mọ pariwo orilẹede Oduduwa, ẹ jẹ ka de ibẹ naa, ka si gbaruku ti ọmọ wa to ba dije nitori awa ni ipo naa tọ si, gbogbo nnkan si lo yẹ ka fi wa. Ẹ jẹ ka ni suuru lasiko yii na, amọ ti ọmọ Yoruba ba de ipo, ti ko ba se daadaa, nigba naa la le sọ pe a fẹ maa lọ. Ẹ ma jẹ ki egun kankan tun sẹ lori wa."" Alaafin gba pẹlu mi pe o yẹ ki Naijiria wa ni isọkan lai yapa Nigba to n salaye bi ijiroro rẹ ati Alaafin tilu Oyo se lọ, Oluwo ni oun ati Alaafin ti dijọ panupọ kede pe kawọn eeyan to n polongo fun agbekalẹ orilẹede Oduduwa lọ se mẹdọ na. ""Baba Alaafin ri ọgbọn ninu ohun ti mo sọ, ti wọn si gba pe lootọ lo yẹ ki Naijiria jẹ ọkan, ka si gburuku ti ọna ta fi ni aarẹ ti yoo wa lati ilẹ Yoruba. Alaafin tun sọ fawọn eeyan to n polongo iyapa orilẹede Naijiria lati ni suuru, ki wọn dakẹ, ki wọn ma si polongo orilẹede Oduduwa mọ."" Oluwo ni lootọ ni iya n jẹ iran Yoruba, baa se kawe to, to si dun wa pupọ, a mọ a gbọdọ rọra nitori ta ba n sunkun, o yẹ ka maa riran. Akomolede àti Asa: Ìyàtọ̀ tó wà láàrin ìlànà ìpolówó ọjà láyé àtijọ́ àti òde òní Irẹpọ gbọdọ jọba laarin awọn ọba alaye, ki iran Yoruba si dari jin ara wọn Oluwo, ninu ọrọ rẹ tun ni oun rọ Alaafin pe ko ri daju pe irẹpọ, isọkan ati igbọraẹniye jọba laarin gbogbo oriade to wa nilẹ Yoruba. O ni gbogbo ikunsinu ati aawọ to ti waye sẹyin laarin awọn ọba ilẹ Yoruba ni ki Alaafin pari, ki igba ọtun pẹlu irẹpọ si de saarin wọn. 'Mo tun bẹbẹ pe kawọn ọmọ Yoruba to ba n bara wọn ja gbagbe ija ana, ki wọn mase binu mọ, ki wọn fi ọrọ idasilẹ orilẹede Oduduwa silẹ, ka si wa ni isọkan."" Se atunto lo yẹ ki ẹya Yoruba faramọ ni abi ko yapa? Nigba ti Oluwo n fesi lori ibeere yii, Oluwo ni ohun toun n fẹ ni ka duro ni ọkan amọ ilana pinpin ipo agbara lati oke de isalẹ, ti wọn n pe ni Divolution of power in oun fara mọ. ""Ilana ki awọn gomina wa lagbara ju aarẹ lọ, ti ijọba apapọ ko si ni lagbara ju awọn ijọba ipinlẹ lọ, kawọn ipinlẹ kọọkan naa si ni ileesẹ ọlọpa tiẹ, ni mo fara mọ."" Eyi yatọ patapata si ilana atunto Nigeria ti wọn pe ni Restructuring, amọ ilana pinpin ipo agbara yoo mu adinku ba agbara ijọba apapọ, tawọn ijọba ipinlẹ yoo si lagbara si."" Ẹran dida kaakiri igboro jẹ asa atijọ, ki ijọba fofin de lo tọ Oluwo tilu Iwo wa koro oju si iwa dida ẹran kaakiri eyi to ni o n faa wahala laarin ẹya gbogbo nilẹ yii. Oriade naa ni asa atijọ gbaa, ti ko jẹ itẹwọgba mọ yika agbaye ni asa dida ẹran jẹko kiri, o si yẹ kijọba tete fi ofin de. ""Bi ijọba ba fofin de ẹran dida, awọn agbẹ ati darandaran yoo dinku, ki wọn si tun se idanilẹkọ fawọn darandaran nipa ilana ọsin ẹran laye ode oni. Bí Oduduwa Republic bá bẹ̀rẹ̀, a ò ní ṣe aburú fún àwọn tó takò wá, ìlànà ààtẹ̀lé rèé - Banji Akintoye Gbogbo ẹya lo ni ajinigbe ati apaniyan, kii se iran kan Bakan naa ni Oluwo tun fikun pe gbogbo ẹya ni awọn eeyan to n jinigbe tabi gbe ni pa wa, eyi ko si jẹ idamọ ẹya kan. ""Gbogbo ẹya lo ni ọdaran, ko si yẹ ka maa lọgun pe ẹya kan lo n daran babi jinigbe. Bí ọlọ́pàá ṣe ń tú afurasí Fulani ajínigbé sílẹ̀ ń bà mí nínú jẹ́ - Alaafin Alaafin tilu Oyọ, Ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi Kkta ti yari mọ ileesẹ ọlọpa ilẹ wa lọwọ lori ọwọ to fi n mu awọn ẹsun tawọn eeyan ba fi kan afurasi ọdaran Fulani. Alaafin fi apa janu lori ọrọ yii lasiko to n gbalejo Oluwo tilu Iwo, Oba Abdulrasheed Akanbi ni Aafin rẹ lọjọ Aje. Ọba alaye naa ni ọpọ awọn afurasi Fulani ti ọwọ ba pe wọn n huwa ijinigbe, ti wsn si fa le ọlọpa lọwọ, ni wọn n pada tu silẹ ni ọna to mu aroye lọwọ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Alaafin ni ilana idajọ Naijiria mẹhẹ pupọ, koda ilana naa ko sisẹ mọ rara, bẹẹ si ni ilana isejọba wa ti kuna, paapaa lori ọrọ eto aabo . ""Mo ti bawọn peju si oniruuru ipejọpọ ti wọn ti n jiroro nipa eto aabo, ti mo si dide pe awọn gomina ipinlẹ nija nitori aja ti ko le bunijẹ ni wọn lẹka eto aabo. Bi ọga agba ọlọpa ba pasẹ pe ki wọn tu afurasi kan silẹ, ko si gomina ipinlẹ kankan to lasẹ lati ni ko ri bẹẹ. A ti saayna to pọ lati mu awọn afurasi Fulani ajinigbe, ta si fa wọn le ọlọpaa lọwọ sugbọn ọpọ wọn ni wọn tu silẹ lẹyin o rẹyin, eyi to n mu ki ibanujẹ dori agba wa kodo."" Ẹ má fi òógùn babańlá wa lórí Nàíjíríà jóná torí ìdásílẹ̀ orílẹ̀èdè Oduduwa - Oluwo Oluwo ti Iwo, Ọba Abdulrosheed Adewale Akanbi ti ṣapejuwe ipolongo fun idasilẹ orilẹ-ede Yoruba, gẹgẹ bi nkan to yẹ ki ijọba ati awọn ọba alaye, o mojuto ni kiakia. Lasiko to ṣe abẹwo si Alaafin ilu Ọyọ, Ọba Lamidi Adeyẹmi, ni aafin rẹ, ni Oluwo sọ ọrọ yii. O ni ko yẹ ka fi laalaa awọn baba nla wa to ja fitafita lati sọ Naijiria di ọkan ṣoṣo, jona nitori awọn nkan to ṣe e yanju lai si wahala. Omi iké kan, l'èèyàn kan lè mu f'ọ́jọ́ mẹ́ta láì ro ti ekòló inú rẹ̀ - Ìlú Elega, Kwara Ninu ọrọ tiẹ naa, Ọba Adeyẹmi koro oju si bi awọn daran-daran Fulani kan ṣe n pa awọn ọmọ Yoruba lori ilẹ wọn. O ni o ṣe pataki fun ijọba apapọ lati tete mu ileeṣẹ ọlọpaa kuro ni abẹ idari ijọba apapọ gẹgẹ bo ṣe wa ninu ilana iṣakoso ti Naijiria n lo. Ipade naa waye lasikot i Oluwo sẹ abẹwo si Alaafin ilu Ọyọ Bẹẹ lo si gboriyin fun Oluwo, fun akitiyan rẹ lati mu ki iṣọkan Naijiria duro. Nigba to n tẹsiwaju ninu ọrọ rẹ, Oluwo ti Iwo, Ọba Akanbi rawọ ẹbẹ si awọn ọmọ Yoruba, lati lo ọgbọn ninu ipolongo wọn fun pinpin orilẹ-ede Naijiria. O ni nkan to yẹ ki wọn o ṣe ni pe ki wọn o ṣe atilẹyin fun ọmọ Yoruba lati di aarẹ Naijiria, kii ṣe ki wọn o ma a lu ilu ituka. Onpetu Ijeru: Akala ní torí Aláàfin kò ṣúgbàá òun fún sáà kejì, ló ṣe ní kí pín ipò alága Bakan naa lo bu ẹnu ẹtẹ lu bi awọn kan lara awọn ajijagbara naa ṣe n sọ ọrọ ti ko dara nipa awọn ọba nilẹ Yoruba. Bakan naa lo rọ Alaafin, lati dari igbesẹ ti yoo mu iṣọkan ba igbimọ awọn lọbalọba nilẹ Yoruba.",0,yoruba Ènìyan ti nilo ẹka fun ilera tabi ìbadandun.,0,yoruba "Ara kì í ṣ'òkúta, bí àìlera bá sọ ará oko wò, ewé ni yóò já, egbò ni yó wà, ara rẹ̀ yóò sì padà bọ̀ sípò. Ọ̀fẹ́ nìwòsàn. #owoekoekolongbe",0,yoruba "Ọmọ fè se, Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde sí ara ilẹ̀.",0,yoruba ài: ti o nuni ti o nuni ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba "Awọn olugbe Akute ni, lati igba ti ọwọ ojo ọdun yii ti n le, ni oloko ko ti lee roko mọ, tawọn ko si lee sun tabi wo nitori isẹlẹ ẹkun omi. Lasiko ti BBC Yoruba kan si adugbo naa, a ri pe aloku ẹrọ amu omi di yinyin, taa mọ si ‘Fridge’, ti ko sisẹ mọ, ati ọpọn iwẹ, taa mọ si ‘Bath Tub’, to ti bajẹ́, lawọn kan n lo lati gbe awọn eeyan kọja lori agbara omiyale naa. Iwadi BBC Yoruba fi han pe, aadọta naira si ọgọrun naira ni ẹni kọọkan n na lati fi wọ ọkọ oju omi igbalode naa. Awọn olugbe Akute wa n rawọ ẹbẹ sijọba ipinlẹ Ogun lati tete bawọn wa nkan se si isẹlẹ ẹkun omi naa, eyi to ti n di isẹlẹ ọdọọdun bayii. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:",0,yoruba "Nígbà tí Ìyá fè mú, Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..",0,yoruba ọba. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba ọlọ́run fẹ. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "Police Checkpoint: Wo àwọn ìgbésẹ̀ tí ó lè gbé láti bọ lọ́wọ́ ẹ̀sọ́ ọlọpàá lóju pópó Gẹ́gẹ́ bi àwọn ọlọpàá s sọ ninu àwọn ìkìlọ rẹ̀ ni pe, Rẹ́rìrín músẹ́, wùwà tó tọ́, kí ó si dẹ̀yìn nínú bibá ọlapàá jà. Díẹ̀ lárá àwọn ìmọ̀ràn tí ilé ọlọ́pàá gbé sílẹ̀ rèé gẹ́gẹ́ bi ohun to le mú ki lílọ́ bíbọ̀ rọrun fún àwọn awakọ, pàápàá jùlọ ti àwọn ọlọpàá ba di ọ̀nà ní orilẹ̀-èdè Nàìjíríà. End of Twitter post, 1 Ìdí ti àwọn ọlọpàá ṣe gbe àwọn ọ̀nà àbáyọ yìí kalẹ̀ kò yé ẹnikẹni sùgbọ̀n kò sàì rọ mọ fọ́nràn kan to n jà rainrain lóri ayelujara laipẹ yìí ni bi ti ọlọpàá kan ti ni dandan afi ki onu gba égbẹrun mẹrin naira lọ́wọ́ awakọ kan Ọlọ́pàá tó n gba rìbá sọ pé 'Ọlọ́run gan fara mọ́ olè jíjà' Ní ọ̀pọ̀ ìgbà irú àwọn ǹkan báyìí ti sọ awakọ miran di ero ọrun ní ki ọlọpàá yìbọn pa irú ẹni bẹẹ ti o ba kọ lati san irú owo bẹ́ẹ̀. Nínú àwọn ọ̀nà abayọ ti awọn ọlọpàá fi sita kò si ibi ti wọn tio gba ẹnikẹni nimọràn láti fún ọlọpàá ni rìbá. Ọ̀pọ̀ àwọn alaye míran ti wọn tun ṣe ni pé ó ṣe pataki lati yin ohun rẹdio kalẹ ti o ba ti de ọdọ̀ ọlọpàá.",0,yoruba "Arúgbó tó f'ara sin ìjọba ò rí ẹ̀tọ́ gba tẹ́rùn, àwọn tó wà lẹ́nu iṣẹ́ gan-an alára ò rí owó oṣù Òmìnira 2017 gba. #OmiInira57",0,yoruba ọmọ ò ní gọ̀ gọ̀ gọ̀ kí ó máà mọ orúkọ rẹ̀ èdè ẹni ni ìdánimọ̀ ẹni ọmọ yoòbá ni mí mo sì mọ rírìi èdè abínibí,0,yoruba "@user @user @user @user Kí hò yẹ kí ó máa lọ bẹ́ẹ̀, ó yẹ kí ìtàkùrọ̀sọ àti ìbáṣepọ̀ tí ó dán mọ́rán ó wà ní àárín òǹtà àti òǹrajà fún ìtẹ̀síwájú okòwò. #EtoOnibaara #consumerright #brandnegligence #LiveYourBestLife @user @user",0,yoruba fẹjú toto wá a wà á sì rí i ṣà máà fẹjú toto wà á o ò sì ní rí i,0,yoruba RT @user: Àjùmọ̀bí ò kan t'àánú; ẹni orí rán sí'ni ló ńṣe'ni lóore. / Blood ties do not guarantee merciful support; help comes o…,0,yoruba àṣà ìdílé. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "Ẹrú ń bẹ, ìwọ̀fà sì wà, àmọ́ bí ìwọ̀fà bá san ọ̀fà rẹ̀ tán ó di òminira. Bẹ́ẹ̀ l'ó rí tẹ́lẹ̀. #nigbatiwonde",0,yoruba Adeboye: Ọlọ́run kò tíì bá mi sọ̀rọ̀ nípa ètò ìdìbò ọdún 2023,0,yoruba lòdì Ìjẹ̀. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ẹkọ́: ti o pẹ jú nìlọ̀ ni ọ̀nà tí ẹ̀ọ́ kan máa.,0,yoruba Ìgbìmọ̀ ìgbẹ́jọ́ ìdìbò ààrẹ kọ ẹ̀bẹ̀ ẹgbẹ́ PDP láti yẹ ojú òpó ayélujára INEC wò,0,yoruba Lọ sókè ní ìpele kan,0,yoruba @user Kí làá wa ṣe nipa àwọn jàgídí-jàgan wọ̀nyí? Wọ́n ti tún ju àdó olóró láti kó jàmbá nlá bá ará ìlú! #boko haram #yoruba,0,yoruba "àṣà ni ìwájú lojiji. Bàbá lo tun se fi. Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba Amọṣa oniruuru ipenija ni wọn n koju ti ọpọ ẹmi si ti ṣofo pẹlu. Oniruuru iriri lawọn ọdọ wọnyii n ri koda ọpọ ninu wọn lo ti ba awọn oniroyin sọrọ lori awọn ohun ti wọn n ba pade nibẹ.,0,yoruba "yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba àìkú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ẹkọ́: ti o lẹ.,0,yoruba njẹ́ a júbà ọlọ́run ọba àkọ́dá aiyé aṣẹ̀dá ọ̀run,0,yoruba òro ìwúrí opin ose abuja fct,0,yoruba tèmi. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ìyá lo tun se joko.,0,yoruba kọ. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa aráyé: ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa aráyé:.,0,yoruba àkóbì asin. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó ṣe pàtàkì.,0,yoruba "ojú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Nitori eyi, ara eni ni nfàn ojú kakaaki.",0,yoruba nípa ìbadandun. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.,0,yoruba È é ṣe tí ìwà ìṣowóòlú-mọ́kumọ̀ku fi j'ọba loókan ààyà wa nílẹ̀ yìí àti níbòmìíràn nílẹ̀ adú? #OminiraNigeria #NigeriaAt56,0,yoruba "ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa aráyé: ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.",0,yoruba mòní nípa ìgbà àkerekere lo je gbogbo ise ibile tèmi.,0,yoruba "àìlẹ̀, Ìyá ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba Píríǹtì ojú-ìwé lọ́wọ́lọ́wọ́,0,yoruba "Ọkan ninu wọn ti a ri ni isọ ti wọn ti n ta alubọsa ṣe alaye wi pe ọwọngogo nnkan ti oun ta tẹlẹ lo sun oun de idi alubọsa nitori ọna atijẹ.Awọn ontaja naa fi kun ọrọ wọn wi pe gbogbo awọn ẹya Yoruba ati Hausa to fi ibẹru sa kuro ninu ọja naa ti n pada wa na ọja bayii, botilẹ jẹ wi pe ibẹru diẹ diẹ ṣi wa lọkan wọn.Bakan naa ni awọn ọkọ nla to n ko ọja bi i ata, alubọsa ati bẹẹ bẹẹ lọ lati Ariwa orilẹede yii ti pada sẹnu iṣẹ wọn. Awọn onibara lati ipinlẹ Ọyọ, Ogun ati awọn ipinlẹ mi i naa ko gbẹyin ninu ọja Ṣaṣa lasiko ti a ṣe abẹwo sibẹ.Awọn ontaja naa parọwa si ijọba lati mu ileri ṣẹ fun imubọsipo ọja naa. Ita gbangba ni gbogbo awọn ti a ba ninu ọja naa ti n ṣe karakata wọn bayii nitori pupọ ninu awọn ṣọọbu ti wọn n lo tẹlẹ lo ti jona ninu rogbodiyan to ṣẹlẹ lọja naa.Awọn onikarakata kan ti o jẹ Hausa naa fi idi ọrọ mulẹ wi pe ọja ti ṣi lootọ ṣugbọn awọn ko ti i le sọ bi ọja ṣe ri nitori pe oni ni ọjọ keji ti ọja naa di ṣiṣi pada. Awọn to kọja nnkan ti wọn n ta lọ si ọja Bodija naa ti n pada si ọja Ṣaṣa ti wọn ti n ta ọja wọn tẹlẹ. Ṣaaju ni Gomina Ṣeyi Makinde ṣe ileri wi pe ijọba ipinlẹ Ọyọ fi ọkọ itulẹ, Budosa ṣọwọ si ọja naa lati wo gbogbo awọn ṣọọbu to jọna palẹ ninu ọja naa.A ri apẹrẹ wi pe iṣẹ naa ti bẹrẹ lasiko ti a ṣe abẹwo sibẹ. Gómìnà ìpínlẹ̀ Oyo Ṣeyi Makinde ti pàṣẹ pe ki ọjà Ṣaṣa di ṣíṣí padà Gomina ipinlẹ Ọyọ Ṣeyi Makinde ti paṣẹ wi pe ki wọn ṣi ọja Ṣaṣa pada lẹyin ọsẹ melo kan ti wọn ti ọja naa pa.Makinde kede ọrọ yii lọjọ Iṣẹgun nibi ipade ti o ṣe ni gbọgan nla igbalejo ""House of Chiefs"" to n bẹ ni Agodi, ilu Ibadan pẹlu igun mejeeji ti o n ba ara wọn ja ninu ọja naa.Gomina ṣe alaye wi pe nitori eto ọrọ aje ati awọn nnkan mii to niṣe pẹlu ipinlẹ yii ni oun ṣe gbe igbesẹ naa. O ni, ""Ti a ba wo eto ọrọ aje ati bi nnkan ṣe ri fun wa, mo ti gbọ nnkan ti ẹ sọ, lẹsẹkẹsẹ si ni a o ṣi ọja naa pada. Wọn yoo gbe awọn ẹrọ itulẹ lọ si ọja naa lonii"".Makinde tẹsiwaju wi pe, ""Lasiko ti emi ati awọn arakunrin mi ti o jẹ Gomina ṣe abẹwo si aafin Seriki Ṣaṣa, nigba ti a n rin kaakiri mo ṣe akiyesi wi pe awọn eeyan ti a ri nibẹ ati awọn eeyan ti a pade ni ọdọ Baalẹ ni inu wọn ko dun nitori pe ọna ati jẹ ti di mọ wọn"".""Ti ẹ ba wo ipinlẹ Ọyọ kodaa gan nigba ti aarun Corona de gongo, mo kọ lati ti awọn ọja wa nitori mo mọ pe nnkan ti pupọ eeyan ba ri lonii ni yoo sọ boya wọn a ri ounẹ jẹ lọla"".",0,yoruba "N jẹ ẹ mọ pe gomina ti yoo se ibura lọjọru ni ipinlẹ Ọyọ, Onimọ ẹrọ Seyi Makinde ti kan si papa iṣere Obafemi Awolowo nibi ti ayẹyẹ ibura naa yoo ti waye. Lasiko to si wa ni ibudo naa, lo se idanilẹkọ nipa bi eto igbaradi naa yoo se waye. Koda, o tun wọ inu ọkọ ti yoo gbe kaakiri wo . Koda, Awọn ase ibudo lọṣọ atawọn ohun eelo ikọrin gan ti wa nikalẹ fun ayẹyẹ ibura naa. Igbaradi ni pẹrẹwu! Seyi Makinde n gbaradi fun ayẹyẹ ibura rẹ Awọn ara ipinlẹ Ọyọ ti ni gomina tuntun Makinde n yan fanda lori papa saaju ọjọ iburawọle Papa isere idaraya Obafemi Awolowo gbe awọ tuntun wọ fun ayẹyẹ ibura Seyi Makinde Atibaba ree fun awọn alejo, o lee daboo bo awọn ero lọwọ ojo ati oorun Papa isere Obafemi Awolowo ti yatọ gbaa fun ibura Seyi Makinde Pẹpẹyẹ yoopọn ọmọ nibi ibura Seyi Makinde lọla. Kekere kọ Ipinlẹ́ Ogun: Gbogbo eto lo ti to bayii ni papa isere idaraya MKO Abiola nilu Abẹokuta fun ayẹyẹ ibura gomina ti ilu dibo yan ni ipinlẹ Ogun, Ọmọọba Dapọ Abiọdun. Akọroyin BBC Yoruba to ti balẹ silu Abẹokuta fi awọn aworan ransẹ nipa ibi ti igbaradi naa de duro. Gbogbo eto ti to saaju ibuwarawọle fun gomina nipinlẹ Ogun Dapo Abiodun ati Noimot Salaki Oyedele ni wọn yoo ma a bura fun gẹgẹ bi gomina ati igbakeji rẹ. Awọn ohun elo orin lọlọkan o jọkan ko gbẹyin nibi igbaradi naa. Awọn asofin ipinlẹ Ogun naa wa lara awọn ti wọn yoo ma burawọle fun ni Ọjọru Ipinlẹ Kwara: Bi o tilẹ jẹ pe awọn ipinlẹ kan ko mu ayẹyẹ ibura awọn gomina tuntun ni kekere, ti wọn si fẹ ṣe ayẹyẹ ibura naa tilu-tifọn, amọ eyi ko ri bẹẹ rara ni ipinlẹ Kwara. Idi ni pe wọọrọwọ ni wọn fẹ se ibura gomina ti ilu dibo yan, Abdulrahman Abdulrazak ti ipinlẹ Kwara, ti ayẹyẹ naa ko si ni kọja ile ijọba ipinlẹ naa. Akọroyin BBC Yoruba to ti kalẹ silu Ilọrin fi ye wa pe, ko si pọpọsinsin kankan to n waye nipa ibura naa. Gbunkẹlẹ ni ayẹyẹ iburawọle ni ipinlẹ Kwara yoo jẹ lọla pẹlu bi ohun gbogbo se dakẹ rọrọ Awọn o sisẹ naa n gbaradi fun ọla Akojọpọ aworan naa wa lati BBC",0,yoruba Omoluabi wa ni ara eni lo ni ẹ̀ká àwẹ eyti o gbe lori iwa rere.,0,yoruba àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìṣẹ̀: ti o ṣe pataki.,0,yoruba "Ọjọ kinni, oṣu Kẹwaa, ọdun 2020 ni wọn ṣe ifilọlẹ eto naa fun ipele tuntun yii. Gẹgẹ bi ikede ti awọn alamojuto eto naa fi sita, iranwọ naa wa fun awọn olokoowo adana kekeeke jakejado Naijiria, lati tu wọn lara fun owo ti wọn padanu nitori itankalẹ aarun coronavirus ni lara ọrọ aje wọn ku. Eto naa ti bẹrẹ fun awọn olokoowo ni ẹka eto ẹkọ, irinajo afẹ, ati awọn miran, ni ọjọ kọkanlelogun, oṣu Kẹsan, ọdun 2020, yoo si pari ni ọjọ kẹkdogun, oṣu Kẹwaa. Fun awọn oniṣẹ ọwọ ati awọn ọlọkọ eero, ẹgbẹrun mẹtalelaadoje (333,000) ni yoo jẹ anfaani lara owo ti ijọba fẹ ẹ fun wọn. Ẹgbẹrun lọna ọgbọn Naira ni ijọba yoo fun ẹni kọọkan wọn. Wo bi iforukọsilẹ yoo ṣe lọ Awọn alamojuto eto naa sọ pe isọri mẹta ni wọn yoo pin awọn oniṣẹ ọwọ ati ọlọkọ eero naa si. Awọn to wa ni isọri kinni yoo ṣe iforukọsilẹ ni ọjọ kinni, oṣu Kẹwaa si ọjọ kẹẹdogun, oṣu Kẹwaa. Awọn ipinlẹ to si wa ni isọri kinni ni: •Abuja •Lagos •Kaduna •Ogun •Kano •Anambra •Borno •Bauchi •Abia •Rivers •Plateau •Delta Ipinlẹ mejila ni yoo kopa ni isọri keji. Wọn o si bẹrẹ eto ti wọn ni ọjọ kọkandinlogun, oṣu Kẹwaa, si ọjọ kọkanlelọgbọn, oṣu Kẹwaa. Ọjọ kẹsan, oṣu Kọkanla si ọjọ kọkanlelogun, oṣu Kọkanla, ni isọri kẹta yoo kan ipinlẹ mẹtala to ku. Wo awọn ilana ti wa a tẹle lati kopa O gbọdọ jẹ olokoowo kekere (to ni oṣiṣẹ) tabi oniṣẹ adani Ida marunlelogoji (45%) awọn ti yoo jẹ anfaani eto naa ni yoo jẹ obinrin, ida marun yoo si jẹ awọn akanda ẹda. To ba jẹ ileeṣẹ, o gbọdọ ti fi orukọ silẹ lọdọ ajọ to n mojuto ọrọ awọn ileeṣẹ, Corporate Affairs Commission; o gbọdọ ni to oṣiṣẹ mẹta; bakan naa ni ọga ilẹẹṣẹ naa gbọdọ jẹ ọmọ Naijiria, to ni nọmba BVN. Fun awọn oniṣẹ adani, awọn awakọ bọọsi, awakọ takisi, to fi mọ awọn takisi igbalode bi i Uber ati Bolt, ati awọn mọkaliiki. Awọn oniṣẹ ọwọ bi birikila, jorin-jorin, ati bẹẹbẹẹ lọ, ni eto naa kan.",0,yoruba "jú, àwọn ènìyàn ni ó pa Ọba lo ìgbà ọkọ.",0,yoruba ayẹwo wey ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba "Onírúurú àrà ni àwọn olólùfẹ́ eré ìdárayá máa ń dá tí ọ̀rọ̀ bá di ti ẹni tí wọ́n ń fẹ́ràn pàápàá lágbo eré bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá. Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ni kò kí ń lè pa ìdúnnú wọn mọ́ra nígbà tí ọ̀rọ̀ eré bọ́ọ̀lù bá dá lórí agbábọ́ọ̀lù tí wọ́n bá  fẹ́ràn jùlọ. Bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ lọ̀rọ̀ rí ní ìpínlẹ̀ Kerala, níbi tí àwọn olólùfẹ́ eré bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá pọ̀ sí jùlọ ní orílẹ̀ èdè India. Ní India, eré ìdárayá Cricket ló gbajúmọ̀ jùlọ, tí àwọn ibẹ̀ sì máa ń ṣe àtìlẹyìn fún àmọ́ àrà ọ̀tọ̀ ni ìfẹ́ tí àwọn ará ìpínlẹ̀ yìí ní sí eré bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá. Ní ọjọ́ Àìkú, ọjọ́ Kejìdínlógún, oṣù Kejìlá, ọdún 2022 tí àṣekágbá ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ìdíje ife ẹ̀yẹ àgbáyé wáyé láàárín orílẹ̀ èdè Argentina àti France, àwọn ará ìpínlẹ̀ náà gbáradì láti wo ìdíje náà dáradára. Àmọ́ ohun kan tó jẹ́ àrà ọ̀tọ̀ ni tí àwọn tọkọtaya kan tí wọ́n ṣe ìgbéyàwó ní ọjọ́ àṣekágbá ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ìdíje ife ẹ̀yẹ àgbáyé yìí. Bí ìmọ̀ àwọn tọkọtaya náà ṣe jọ lórí gbogbo nǹkan tí wọ́n máa lò ní ọjọ́ ìgbéyàwó wọn, ó dàbí wí pé ẹnu wọn kò kò lórí orílẹ̀ èdè tí wọ́n jọ máa ṣe àtìlẹyìn fún. Sachin R tó jẹ́ ọkọ ìyàwó ló jẹ́ alátìlẹyìn Messi ti orílẹ̀ èdè Argentina nígbà tí ìyàwó rẹ̀ sì ń ṣe àtìlẹyìn fún orílẹ̀ èdè France láti gbégbá orókè níbi ìdíje náà. Èyí ló mú àwọn tọkọtaya náà wọ “jẹsí” lórí aṣọ tí wọ́n fi ṣe ìgbéyàwó wọn níbi ayẹyẹ ìgbéyàwó náà tó wáyé ní ìlú Kochi láti fi ìfẹ́ wọn sí eré ìdárayá náà hàn. Athira tó jẹ́ ìyàwó wọ “jẹsí Mbappe láti fi ìfẹ́ rẹ̀ sí France hàn nígbà tí ọkọ rẹ̀ Sachin wọ “jẹsí” Messi láti ṣàtìlẹyìn fún Argentina. Ìwé ìròyìn Malayala Manorama jábọ̀ pé ní kíákíá ni àwọn tọkọtaya náà kúrò níbi tí wẹ̀jẹwẹ̀mu ayẹyẹ ìgbéyàwó wọn ti ń wáyé láti lọ wó àṣekágbá eré bọ́ọ̀lù náà. Ìpínlẹ̀ Kerala gẹ́gẹ́ bí ìròyìn ṣe sọ ni ayẹyẹ lọ́kan-ò-jọ̀kan ṣì ń wáyé níbẹ̀ nítorí Messi ni ọ̀pọ̀lọpọ̀ wọn ń ṣe àtìlẹyìn fún.",0,yoruba "Ni ọjọ Aje ni ileeṣẹ BBC News Yoruba gbe iroyin nipa ileewosan nla UCH nibi ti iwe akọranṣẹ labẹle kan ti lu sita . Aṣẹ inu lẹta naa lo ni pe awọn alaṣẹ ileewosan naa fé ki awọn aláìsàn tó bá wà ní ilé ìwòsàn náà óò máa san ẹgbẹ̀rún kan náírà ní ojoojúmọ́ gẹ́gẹ́ bí owó iná. Iroyin to n tẹ BBC News Yoruba lọwọ bayii n sọ pe eeyan kan to ri apinka iroyin naa to lu ori ayelujara pa lanaa ni eyi ti wọn fi ranṣẹ sii lati ilẹ okeere ti gbe owo kalẹ fun rira ẹgbẹrun kan lita epo disu lati fi tan ina ni ileewosan nla naa. Alukoro ileewosan nla UCH, Ogbeni Toye Akinrinọla ṣalaye fun BBC News Yoruba pe ẹlẹyinju aanu kan ti orukọ rẹ n jẹ Họnọrebu Lanre Laoshe se eto aanu naa. O ni pe Laoshe lo pe ileewosan naa to si sọ fun wọn pe oun mọ ipenija ti irufẹ ileewosan nla bii ti UCH lee maa dojukọ laarin bi nnkan ṣe n lọ kaakiri bayii. O ni Họnọrebu Laoshe lo wa gbe owo kalẹ pe ki wọn fi ra ẹgbẹrun kan lita disu fun elo ileewosan nla naa. Ninu atẹjade kan ti awọn alaṣẹ ileewosan nla UCH nilu Ibadan fi sita,  dokita agba nibẹ  Ọjọgbọn Jesse Abiọdun Ọtẹgbayọ kan sara si ẹlẹyinju aanu naa. O pe orukọ rẹ ni Họnọrebu Lanre Laoshe lati ilu Eko fun itọrẹ aanu lati ran ileewosan nla naa lọwọ. Gẹgẹ bi ohun ti Ọjọgbọn Ọtẹgbayọ kọ, Họnọrebu Laoshe sọ pe: “Mo wa ninu ẹgbẹ ikanni ori 'Whatsapp' kan nibi ti iroyin kan ti jade lori ile iwosan UCH pe awọn alaisan yoo maa san ẹgbẹrun kan Naira owo ina. ""Mo kaanu gidi fun ileewosan UCH nitori pe  mo woo pe ki wọn to le fọkan pọ sori igbesẹ bẹẹ a jẹ wi pe nnkan ti kọja ẹmi wọn ni. ""Mo sọ fun awọn akẹgbẹ mi lori ikanni naa pe dipo bibu ẹnu atẹ lu ileewosan UCH, o yẹ ki a wa ọna lati ran ileewosan naa lọwọ ni. Honorebu naa ni pe: “Ogo orilẹ-ede Naijiria ni UCH, Ogo ajumọni gbogbo wa ni ileewosan nla UCH jẹ. Eyi ni mo fi pinnu lati gbe disu ẹgbẹrun lita kan silẹ gẹgẹ bi iwọnba igbesẹ majẹ ko bajẹ temi lati koju ipenija ipese ina mọnamọna ni ileewosan naa.” Ọjọgbọ̀n Ọtẹgbayọ ni ki agogo marun un irọlẹ ọjọ Aje to lu ni epo disu ti Họnọrebu Laoshe ṣeleri ti de ikawọ awọn alaṣẹ ileewosan naa. Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ, alukoro ileewosan nla UCH, Ọgbẹni Akinrinọla ṣalaye pe nigba ti wahala ipese ina fẹ pin ileewosan naa lẹmi lawọn alaṣẹ ileewosan naa fi gbe ipade dide nibi ti aba orisiirisii ti jẹyọ lori ọna ati wa ojuutu si iṣoro ipese ina. Awọn miran n gbamoran orisii bii eyi fun awon alase UCH lati fi wa ojutu si isoro naa: 1.       Mimu ki awọn alaisan to wa nibẹ o san ẹgbẹrun kan Nairia owo ina 2.       Lilọ kaakiri ori ayelujara lati sọ nipa iṣoro yii fun awọn oninudidun ọlọrẹ ti o ba lee ṣe ileewosan naa laanu 3.       Tabi fifi ẹgbẹrun kan owo ina sisan naa sori iye owo ti olukuluku awọn alaisan to ba wa sileewosan naa yoo maa san, ṣugbọn wọn ko ni jẹ ki wọn mọ. Pelu ọpọ imoran mii lo n jade bayii Bakan naa ni ọpọ eeyan n sọrọ si ijọba Naijiria lori pe abuku ijọba to wa lori aleefa ni pe ileewosan Fasiti akọkọ ni Naijiria ko ri owo fi pese ina Oba fun alaisan lasiko yii. Awọn miran tun sọrọ si awọn alaṣẹ pe ajẹbanu wọn ti pọju ninu awon oloselu orilẹede yii. Amọṣa, ko tii si eyikeyi ninu awọn alaisan to wa nileewosan naa to tii san owo naa titi di bi a ṣe n sọrọ yii. Ni kete ti iroyin naa jade lọjọ Aje ni awọn ọmọ Naijiria ti n ba ileewosan naa ṣi iye ti owo naa yoo maa ja si fun wọn lojumọ. Bi awọn kan ṣe n sọ pe iye awọn alaisan to n wọ ileewosan naa lojumọ ko din ni ẹgbẹrun lọna ogun lawọn kan n sọ pe yoo to biliọnu kan naira ti wọn yoo maa ri rejọ lori owo epo disu naa. Amọṣa, nigba ti BBC News Yoruba gbọ ọrọ lẹnu alukoro ileewosan naa, o ni gbogbo aye bẹẹdi to wa lati gba alaisan si ni ileewosan naa ko ju ẹgbẹrun kan o le igba lọ (1, 200). O ṣalaye pe ko si ileewosan kankan lagbaye to le e ni aaye lati gba alaisan ẹgbẹrun lọna ogun lojumọ. O fi kun un pe gbogbo ohun to ṣokunfa wahala yii ko ju bi ileeṣẹ apinna ọba IBEDC ṣe n kuna lati pese ina fun ileewosan naa bi o ti tọ ati bi o ti yẹ. O fi kun un pe nnkan bii aadọta si adoorin rin miliọnu lawọn alaṣẹ ileewosan naa nsan loṣu fun ina ọba ti wọn si tun maa n na bii ogun miliọnu miran lati fi ra epo disu si ẹrọ amunawa gbogbo ti wọn n lo nibẹ. Àwọn aláṣẹ ilé ìwòsàn University College Hospital, UCH, Ibadan, ìpínlẹ̀ Oyo ti ní àwọn aláìsàn tó bá wà ní ilé ìwòsàn náà yóò máa san ẹgbẹ̀rún kan náírà ní ojoojúmọ́ gẹ́gẹ́ bí owó iná. Wọ́n ní èyí jẹ́ láti mú àdínkù bá ìpèníjà tí ilé ìwòsàn náà ń kojú lórí sísan owó iná ọba àti ríra dísù sínú gẹnẹrétọ̀ tí wọ́n fi ń tan iná ní ilé ìwòsàn náà. Nínú ìwé àkọránṣẹ́ lábẹ́lé lọ́jọ́ Kọkànlélógún, oṣù Kẹfà, ọdún 2022 ní owó tó ń lé owó iná ọba àti bí dísù ṣe ń fi ojoojúmọ́ gbẹ́nu sókè si ló mú àwọn pinnu láti ní kí àwọn aláìsàn máa san owó iná tí wọ́n bá lò. Ìwé náà tí alákoso ilé ìwòsàn náà, Wole Oyeyemi buwọ́lu lórúkọ gíwà àgbà ilé ìwòsàn ọ̀hún ní ìgbésẹ̀ yìí yóò jẹ́ kí àwọn le pèsè ìwòsàn tó péye fún àwọn aláìsàn. Bákan náà ló ní àwọn ti buwọ́lu ìpinnu nìyí.",0,yoruba oke talagbara gun tomi hele oun lomo lorun gun to tun pada wa dupegbogbo oke isoro to wa niwaju wa nio di petele,0,yoruba "ojú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba "Moyinoluwa ẹni ọdun mẹrindinlọgbọn ṣalaye pe, niwọn igba ti oun si wa lori itẹ baba oun, aṣa ati iṣe ilu Ibulesoro ko gba oun laaye lati lọkọ tabi ṣe abiyamọ. Amọ, Moyinoluwa sọ pe oun si n foju sọna lati ṣe iyawo alarede, ni kete ti oun ba ti pari iṣẹ oun gẹgẹ bi Adele, ti ọba miiran si gori itẹ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Adele Ọba Ibulesoro ni, ipo oun ko jẹ iyalẹnu fun afeṣọna oun nitori oun ti ṣalaye fun tẹlẹ pe, oye Adele le yi kan oun ti baba oun ba papoda. Moyinoluwa fikun ọrọ rẹ pe, oun ko gbọdọ gbe ohunkohun le ori oun tabi ki oun ṣi ori ṣilẹ, koda oun ko gbọdọ kunlẹ niwaju ẹnikankan mọ, niwọn igba t'oun wa lori oye gẹgẹ bi adele. Adele Oba Falowo ni oye naa ti jẹ ki oun mọ ọpọlọpọ nnkan ti oun ko mọ tẹlẹ, nipa aṣa ati iṣe ilẹ Yoruba. O ni wiwọ aṣọ ọkunrin ko jẹ nnkan to jọju f'oun nitori ohun to wa ninu aṣa ni wi pe, ọkunrin ni adele tabi ọba to wa lori tẹ gbọdọ jẹẹ. Amọ, Moyinoluwa sọ pe, bi awọn agbalagba ṣe maa n kunlẹ tabi dọbalẹ fun oun kọkọ ri bakan lara oun, nigba ti oun ṣẹṣẹ jẹ oye naa. Ṣugbọn bayii, o ni tayọ tayọ loun maa fi n ki awọn to ba n ki oun nitori oun mọ pe, ori ade ni wọn n bọwọ fun un, kii ṣe oun gẹgẹ bi ẹnikan. The Polytechnic Ibadan: Ẹ̀rọ abẹ́lé tó ń fọ ọwọ́ àti ‘Ventilator’ ló ṣẹ̀ṣẹ̀ gbé jáde Adele Falowo tun sọ pe, ni ọpọ igba lawọn ojuṣe kan gẹgẹ bi Adele maa n tako igbagbọ oun gẹgẹ bi onigbagbọ ati ọmọlẹyin Kristi. Amọ, o ni oun maa n yanju rẹ ni itubi inubi pẹlu awọn agbaagba oloye afọbajẹ laisi ikunsinu kankan. Adele Ọba Ibulesoro ṣalaye pe, sisọ aṣa nu lo n ṣe okunfa iwa ifipabanilopọ to n gogo sii ni Naijiria bayii. Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo O ni ti aṣa ba ti sọnu, yoo jẹ ki rukerudo atawọn iwa ibajẹ maa pọ si lawujọ wa.",0,yoruba Àwọn ènìyàn ti gba gbe wey o dara.,0,yoruba ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba "Lọjọ Abamẹta, ọjọ kẹrinlọgbọn, oṣu Kẹsan, ọdun 2020 ni Olori fi oriṣiriṣii fọto rẹ ati ti Alaafin pẹlu pẹlu ọmọ ti Eleduwa fi jinki wọn si oju opo Instagram rẹ. Lẹyin naa, ọpọ eeyan bẹrẹ si ni beere wi pe ki ni Olori n ṣe gan an? Amọ, ninu ohun to kọ sori awọn to fi sori awọn fọto, Olori Abbey kọkọ gboṣuba rabandẹ fun Eleduwa fun ore-ọfe to fun oun. O dupẹ fun Ọlọrun fun ọpọlọpọ ibukun to fi fun oun lati igba ti oun ti wa loke eepẹ. Lẹyin naa lo bẹrẹ si ni dupẹ ni mẹsan an mẹwaa lọwọ olowo-ori rẹ, Alaafin Oyo. Olori Abbey ni oun ko le ṣalai dupẹ lọwọ Iku Baba Yeye fun ifẹ ti ko ṣe fẹnu sọ to ni si oun, fun ọrọ ti oun n jẹ anfaani rẹ ati fun idunnu ati ayọ to n ri lara Oba Adeyemi. ''Kabiesi, lai si iranwọ yin ati ifẹ ti ko lẹgbẹ ti ẹ fihan si mi, ko ba ti si ẹni to n jẹ emi,'' Olori Abbey lo sọ bẹẹ. O ni lai si ore-ọfẹ ti oun n ri jẹ lara Alaafin ni, oun ko le di iru obinrin t'oun da lonii. Olori Abbey ni ọpẹ oloore, adaadatan ni, o ni lailai l'oun yoo maa dupẹ lọwọ Ọba Lamidi Adeyemi. Ni ipari ọrọ rẹ ni Olori Abbey ki ara rẹ ku ayẹyẹ ọjọ ibi, o gbadura pe ki Eleduwa fi ẹmi gigun ati ayọ jinki oun.",0,yoruba @user Èkó kẹ̀? Ẹ ò rí bí iná ṣe tàn sílẹ̀ ni? :),0,yoruba "Ní igba mi owó àkokò, Baàlè ri A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà. ti Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..",0,yoruba yìí ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba 10. Orúkọ-àmútọ̀runwá wo ni à ń pe ọmọ tuntun tí ó fi àwọ̀n bo ojú/orí? A) Ato B) Òjó D) Àìná #Ibeere #Yoruba,0,yoruba Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "Nígbà àkerekere, Ìyá mú. A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà.. Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba "Gbajúgbajà òṣèré John Adewumi ti ọ̀pọ̀lọpọ̀ mọ̀ sí Tafa Oleyede tó jáde láyé lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun, kìíní oṣù kejì yóò káà ilẹ̀ sùn lọ́jọ́ Ẹti, ọjọ́ kọkànlá oṣù kejì. Gómìnà ẹgbẹ́ TAMPAN ní ìpínlẹ̀ Osun, Alhaji Moruf Lawal lo sọ èyí nílùú Osogbo. Lawal ní àwọn tí parí gbogbo ètò pẹ̀lú àwọn mọ̀lẹ́bí olóògbé náà nipa bi isinku rẹ yoo se lọ. Ó ní lọ́jọ́bọ, ọjọ́ kẹwàá osu keji ọdun 2022 ni ẹgbẹ́ àwọn osere tiata yóò ṣe ayẹyẹ idagbere fun, ta tun mọ si ""Artist Day"". Ile rẹ to wa ní ìlú abinibi Tafa Oloyede, Ẹdẹ ni eto naa yoo ti maa waye bẹrẹ lati aago méjì ọ̀sán sí aago mẹ́fà ìrọ̀lẹ́. Bẹ́ẹ̀ náà ló ní alẹ́ àìsùn onígbàgbọ́ yóò wáyé lọ́jọ́bọ bákan náà, kí olóògbé tó máa lọ sinmi láyà olùgbàlà lọ́jọ́ Ẹtì, ọjọ kọkànlá. Àwọn àgbà òṣere n ṣe idaro Tafa Oloyede to re ibi agba n re yii. Gbajúgbajà òṣèré tíátà nì, John Adewumi tí ọ̀pọ̀ mọ̀ sí Tafa Oloyede dágbére fáyé Jide Kosoko, Otunba Dodoede n selédè lẹ́yìn Tafa Oloyede tó kú Ni kete ti iroyin iku oloogbe John Adewumi ni awọn agba oṣere bii Adebayo Bello ti ọpọ n pe ni Oga Bello ti n ṣe idaro rẹ . Awon mii tun ni Otunba Adekunle Abolade Dodoede to mẹnuba awọn ere Oloogbe Tafa to gbadun bii Ayanmọ Ekuro ọlọja, Orogun, Akanji Oniposi ati bẹẹ bẹẹ lọ. Ikú dóró: Gbajúgbajà òṣèré tíátà Tafa Oloyede dágbére fáyé Kò sí bó ti wù ká gbajúmọ̀ tó nílè ayé tàbí kí a là kàkà tó, ọjọ́ ọjọ́ kan la ó ṣe dúnìyàn lódìgbà. Gbajúgbajà òṣèré tíátà, John Adewumi tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn mọ̀ sí Tafa Oloyede ti dágbére fáyé. Lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun ni Tafa Oloyede mí mímí ìkẹyìn ní ilé rẹ̀ tó wà ní Arowomole, Osogbo, ìpínlẹ̀ Osun, lẹ́yìn àìsàn ráńpẹ́. Oloyede, tó di gbajúgbajà òṣèré lẹ́yìn tó kópa nínú eré Akanji Oniposi, fi ìyàwó àti àwọn ọmọ sáyé lọ. Ta ni Tafa Oloyede? John Adewumi ni orúkọ tí ìyá àti bàbá rẹ̀ sọ ṣùgbọ́n orúkọ ìnagijẹ rẹ̀ ni Tafa Oloyede. Ní ọjọ́ kọkàndínlógún, oṣù kọkànlá ọdún 1952 ni wọ́n bi, tó sì bẹ̀rẹ̀ eré tíátà lọ́dún 1974. Ọmọ bíbí ìlú Ẹdẹ ní ìpínlẹ̀ Osun ni, tó sì lọ sí ilé ẹ̀kọ́ alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ àti girama ní ìpínlẹ̀ Osun. Ó ti kópa nínú ọ̀pọ̀lọpọ̀ eré bíi Jayesinmi, Ayanmo, Ekuro Oloja, Orogun, Akanji Oniposi àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ.",0,yoruba "jú, àwọn ènìyàn ni ó pa Alàji lo ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba ègé olóótọ fún àwọn ìkòkò tí ó wáyé..,0,yoruba ìlú. ti Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba wúlò. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Alàji lo ni àṣà yorubá eyti o gbe lori ọ̀run dídì.,0,yoruba Omo Alata. 😯😯 👉 Yorùbátv ẸGBẸ ỌMỌ OLÚWA BÍ GBOGBO ÀGBÁYÉ Ojú òpó ìkànsíraẹni 🇳🇬🇹🇬🇧🇯🇧🇷🇨🇴🇨🇺🇬🇭🇨🇮______________________________□ Yoruba TV 🥰😘🔥 #yoruba #yorubatv #yorubaweddings #ebi #asoebi #nigerianwedding #hausa… https://t.co/EThzL82FIH,0,yoruba "Ẹgbẹ NLC ṣalaye lọjọ Aiku pe, bi ijọba ko ba tete ṣee, iyanṣẹlodi kale-n-kako yoo waye lorilẹede Naijiria. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ninu lẹta kan ti ẹgbẹ oṣiṣẹ kọ si ijọba apapọ, eleyii ti akọwe apapọ rẹ, Emmanuel Ugboaja fọwọ si lo yọju eyi sita to si n rọ awọn alakoso ẹkun ẹgbẹ oṣiṣẹ gbogbo lorilẹede Naijiria lati maa mura silẹ. Amọṣa, bi awọn iwe iroyin abẹle kan lorilẹede Naijiria ti ṣe gbee sita, minisita fọrọ oṣiṣẹ, Chris Ngige ti n lepa ati pana wahala to ṣeeṣe ko bẹ silẹ lagbo oṣiṣẹ. Nibayii , Ngige ti pe ipade kan pẹlu awọn aṣoju ẹgbẹ oṣiṣẹ, NLC ati igbimọ to n duna-dura lorukọ oṣiṣẹ Joint National Public Service Negotiating Council (JNPSNC) ni ọjọ Iṣẹgun. Bakan naa ni gomina Kayọde Fayẹmi to jẹ olori ajs awọn gomina ipinlẹ lorilẹede Naijiria, NGF pẹlu ti rawọ ẹbẹ sawọn oṣiṣẹ lati bu omi suuru mu lori igbesẹ a n yanṣa lodi. O ni ko yẹ kawọ ẹgbẹ oṣiṣẹ fẹ da luru pọ mọ ṣapa niap dida ọrọ owo oṣu tuntun to kere ju fun oṣiṣẹ pọ mọ ọrọ ẹkunwo oṣu. Ẹgbẹ oṣiṣẹ n beere fun afikun ida mọkandinlọgbọn owo osu fun awọn oṣiṣẹ alakasọ keje si ikẹrinrinla, ati afikun ida mẹrinlelogun fun awọn oṣiṣẹ alakasọ karundinlogun si ikẹtadinlogun.",0,yoruba gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Alàji lo aye àìlẹ̀.,0,yoruba "ojú òní.. Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.",0,yoruba "Bótilẹ̀jẹ́pé ẹ̀rọ-alátagbà ni ìṣètò tìrẹ, o lè rí àwòṣe. Ìṣètò Ibi-ìkọ̀kọ̀ ń bẹ láti dáhùn ìbéèrè: """"""""""""""""""""""""""""""""ta ló lè rí ọ?"""""""""""""""""""""""""""""""" Níbí lo ti ṣe é ṣe kí o rí ààtò tí ó ní í ṣe pẹ̀lú ààtòàbáwá (""""""""""""""""""""""""""""""""gbogboògbò,"""""""""""""""""""""""""""""""" """"""""""""""""""""""""""""""""ọ̀rẹ́ ọ̀rẹ́,"""""""""""""""""""""""""""""""" """"""""""""""""""""""""""""""""ọ̀rẹ́ nìkan,"""""""""""""""""""""""""""""""" abbl),",0,yoruba RT @user: Eni Aba laba ni BaBa @user,0,yoruba @user Èdè Potokí lẹ fi kọ ọ́ ni? Ọlọ́run ṣe é mo kúkú gbọ́ ìyẹn náà díẹ̀. :),0,yoruba ti ibile. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọmọ lo ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà.,0,yoruba "Àkọ́kọ́, Ọba joko lòdì Òyó. Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.. Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "RT @user: Kòsí bí óse wù kì órí, ẹjẹ́ kí á bọ̀wọ̀ fún àgbà nítorí bí wọ̀n se jẹ́. @user @user @user",0,yoruba "Abideen ti ọpọ eeyan mọ si Ejiogbe sọ fun ileeṣẹ BBC Yoruba ninu ifọrọwerọ pe ohun ko ni nkankan sọ nipa igbesẹ yi yatọ si eleyi ti awọn agba ẹgbẹ NURTW ni Abuja ba sọ. Ni ọjọ Aje ni ijọba ipinlẹ Oyo ṣe ifilọlẹ awọn adari ibudo iwọkọ ti yoo ma ṣe akoso gbigba owo si apo ijọba lawọn ibudoko kaakiri ipinlẹ naa. Fun idi eyi, ọwọ ijọba ipinlẹ Oyo ni owo ti wọn ba gba yoo maa lọ bayii. Ṣaaju ifilọlẹ yi, Ejiogbe ati awọn ọmọ gbẹ rẹ kan ti fohun silẹ ninu fọnran fidio kan pe awọn yoo da wahala silẹ ti ijọba ba tẹsiwaju pẹlu igbesẹ yi lọjọ Aje. Alhaji Mukaila Lamidi ti awọn eeyan mọ si Auxilliary naa da si ọrọ yi ninu fidio ti ẹ na totini kawọn eeyan sowọ pọ pẹlu ijọba. Ninu atẹjade tawọn naa fi sita ni idahun si fidio yi, ileeṣẹ ọlọpaa ni Oyo fi ikilọ sita pe ki awọn ọmọ ẹgbẹ naa ti ọwọ ọmọ wọn baṣọ ti wọn ko ba fẹ jẹ iyan wọn niṣu. Ẹwẹ ifilọlọlẹ awọn adari tuntun yi ti waye gẹgẹ bi ohun ta ri ka ninu iwe iroyin Tribune to fi Ibadan ṣe ibujoko. Gẹgẹ bi wọn ṣe sọ,Kọmisana fun ohun amayederun ati irinna ni Oyo, Raphael Afonja lo ṣe ifilọlẹ yi. Yatọ si awọn adari ti wọn yan ati igbakeji wọn fun ibudokọ kọọkan, ijọba tun fi alaga ẹgbẹ awakọ ero tẹlẹ ri ni Ibadan Alahaji Lamidi Mukaila Auxiliary jẹ alaga igbimọ ti yoo ma ṣe akoso awọn adari wọn yi. Kò sí ǹkan tó ń jẹ́ ọ̀rọ̀ ìgbàgbọ́ tàbí ìmọ̀le nínú àgbékalẹ̀ Amotekun - Alake ti Egba",0,yoruba Àkóbì níjó òní nípa ayé ọ̀ṣun ni nfàn ojú kakaaki.,0,yoruba RT @user: Àwòrán: Onílù | Ọláòníye Àllíù Fèyíṣọlá https://t.co/PepzFApRak #Atelewo #Yoruba https://t.co/MhK9JJFLVC,0,yoruba "Afurasi naa, Tope Olaitan, ṣalaye pe iṣẹ gbẹnagbẹna ni oun yan laayo ṣaaju iṣẹ ole jija, ṣugbọn nnkan ko ṣenure ni saa kan nitori airi owo ile ati owo ṣọọbu san. O ni oun ki i fi ohun ija oloro jale bi awọn ole miran, ṣugbọn igboya lasan ni oun maa n lo lati ṣẹru ba awọn ti oun ba fẹ ja lole. Olaitan ṣalaye pe ""ẹrọ ibanisọrọ ati kọmputa alagbeka ni mo yan laayo lati maa ji, ti mo ba fẹ jale, niṣe ni mo maa n ki ọwọ sinu aṣọ bi ẹni to ni ibọn lọwọ lati fi ko awọn eeyan laya jẹ."" Nigba to n ṣalaye iṣẹ to ṣe kẹyin ki ọwọ ọpalanba rẹ to segi, o ni oun fo igana wọ inu ile obinrin kan ti oun ṣakiyesi pe o n da gbe, oun si beere owo lọwọ rẹ ṣugbọn o kọ jalẹ. O ni lẹyin ti gbogbo akitiyan oun lati gba owo lọwọ obinrin naa ja si pabo ni oun wọ inu ile idana rẹ lọ, ti oun si ri ẹran tolotolo meji ninu firiji. Gẹgẹ bo sọ, ẹran naa lo n se lọwọ ninu ile idana ti obinrin ọhun fi ri aye ṣa asala mọ o lọwọ to si kẹ gbajari si awọn eeyan adugbo. Afurasi ọhun ni afujusun oun ni lati fi owo ti ohun ba ri ninu iṣẹ ole jija tun ṣoọbu to wa niwaju ile iya oun ṣe, lati maa lo fun iṣẹ gbẹnagbẹna. Olaitan sọ pe oun kabamọ ole jija nitori itiju ti oun mu ba awọn ẹbi oun. Mayowa Omoniyi: Kò sí orin Obey, Sunny Ade abí tàkasúfèé tí ń kò le ta gìtá sí Saaju ni ọkunrin kan ti kọkọ jale pẹlu irufẹ ero to yatọ bayii: Inú oṣù kẹwàá ni mo ti ń ṣètò olè tí mo jà ní Báǹkì mi- Larry Ehizo Oṣiṣẹ́ to wà ni ẹ̀ka to n ri si ẹdún awọn onibara banki ti ọlọpàá dá wọn lọ́wọ́ iṣẹ́ duro lọ́jọ́ satide to kọja Larry Ehizo ní, láti inú oṣù kẹwàá ọdun 2019 ni òun ti bẹ̀rẹ̀ sini ṣètò bi òun yóò ṣe lọ digun ja Banki náà lóle. Ehizo yìí lo pada kúrò lóri ọ̀rọ̀ rẹ̀ pé ọkunrin agbọti kan ló n ba òun lórukọ jẹ́ to si ni ki òun lọ jale, o ní òun ti n gbà á lérò tí òun si ti n mojuto bi ètò ààbo Banki náà ṣe wà tẹ́lẹ̀. Ọkùnrin yii ṣàlàyé pé gbogbo ǹkan ti Ewim sọ òòtọ ni, ""kò dúkokò mọ ni. Mo fi tọ́kantọkan gba nọmba rẹ̀ ni, mo pè é o si ni ki n fún òun ní àsìkò díẹ̀"" "" Nígbà ti mo pè é, mo ṣàlàyé fun bi yóò ṣe wọle, ibi ti wọ́n yóò ti ri àwọn ọlọpàá to n sọ banki náà, ọnà ti wọ́n yóò gbà láti yọ ẹrọ ayaworan (CCTV) kúrò. Ní alẹ́ ọjọ Jimọ lásìkò ìpàdé wa, a ni ìsòrò láti ri awakọ ti yóò wà wá."" Abuja Bank Robbery: Inú oṣù kẹwàá ni móti n ṣeto jíja olè ni Banki mi- Larry Ehizo Nígbà ti akọròyìn bèrè pé kíní ìdí ti Ehizo fi ṣe irú ǹkan bẹ́ẹ̀, o ni ìwà ọkájúwà lásán ni, mo rò pé ǹkan ti yóò rọrun láti ṣe ni, mo ti lo àsìkò mi láti wo gbogbo ǹkan ti mo fẹ́ ṣe, mo ti n ro láti inú oṣù kẹwàá. "" Bóyá nitori pé mo ń siṣẹ́ ni Banki ni, mo ro pé mo le ni ìpín nínú owo banki, nítori náà mo ti wo gbogbo ibi ti CCTV wa ibi ti àwọn ọlọpàá wa, bi wọ́n ṣe maa n wà ni òpìn ọṣẹṣẹ, àti ẹrọ apọwo wa ṣe maa ṣe lásìkò náà"" 'Inu mi bàjẹ́ nígbà tí mo bí i, odidi oṣù mẹ́ta, mi ò lè gbàdúrà s'Ọ́lọ́run' Ọlọpàá Ilú Abuja ti mú àwọn ọmọ ẹgbẹ́ ọdaran méfa ninu àwọn ọdaran bẹ́ẹ̀ ni wọ́n tun mu Ewim nibi to sápamọ si. Sááju ni ọlọpàá ti fún ọkan ninu wọ́n ti wọ́n pe Patrick nibón ti wọ́n si mu àwọn mẹ́rin to ku lẹyin ti ipinu wọ́n kùna Kọmisọnna ilú Abuja Bala Ciroma ti fi oju wọ́n han ni ọjọ iṣẹ́gun to fi mọ Ehizo ọgbọn ọdun, Timothy Joe ọdun mọkanlelogun, Princewill Obinna, mẹrinlélogun, àti Elijah David mọkandinklogun.",0,yoruba "iṣẹ́ ni nkan pataki lojiji. Ọmọ lo tun se lọ. Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba apo ikowosi ile okere egbe oselu pdp pe fun fifi owo sikun ofin mu asiwaju bola ahmed tinubu,0,yoruba agba ri pe ṣe iyalẹnu wey ti o tẹ.,0,yoruba ìgbà mi owó àkokò eyti o gbe lori iwa rere.,0,yoruba Olódùmarè Ọba-Atẹ́nílẹ́gẹ́lẹ́gẹ́ fi orí ṣe agbeji ẹni ni ìṣẹ̀ṣe. Òhun ló dá àgbá-ńlá ilé ayé. #Iseseday #Iseselagba #Yoruba #August20,0,yoruba "Ní oṣù Ẹrẹ́nà ọdún yìí , Enough is Enough Nigeria ( EIE ) , tí ó jẹ́ àkójọpọ̀ àwọn ọ̀dọ́ kan àti Paradigm Initiative ( PI ) , tí ó jẹ́ ẹgbẹ́ aṣòfin àti ajàfẹ́tọ̀ọ́ ẹni lórí ẹ̀rọ - ayárabíàṣá , ṣe ìfilọ́lẹ̀ ìpèlẹ́jọ́ Onochie àti Gbénga Ọlọ́runpomi tí ó jẹ́ olùrànlọ́wọ́ gómìnà ìpínlẹ̀ - ẹ Kogi lẹ́jọ́ ní Ilé - ẹjọ́ kan ní Abuja .",0,yoruba "Lẹyin ti gbogbo ọmọ Naijira bẹnu atẹ lu bi awọn ọlọpaa ṣe lu arakunrin naa, ni wọn ṣe ayẹwo oku rẹ. Ayẹwọ naa ti o tẹ awọn oniroyin lọwọ fi han wi pe ko si aisan kankan lara arakunrin naa ki o to ku lojiji lẹyin iṣẹlẹ pẹlu awọn ọlọpaaa naa. Iroyin yi n jade lẹyin ti agbẹnusọ ọlọpaa ni Naijiria, Frank Mba ni ko si oun kankan to ṣe Ogah ati wi pe, ṣe ni o funra rẹ wa ọkọ rẹ wa si agọ ọlọpaa Nyanya ki o to gbẹmi mi. Mba sọ nigba naa wi pe ko si ootọ kankan ninu iroyin wi pe awọn ọlọpaa lu u ni alubami. Ibi ibudo awọn ọlọpaa to n dari ọkọ ni popona Nyanya-Karshi ni bi aago meje aabọ ogunjọ oṣu kẹta ni iṣelẹ naa ṣẹlẹ. Iyawo rẹ sọ fun awọn oniroyin wi pe nigba ti wọn mu ọkọ oun, oun ati ọmọ oun wa nibẹ. O ṣalaye wi pe, ṣe ni wọn fi kóńdó ọlọ́pàá náà lori ati lara. Esi ayẹwo ile iwosan lori oku Ogah fi han wi pe, lẹyin lilu ti wọn lu oloogbe naa, ọpọlọ rẹ wu. Wọn ni oun to pa ree. Akọroyin BBC Yoruba kan si Mba lati gbọ oun to nii sọ nipa esi ayẹwo yii ati igbesẹ ti ileeṣẹ ọlọpaa fẹ gbe lori ọrọ naa. Ṣugbọn oluranlọwọ rẹ kan sọ wi pe, o wa ninu ipade, ati wi pe irọle ni yoo le ba akọroyin naa sọrọ. Segalink:ìkùnsínú pọ̀ láàrin àwọn agbófinró bẹ́ẹ̀ wọn kò ni agbẹnusọ",0,yoruba asin. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó ṣe pàtàkì.,0,yoruba "Ní igba mi owó àkokò, Baàlè ri Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀. ti A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..",0,yoruba "Lẹyin ti awọn agbebọn pa Funke Olakunrin to jẹ ọmọ adari ẹgbẹ Afẹnifẹrẹ lorilẹ-ede Naijiria, iṣẹlẹ naa wu ọpọlọnu irunu jade lọdọ awọn ọmọ Naijiria. Lara eyi naa lo mu ki awọn ọdọ ipinlẹ Ondo figbe ta pe o ti to gẹ pe ki awon Fulani kuro lagbegbe awọn, tori awọn kan n sọ wi pe awọn lo wa nidi iku rẹ. Adekanbi Oluwatuyi to jẹ olori ọdọ ni gbogbo ilu Akure sọ fun BBC Yoruba pe gbogbo agbaye mọ pe iṣẹ agbẹ lo wọpọ ju lagbegbe awọn ṣugbọn gbogbo eniyan lo ti sa kuro l'oko. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ṣe ni wọn n tẹnu mọ ọ pe awọn Fulani darandaran ti gba gbogbo ilu awọn tan wọn si ti n ke si ijọba titi titi ti ko si oun ti ijọba ṣe. Olori ọdọ ni ohun to ku tawọn yoo ṣe ni ki onikaluku maa ja funra wọn.",0,yoruba ANUOLUWAPOSI × Yoruba The mercies of God are ever increasing. #Anuoluwaposi #Yoruba #MARDLife #AfricanNames #NigerianNames #NamesAndMeaning #NameAndMeaning #MeaningOfNames #Meaning #Mercy #Increase #Anu https://t.co/W2iTSyj2JV,0,yoruba owo ṣẹlẹ ni Eko ti gbogbo eniyan sọ o dara. (1998),0,yoruba "Bọ́tà (butter) kì í ṣe oúnjẹ ọ̀bọ. Ta l'ó kọ́kọ́ p'òwe ìgbàlódée nì gan-an! Mo mọ́ ọn ń rò, kílonítọ̀hún rí tí ó fi pa á. #Owe #Yoruba",0,yoruba "Fidio to jade safihan awọn akẹẹkọ girama ti wọn n sa asala fun ẹmi wọn lẹyin ti ọkan ninu won da ipaya sile. Opin ọsẹ ni fidio kan jade nibiti awọn ọmọ ile iwe girama ti n sa asala fun ẹmi wọn lẹyin ti rogbodiyan bẹ silẹ ni ile iwe naa. Ọlọpaa ninu atẹjade ti wọn fi lede sọ wi pe awọn ọmọ kilasi SS2 ati SS3 ti wọn ni ija ti tẹlẹ ni wọn fẹ sọsẹ fun ara wọn. Ọkan ninu wọn lo mu tajutaju wa lati ile, amọ ti ẹlomiran si mu u nibi to fi pamọ si to si fi si ara awọn ọmọ kilasii rẹ. Awọn wọn yii lo bẹ jade gba oju ferese ti wọn si bẹrẹ si ni sa asala fun ẹmi wọn, eleyii to da ipaya si lẹ, ti gbogbo ile iwe fi daru lọjọ naa. Ile isẹ ọlọpaa naa wa fi da awọn eniyan loju pe ọrọ naa ki i se igbesunmọni tabi ikọlu, sugbọn aigboraẹniye laaarin awọn akẹẹkọ lo fa wahala. Iwadii si n lo lori awọn to da wahala naa silẹ ni ile ẹkọ girama naa, ati wi pe Ọjọ Aje, Ọjọ Kẹtadinlọgbọn ni ọkunrin to fi tajutaju naa yoo pada si agọ ọlọpaa. Mike Ifabunmi: Òrìṣà ló gbè wà jù ni Brazil",0,yoruba ọmọ ri pe jẹ́ pàtàkì wey ti o dun.,0,yoruba e fun wa nina,0,yoruba Foran! Aaare Biafra to otun je atokin egbe IPOB @user ofi tibi sere rara!😋😋😋😋😋 https://t.co/YfC0cLBWQV,0,yoruba "Àwọn apani ṣe iṣẹ́ wọn pé , wọn kò sì dáwọ́ dúró lẹ́yìn tí wọ́n yẹgi fún wọn , wọ́n tún wọ́ òkúu wọn nílẹ̀ bẹ́ẹ̀ náà ni wọ́n sì ń jókòó lé wọn lórí .",0,yoruba "Nígbà tó kún jú, àwọn ènìyàn ni ó jáde nìlẹ̀̀ní sáàrí ti nípa ìtànká àti ire ènìyàn.",0,yoruba "Gbànjo! Ra àwọn ìwé méjèèjì yìí papọ̀ ni N4,999 péré. Ọ̀kan jẹ́ ewì. Èkejì jẹ́ àròsọ. Ìwé méjèèjì jẹ́ iṣẹ́ Emily R. Grosholz àti Wọlé Sóyínká ti @user àti Akínwùmí Ìṣọ̀lá túmọ̀ sí èdè Yorùbá. #Yoruba #Atelewo #Yorubabooks https://t.co/AGm1FCebVF",0,yoruba "Ní nígbà àkerekere, Baàlè ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Bàbá lo ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Ọọni ti Ile Ife, Adeyeye Ogunwusi nigba ti awọn obi ọmọ yọju si i laafin sọ pe ki wọn ma foya, o ṣe iléri pé òun yóò tu iṣu dé ìsàlẹ̀ ikoko lóri ọ̀rọ̀ náà ati pé ìpè yòó lọ si ọdọ àwọn àjọ DSS láti ma jẹ́ ki àwọn alagbara kankan o yọ woli náà kuro latimọle titi ti ọ̀rọ̀ yòó fi yanju. Ọọni ni pé wọ́n o mú wọ́n si ilé Orisà Oodua láti lọ wádìí ibi ti ọmọ náà wa. Bí ọ̀rọ̀ ṣe ṣẹlẹ̀ Arabinrin Olawole to jẹ́ iyá Gold Kolawole lo gbe ọmọ rẹ̀ lọ si sọọsi awọn ọmọde nile ijọsin wọn lẹ́yin ọ̀pọ̀lọpọ ọ̀rọ̀ latọdọ àwọn olukọ ọmọde ninu ijọ náà pe ki iya Gold maa gbé ọmọ rẹ̀ wá si ilé ijọsin ọmọ wẹwẹ. Akure Kidnap: Àwọn abiyamọ fẹ̀hónúhàn lórí ọmọ tí wan jígbé nílé ìjọsìn Akurẹ Ọpọlọpọ lo ti fẹhonu han lori ọ̀rọ̀ yii nigba ti wn ko ri ki ohunkohun ṣẹlẹ lati igba ti iya ọmọ ti figbe ta. Lẹ́yin ti o pada lọ si ilé ijọsin láti lọ wo ọmọ rẹ̀ ló ri i pé ọmọ náà ko si nibẹ̀ mọ. Sotitobire church: Ẹgbẹ́ CAN ní kí ìjọba ṣe ohun tó yẹ Bayii ni wahala ṣe bẹ̀rẹ̀, nitori pé o hàn gbangba pé ẹnikan ti ji ọmọ gbé. Kini otitiọ kini irọ́ nínú gbogbo ìṣẹ̀lẹ̀ náà Gẹ́gẹ́ bí ìyá ọmọ náà ṣe sọ, nígba ti ọmọ sọnú, o ni oludásìlẹ̀ ijọ náà Alufa Babatunde rọ àwọn láti lọ simi silé ki wọn si ma fi ọ̀rọ̀ náà lọ ọlọpàá. Lẹ́yìn gbogbo ìgbìyànju ti ọmọ náà kò si jẹ́ rírí, Arabinrin Kolawole ni olùdásilẹ̀ ijọ náà ko gbe igbésẹ̀ kan to ṣe koko, èyí ló fàá ti òun fi ke gbajare sita ti Deji Akure si fi pa a láṣẹ̀ pé ki awọn wa bura. Arabinrin Modupe Kolawole ni àwọn aṣọna to wa lẹ́nu iṣẹ́ lọ́jọ́ náà àti igbakeji oludari lo lọ sibẹ ṣùgbọ́n oludasilẹ ijọ ko dasi ọ̀rọ̀ náà. Wọn pa ọlọ́pàá kan níbi tí wọ́n ti dáná sun ìjọ Sotitobire l'Akurẹ - Police PRO Sotitobire church: Àwọn ọ̀dọ́ ilu dáná sun ilé ìjọsìn Nígba ti ọ̀rọ̀ de agọ ọlọpàá, nínú àwọn aṣọ́na mẹrinla to wà nilé ijọsin lọ́jọ́ ìṣẹ̀lẹ̀ náà, meji péré lo yọju si agọ ọlọpàá. Ní ọ̀sẹ̀ to kioja nígba ti ọ̀rọ̀ náà kò yanju ni ọlọpàá gbé Alfa Babatunde lọ si agọ wọ́n fun ifọ̀rọ̀wánilẹnuwo. BBC yoruba ko ri àrídáju pé lóòtọ ni Alfa Babatunde dáku ni àgọ àwọn àjọ DSS. Ijọ Sotitobirẹ: Idí ilé òrìsà ni ọ̀rọ̀ náà yoò ti yànju- Ọọni Ife Ní ọjọ ru ni òkíkí kan pé wọ́n ri òkú ọmọ kan nibi ti wọ́n rì í mọ́lẹ̀ si niwáju pẹpẹ ilé ìjọsin Sọtitobirẹ, èyí si lo ṣe okùnfa ti àwọn ọdọ àti ara ilú fi lọ dána sun ilé Woli àti ijọ Sotitobirẹ nilu Akure. Nígba ti ọ̀rọ̀ náà bẹ̀rẹ̀, àwọn kan ni Alfa ọhun ni ìbásṣepọ pẹlú gomina ìpínlẹ̀ Ondo, èyi si ló ṣe okùnfa ti Gomina ipínlẹ̀ kò fi dá si ọ̀rọ̀ náà. Sùgbọ́n ní ìgba ti BBC ba oluranlọwọ pàtàki Gomina Akeredolu Onimọ ẹrọ Tunji Ariyomo sọ̀rọ̀ lóri ọ̀rọ̀ rẹ̀, o ni kò si ǹkan to jọ bẹ́ẹ̀, sùgbọ́n gẹ́gẹ́ bi olórí, oye lààgbà wó ni gomina fi ṣe, ati pe Gomina ko ni ìbásepọ kankan pẹ̀lú woli náà. O ni ""ipo Ọba ni Gomina wa, ko yẹ ko yára sọrọ"". Níbo ni ọ̀rọ̀ de duro bayìí? Nígba ti BBC kan si àjọ CAN lóri ọ̀rọ̀ náà , wọ́n ni àwọn kò ni ọ̀rọ̀ kankan láti sọ nítori pé Babtunde kìí ṣe ọmọ ẹgbẹ́ Christian Association of Nigeria (CAN). Ní bayìí ilé iṣẹ́ ọlọpàá ti kó ọmọ ijọ méje àti àwọn ènìyàn mẹ́wàá mìíràn ti wọ́n ba níbi ti wọ́n ti n kó àwọn nkan to jóná kù. Arabinrin Modupe Kolawole ni àwọn asọna to wa lẹ́nu iṣẹ́ lọ́jọ́ náà àti igbakeji oludari lo lọ sibl sùgbọ́n oludasilẹ o dasi ọ̀rọ̀ náà. Idí ilé òrìsà ni ọ̀rọ̀ náà yoò ti yànju - Ọọni Ife Bakan náà ni àkọròyìn BBC ní Akurẹ sàlàyé pé ìyá ọmọ to sọnú fi ìròyìn sọwọ́ sí òun pé àwọn ti lọ ri Ọni ilé Ifẹ̀ Ọba Adeyeye Enitan Ogunwusi lóri ọ̀rọ̀ ọmọ náà ati pé Kabiyesi ti ṣe iléri pé òun yóò tu iṣu dé ìsàlẹ̀ ikoko lóri ọ̀rọ̀ náà ati pé ìpè yòó lọ si ọdọ àwọn àjọ DSS láti ma jẹ́ ki àwọn alagbara kankan o yọ woli náà kuro latimọle titi ti ọ̀rọ̀ yòó fi yanju. Bakan náà ni Ọọni ni ki wọ́n fi ọkàn wọ́n balẹ̀ pé wọ́n o mú wọ́n si ilé Orisà Oodua láti lọ wádìí ibi ti ọmọ náà wa.",0,yoruba "Atẹjade kan lati ọọfisi ile igbimọ aṣofin ilẹ Gẹẹsi ti sọ pe o yẹ ki awọn obinrin maa ṣe ayẹwo ‘menopause’ wọn ti wọn ba ti wọ ọdun marundinlaadọta. Ẹgbẹ kan, Menopause All-Party Parliamentary Group, lo sọ bẹẹ lẹyin iwadii ti wọn ṣe fun ọdun kan gbako. Aṣofin kan, Carolyn Harris sọ pe oniruru idẹyẹsi lawọn obinrin ti wọn ko ri nnkan oṣu wọn maa n koju, eyii to maa n ṣakoba fun wọn lẹnu iṣẹ, laarin awọn ọrẹ ati ẹbi ati lọdọ ololufẹ wọn. Akoko yii jẹ igba ti awọn obinrin ko ni le ṣe nnkan oṣu wọn mọ, eyii to tun n tumọ si pe wọn ko ni le loyun. ‘Menopause’ yii maa n waye ti obinrin ba ti n dagba, o si maa n bẹrẹ lati ọdun marundinlaadọta si ọdun marundinlọgọta. O tun le waye nipa iṣẹ abẹ, eyi ti wọn n pe ni ‘hysterectomy.’ Ti obinrin ko ba ri nnkan oṣu rẹ fun oṣu mejila gbako, o n tumọ si pe o ti wọ ‘menopause’ niyẹn. Iye ọjọ ori ti obinrin ko fi ni ri nnkan oṣu rẹ mọ bẹrẹ lati ọdun mọkanlelaadọta, amọ o ṣeeṣe ki awọn obinrin kan ti ọjọ ori wọn ko tii wọ ọgbọn ọdun naa wọ menopause. Ipele ti obinrin fi n wọ menopause ni wọn  pe ‘Perimenopause.’ Awọn obinrin kan maa n ri apẹrẹ lara wọn pe menopause ti n sumọle, amọ awọn obinrin mii ki n ri titi di igba ti wọn ko fi ni ri nnkan oṣu naa mọ. Awọn apẹrẹ menopause ati perimenopause ni ipa nla ninu aye obinrin, paapaa lori iṣẹ ati ibaṣepọ wọn pẹlu awọn ẹlomiran. Amọ awọn apẹrẹ naa ko dọgba, nitori oniruru eeyan lo maa n ri oniruru apẹrẹ tirẹ to si yatọ si ti ẹlomiran. Awọn apẹrẹ naa maa jade fun ọpọ ọsẹ tabi oṣu ko to di pe nnkan oṣu naa ko ni waye mọ. Apẹrẹ akọkọ ni pe nnkan oṣu irufẹ obinrin bẹẹ yoo maa ṣe segesege. Bakan naa, o ṣeeṣe ki irufẹ obinrin naa maa binu si awọn eeyan ti ko yẹ ko binu si ati ni akoko ti ko yẹ ko binu. Onimọ nipa nnkan oṣu obinrin, Heather Currie sọ pe ko yẹ ki awọn obinrin foya ti wọn ko ba ri nnkan oṣu naa mọ. Lara awọn nnkan to sọ ni pe wọn le lo awọn oogun to le dipo awọn ẹya ara wọn bii osetrogen ati progesterone to n jẹ ki nnkan oṣu wa. O tun mẹnuba jijẹ awọn ounjẹ aṣaraloore ti wọn n pe ni ‘balanced diet.’ Dokita naa sọ pe ere idaraya ṣe pataki. Lẹyin naa lo gba awọn obinrin niyanju lati sọra fun siga ati ọti mimu.",0,yoruba ẹkọ́: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa aráyé: ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó wáyé.,0,yoruba "Lara awọn iṣẹlẹ manigbagbe naa ree: Iwọde #EndSARS Iwọde EndSARS bẹrẹ lẹyin ti fidio kan fa ori ayelujara ya lọjọ kẹta, oṣu Kẹwaa, ọdun 2020, eyii to ṣafihan bi awọn ọlọpaa SARS ṣe yinbọn fun ọkunri na niwaju ile itura Wetland, to wa ni Ugheli, ni ipinlẹ Delta. Iṣelẹ naa lo ta epo si ifẹhonuhan EndSARS lori ikanni Twitter. Ṣugbọn nigba ti iyẹn ṣi n lọwọ, ni iroyin kan tun jade pe awọn oṣiṣẹ SARS tun ti pa olorin takasufe kan to jẹ ọmọ ogun ọdun, ti orukẹ rẹ n jẹ Daniel Chibuike. Lẹyin naa ni awọn eeyan bẹrẹ iwọde kaakiri awọn ilu nla ni Naijiria ati loke okun, ti wọn si n ke gbajare si ijọba apapọ pe ko fi opin ẹka ileeṣẹ ọlọpaa SARS naa. AbdulQudus Bello ṣàlàyé bí òun ṣe dí aláàbọ̀ ara nítorí pọpọ́ọ̀fù àti ìbínú jàǹdùkù àdúgbò Igba to di ọjọ kẹjọ, oṣu Kẹwaa, ọdun 2020 ni iwọde ita gbangba bẹrẹ ni pẹrẹwu, ti ọpọ awọn gbajumọ ni Naijiria ati kaakiri agbaye si n sọ pe wọn fi ọwọ si iwọde ọhun. Ifẹmiṣofo ni Lekki Toll Gate Ni nnkan bi aago mẹfa abọ ogunjọ, oṣu Kẹwaa, ọdun 2020, ni awọn ẹṣọ alabo ṣina ibọn bolẹ fun awọn oluwọde to kọ lati fi iloro naa silẹ lẹyin ti ijọba ipinlẹ Eko ti kede ofin konile-o-gble oni wakati mẹrinlelogun. Olorin takasufe kan, Dj Switch ka iṣẹlẹ naa silẹ loju opo Instagram rẹ, to si sọ pe awọn ọlọpaa atawọn ọmọ ogun lo ṣiṣẹ ibi naa, ṣugbọn ileeṣẹ ologun ti ni oun ko mọwọ mẹsẹ ninu iṣẹlẹ ọhun. Jiji ounjẹ iranwọ Covid-19 ko Lẹyin ti iwọde EndSARS gbọna mii yọ ni awọn janduku ja iwọde naa gba, ti wọn si bẹrẹ sii kọlu awọn ile ti ijọba ko ounjẹ iranwọ Covid-19 pamọ si. Wọn ni o yẹ ki ijọba ti pin awọn ounjẹ naa, ṣugbọn wọn ko pa lati lu ni gbanjo. Awọn miran tun ṣakọlu si ọpọ agọ ọlọpaa ni ipinlẹ Eko, alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko tilẹ sọ fun BBC pe ko din ni agọ ọlọpaa marundinlogun ti awọn janduku naa dana sun. EndSars, EndSwat Protest: Òbí agbábọ̀ọ̀lù Gbenga Tiamiyu Kaka àtàwọn míì tí ọlapàá pa sọ̀r Ikọlu gomina ipinlẹ Osun Ọjọ kọkandinlogun oṣu Kẹwaa yii kan naa ni awọn janduku kan ṣakọlu si gomina ipinlẹ Osun, Gboyega Oyetola, nibi iwọde EndSARS ni ilu Osogbo. Awọn janduku ọhun sọ oko, kondo atawọn ohun ija miran si gomina ọhun, ti awọn eeyan si farapa. Akomolede àti Asa lórí BBC Yorùbá: Mọ̀ síi nípa ẹ̀kún ìyàwó níbí Awọn ẹlẹwọn salọ ni Edo Igba ti iwọde EndSARS n lọwọ ni awọn janduku kọlu ọgba ẹwọn to wa ni opopona Sapele, ti wọn si tu awọn ẹlẹwọn silẹ. Nnkan bi ẹgbẹrun meji ẹlẹwọn ni awọn janduku naa fun ni ominira, eyii to mu ki gomina Godwin Obaaseki kede igbele oni wakati mẹrinlelogun. Igbohunsafẹfẹ Aarẹ Muhammadu Buhari Lẹyin ti iwọde EndSARS ti bẹrẹ lọpọ eeyan kaakiri Naijiria ti n reti ki Aarẹ Muhammadu Buhari sọrọ soke ṣugbọn ko wi nnkan. Ẹwẹ, lẹyin ti awọn ṣọja yinbọ fun awọn oluwọde ni iloro Lekki, ti gbogbo ọrọ si dojuru ni Aarẹ to sọrọ soke. Orlando Owoh: Èmí àti Oladipupo Owomoyela jọ lọ ẹ̀wọ̀n Alágbọn- Caroline Owoh, aya Orlando Ṣugbọn o ṣeni laanu pe igbohunsafẹfẹ naa ko tẹ awọn ọmọ Naijiria lọrun nitori wọn ni ọkọ Aisha ko mẹnuba ohun ti wọn reti ko sọ. Bi awọn kan ṣe n sọ pe ifakoko ṣofo lasan ni igbohunsafẹfẹ naa lawọn miran n sọ pe ki ṣe Aarẹ lo ṣe igbohunsafẹfẹ ọhun.",0,yoruba ẹní bá ríbi ṣu á dáwọ́ tẹlẹ̀ á fẹju ranran,0,yoruba "RT @user: Jedi ko m'akowe...#ATUNTE! """"""""""""""""""""""""""""""""@user: Pápàpá iṣẹ́ tòní ń tán lọ. Ó wá ku fàájì pẹrẹhu. Àríyá kẹlẹlẹ.""""""""""""""""""""""""""""""""",0,yoruba "Ibo oôdun 2015 ti n sun moôle,Haa, Atiku fee ba ti Jonathan je o http://t.co/EprZkrfNhk",0,yoruba Kini Yoòbá ń pe A àti B inú àwòrán yìí? #ibeere #Yoruba https://t.co/SxBJK8fVHY,0,yoruba Coronavirus in Nigeria: Ìtànkálẹ̀ coronavirus ṣe ìdíwọ́ fún ìrun Jimọ,0,yoruba "Buhari lo sọ ọrọ naa loju opo Twitter rẹ nibi to ti sọ pe afojusun ijọba oun ni lati mu ki idagbasoke de ba agbegbe naa. O ni ""Mo ti paṣẹ fun awọn aṣoju-sofin ati agbofinro lati fọwọ-sowọpọ ki wọn lee mọ ibi ti owo ti ijọba n la kalẹ fun agbegbe naa n wọlẹ si."" End of Twitter post, 1 Aarẹ tẹsiwaju pe ki gbogbo ileeṣẹ ati ajọ to n ṣewadii ajọ NDDC jara mọṣẹ, ki wọn si bu oun gbọ lori ibi ti wọn ba baṣẹ de. Buhari pari ọrọ rẹ pe ijọba oun ko ni bojuwẹyin ninu afojusun rẹ lati ri pe ajọ NDDC atawọn ileeṣe ijooba apapọ miran kun oju oṣuwọn lẹnu iṣẹ wọn, ati pe ki gbogbo ohun ti wọn ba n ṣe nibẹ han si gbogbo ọmọ Naijiria. Nnkan bi ọsẹ diẹ sẹyin ni awuyewuye ṣiṣe owo baṣubaṣu jẹyọ ni ajọ ọhun, koda wọn fi ọwọ osi juwe ile fun adari ajọ naa tẹlẹ, Joy Nunieh. Ṣaaju ni igbimọ to n ri si ọrọ NDDC nile aṣoju-sofin ti kọkọ gbiyanju lati tu iṣu de isalẹ ikoko nipa ẹsun iṣowo baṣubaṣu ti wọn fi kan ajọ ọhun ni ibẹrẹ ọdun 2020. Ṣugbọn iwadii ọhun dojuru lẹyin ti awọn ti wọn fiwe pe lati NDDC jade kuro niwaju igbimọ naa pẹlu ibinu. Igbesẹ naa si ti mu ki igbimọ ọhun paṣe pe ki awọn agbofinro fi panpẹ ofin mu awọn adari ajọ ọhun, ki wọn lee wa sọ tẹnu wọn bi ọrọ owo naa ṣe jẹ. Sinimá oríta nílé aṣojú-sòfin, NDDC bínú jáde ní ibùdó ìwádìí Awọn adari ajọ Niger Delta Development Commission, NDDC ti jade kuro ni gbọngan ti ile igbimọ aṣofin kekere ti n ṣe iwadii owo to le ni biliọnu mọkanlelọgọrin naira. Ṣaaju ni igbimọ to n ri si ọrọ NDDC nile naa ti kọkọ gbiyanju lati tu iṣu de isalẹ ikoko nipa ẹsun iṣowo baṣubaṣu ti wọn fi kan ajọ ọhun laarin oṣu Kinni si oṣu Keje ọdun 2020. Alakoso fidihẹ fun ajọ naa, Kemebrandikumo Pondei, to ko awọn alabaṣiṣẹpọ rẹ lọ sibi iwadii ọhun sọ pe, alaga igbimọ oluwadi naa, Olubunmi Tunji-Ojo ko yẹ lẹni ti yoo dari iwadii naa nitori wọn ti fi ẹsun aṣemaṣe nipa ajọ ọhun kan oun naa ri. Ṣugbọn pupọ ninu awọn ọmọ igbimọ to n ṣe iwadii owo ọhun fesi pe, Pondei ko lẹtọ lati pa iru aṣẹ bẹẹ niwaju igbimọ ọhun. Wọn ni ko kọwe si ileeṣẹ ọlọpaa, tabi ajọ to n gbogun ti iwa jẹgudujẹra atawọn ajọ miran to n gbogun ti iwa ibajẹ, to ba ni ẹsun kankan lati fi kan Olubunmi Tunji-Ojo. Wo àwọn nkan tí ó yẹ kí o mọ̀ nípa Bitcoin, kí o tó ó dáwọ́ le e Nigeria Police recruitment 2020: Bí ó bá fẹ́ dara pọ̀ mọ́ ìṣẹ́ ọlọ́pàá, forúkọ́ sílẹ̀ níbí Bii sinima orita lo ri lẹyin ti awọn aṣoju ajọ NDDC naa jade kuro niwaju igbimọ iwadii ọhun, ti wọn si fi awọn oluwadii silẹ lori ijoko. Igbesẹ yii ko dun mọ igbimọ oluwadii naa ninu, eyi si ti mu ki wọn paṣe pe ki awọn agbofinro fi panpẹ ofin mu wọn, ki wọn lee wa sọ tẹnu wọn fun awọn ọmọ Naijiria lori bi ọrọ owo naa ṣe jẹ. 'Àrùn Coronavirus ló pá adarí ètò ìṣúná Àjọ NDDC ' Ajọ Niger Delta Development Commission ti kede pe arun Coronavirus lo pa adari eto isuna, Ibanga Etang. Owúrò Ọjọ́bọ̀, Ọjọ Kejidinlọgbọn, Oṣu Karun un ní àdarí ẹ̀ka ètò ìṣúná yóò jáde láyé. Ajọ Niger Delta Development Commission ti kéde pe òwúrò Ọjọ́bọ̀ ní àdarí ẹ̀ka ètò ìṣúná yóò jáde láyé. Ajọ naa ni awọn ẹbi lo fun wọn laṣẹ lati kede iku Ibang lẹyin ti ayẹwọ fihan pe o ni arun Coronavirus. Bakan naa ni ileeṣẹ eto ilẹra ni ijọba ipinlẹ Rivers ti kọ iwe si Ajọ NDDC lati si ajọ loju eegun iku to Etang. Nibayii, Ajọ naa ti wa paṣẹ ki awọn adari ni ajọ naa wa ni iyasọtọ bẹrẹ lati Ọjọ Iṣẹgun. Bakan naa ni Ajọ NDDC ti paṣẹ ki wọn bẹrẹ si ni wa gbogbo awọn to ti farakan adari eto isuna, Ibanga Etang to di oloogbe naa. Wo àwọn ìjọba ìbílẹ̀ 20 tí àrùn coronavirus pọ̀ sí jùlọ ní Nàìjíríà Ni ọjọ aje ni igbimọ apapọ lori gbigbogun ti ajakalẹ arun coronavirus lorilẹede Naijiria, PTF jade pẹlu awsn ilana tuntun ti aarẹ buwọlu fun didena itankalẹ arun COVID-19. Nibẹ ni wọn si ti ṣalaye wi pe awọn ti ṣe awari awọn ijọba ibilẹ ti arun Coronavirus ti fidimulẹ julọ lorilẹede Naijiria. Boss Mustapha akọwe ijọba apapọ to tun jẹ alaga igbimọ naa ṣalaye pe awọn ijọba ibilẹ bii ogun naa ni wọn ko ida bii ọgọta ninu ọgọrun iye arun coronavirus lorilẹede Naijiria. Awọn ijọ ibilẹ naa niwọnyii: Ìjọba àpapọ̀ kò tíì fi ìlànà ṣíṣí iléèjọ́sìn ránṣẹ́ sí wa-Ẹgbẹ́ Mùsùlùmí tó ga jù ní Nàìjíríà, NSCIA Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari ti paṣẹ fun awọn ile ijọsin lati si pada lọna ati jẹ ki ofin konile-o-gbele rọlẹ. Ajọ Nigerian Supreme Council for Islamic Affairs ti sọ wi pe awọn n rọ ijọba lati ri pe awọn n fin awọn ile ijọsin kaakiri ni ojoojumọ nitori awọn ile ijọsin ko ni owo lati se e. Eyi ko ṣẹyin aṣẹ aarẹ Buhari pe ki awọn ile ijọsin pada bẹrẹ si ni si fun awọn eniyan lọna ati jẹ ki ofin konile-o-gbele rọle si ni Naijiria. Akọwe Ajọ Nigerian Supreme Council for Islamic Affairs, Ọjọgbọn Ishaq Oloyede lasiko to n ba BBC sọrọ ni awọn ko ni owo lati ma a fin ileejọsin ni ojoojumọ nitori awọn kii gba owo ni ile ijọsin, wọn kan n lọ sin Olorun ni. Bẹẹ ni Oloyede ni awọn kii gba iranwọ lati ile okeere tabi abẹle lati fi se akoso awọn mọsalasi kaakiri orilẹede Naijiria nitori naa ni awọn ṣe n rọ ijọba lati ran awn lọwọ pẹlu oogun apakokoro. O fikun pe owo ti awọn eniyan ba fi ta wọn lọrẹ ni awọn fi n ṣakoso mọsalasi kaakiri Naijiria. Ṣe ofin ijinasiraẹni ko tako ẹsin Musulumi? Akọwe Ajọ Nigerian Supreme Council for Islamic Affairs, Ọjọgbọn Ishaq Oloyede ti ni ofin ijinasiraẹni lasiko arun Coronavirus ko tako ẹsin Musulumi. Ọjọgbọn Oloyede ni ẹsin Islam fagbaye gba yiyago fun araẹni ti o ba ma a mu inira dani. O ni Islam jẹ ẹsin ti ko fun ẹnikẹni ni inira ju ohun ti agbara rẹ gbe lọ, ko da wọn le e ṣẹ ẹsin ninu ile, ti wọn ba ṣe aisan, wọn le e dubulẹ kirun bo ba ṣe rọ wọn lọrun si. Ṣé ìjọba àpapọ̀ tí ṣí àwọn ìléèwé àti ilé ìjọsìn padà bí? Ijọba apapọ ni titpa lawọn ileewe yoo ṣi wa bayii nitori bi iye awọn to n ni arun naa ṣe n fojojumọ gogo sii lorilẹede Naijiria. Igbimọ amuṣẹya ti ijsba apapọ gbe kalẹ lori arun coronavirus lo sọ bẹẹ lasiko ifọrọwerọ rẹ pẹlawọn oniroyin. Igbesẹ naa si wa lara awọn igbesẹ to wa nilẹ eyi ti igbims naa ni, pẹlu ifọwọsi aarẹ muhammadu Buhari, ṣi n tẹsiwaju. Nigeria Lockdown Updates: Ẹ wo àwọn ìlànà tuntun tí ìjọba là sílẹ̀, ó ṣeéṣe kí ilé ìjọsìn, mọ́sálásí àti ọkọ òfurufú ṣí Ó ṣeéṣe kí ilé ìjọsìn, mọ́sálásí àti ọkọ òfurufú ṣí, Ẹ wo àwọn ìlànà tuntun tí ìjọba là sílẹ̀ Ìjọba orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ni àwọn ti wọ ipele kéji fún dídẹ ọkùn ìgbéle ni orílẹ̀-èdè Nàìjíríà báyìí. Alága ìgbìmọ̀ amúṣẹ́ṣe lórí ààrùn coronavirus lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà tó tún jẹ́ akọwé ìjọba àpapọ̀ Boss Mustapha ló kéde èyí lásìkò tó n jábọ ibi abáṣẹ́dé lorí Covid-19 lọ́sàn òní nílùú Abuja. Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, ipele kejì yìí yóò wà fún ọ̀sẹ̀ mẹ́rin láti ọjọ́ kejì oṣù kẹfa sí ọjọ́ kọkàdínlọ́gbọ̀n oṣù kẹfà, ọdún 2020. Mustapha ni óṣeéṣe kí àwọn ilé ìjọsìn ṣí bótilẹ̀ jẹ́ pé kò ni sí ìpíjọpọ̀ to ju ogún èèyàn lọ níbikíbi to ba yàtọ̀ si ibi iṣk àti ilé ìjọsìn. Àwọn ǹkan míràn ti yóò tún wáyé lásìkò ipele kejì yìí rèé. Ní báyìí orílẹ̀-èdeè Nàìjíríà ti ní èèyàn tó lé ni ẹgbẹ̀run mẹ́wàá tó ti ni ààrùn Covid-19 tí èǹiyàn to lé ni ẹgbẹ̀rún mẹ́ta ti móríbọ́ ti àwọn to lé ní igba sì ti báa lọ Ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ Nàìjíríà fẹ́ kí Ààrẹ Buhari ṣí wọn sílẹ̀ kúrò lọ́wọ́ òfin kónílé -ó-gbélé President Buhari speech today: Ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ Naijiria fẹ́ kí Ààrẹ Buhari ṣí wọn sílẹ̀ kúrò lọ́wọ́ òfin kónílé -ó-gbélé Nibayii, a n reti ohun ti aarẹ Buhari yoo kede lọni lẹyin ti Ajọ amuṣẹya aarẹ lori arun Coronavirus, PTF fi lede wi pe awọn ti jiyin fun aarẹ lori bo ṣẹ n lọ ni Naijiria ati amọran fun aarẹ Buhari boya ki ofin konile o gbele tẹsiwaju abi ko dopin. Ọjọ Ajẹ, ọsẹ yii lo pe ọṣẹ kẹrin ti irọlẹ ofin konile o gbele bẹrẹ ni Naijiria, amọ ofin naa si de irinna lati ipinlẹ kan si omiran. Amọ, ọpọlọpọ awọn ọmọ Naijiria to fi ẹrọ wọn lede loju opo BBC Yoruba lori Facebook ti kesi aare lati tu awọn silẹ lọwọ ofin konile-o-gbele ti yoo pari loni. Awọn to fi ero wọn han naa sọ wi pe awọn fẹ ki awọn nkan pada si bi o ti wa tẹlẹ ki arun Coronavirus to bẹ silẹ ni Niajiria. Lara awọn to fi ero wọn lede ohun sọ pe iya ati iṣẹ ti poju lawujọ lasiko arun Coronavirus yii, nitori naa ki ijọba fi wọn silẹ lati wa ounjẹ ojo wọn. Awọn miran ti lẹ sọ wi pe ki aarẹ jẹ ki ileewe ṣi, ki awọn olukọ le pada si ẹnu iṣẹ, ki awọn ti wọn ti kuna iṣẹ wọn nitori arun Coronavirus naa le ri iṣẹ. Amọ awọn to fẹ ki ofin konile o gbele o tẹsiwaju ko po to awọn to fẹ ki ofin naa di ohun ana. Awọn kan ti lẹ sọ pe ko si eleyii to kan awọn, nkan to ba wu aarẹ Buhari nitori awọn ko ni igbagbọ ninu rẹ mọ. Amọ loju ẹrọ ikansiraẹni Twitter, awọn elomiran n bere idi ti ijọba ṣe jẹki ofin konile-o-gbele rọlẹ nigba ti iye awọn to ti ni arun Coronavirus n peleke si ni Naijiria lojojumọ.",0,yoruba "ibile. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Wọ́n kọ̀ wọn kò fèsì nítorí kò sí àwọn agbẹ́jọ́rò wọn níkàlẹ̀ , wọ́n sì dá wọn padà sí àtìmọ́lé , kí ọjọ́ 18 tí a dá fún ìgbẹ́jọ́ ó kò .",0,yoruba International Nurses Day 2021: Wo ìpèníjà àti àǹfàní inú iṣẹ́ nọ́ọ̀sì- Adetokunbo Shaba,0,yoruba "Alaga fun ẹgbẹ oṣelu All Progressive Congress nigba kan ri, Adam Oshiomhole sọ fun aarẹ tẹlẹ lorilẹede Naijiria, Goodluck Jonathan pe oun ditẹ iṣejọba rẹ nitori ọrọ ọselu. Oshiomhole sọ ọrọ yii nigbati o darapọ aarẹ tẹlẹ naa nibi ayẹyẹ iranti ọdun kan ti Idahosa Okunbo jade laye niluu Abuja. O ni Jonathan fi ipa rẹrẹ silẹ gẹgẹ bi Aarẹ sugbọn oun tako ijọba Jonathan rẹ nitori ija oṣelu. "" Ipa ti aarẹ ti fisilẹ, a ko le ri ẹni ti yoo ṣe bi Aarẹ Jonathan. “Gẹgẹ bi a ṣe mọ ọrọ oṣelu, angẹli gan ma fidi rẹmi nigba mii ṣugbọn Aarẹ ṣe isẹ takuntakun ti awọn yoku to tẹlẹ wọn gbọdọ wo awukọṣe wọn. “Ninu iṣejọba yii, ẹ kọ ile iwe fun awọn Almaijiri, nigbati ẹ ro pe ko yẹ ki awọn ọmọ orilẹede Naijiria kankan wa lori titi, ki wọn ma ni anfani si ile ẹkọ. “Gbogbo awọn erongba yii ni ko jẹ tuntun sugbọn a padanu ẹmi lati ṣe isẹ naa. “A ko lo ṣe iyato laarin ọta ati ọrẹ, o di igba ti a ba ku. “A ki mọ iyi eeyan afi ti ko si lara wa mọ.” Aarẹ tẹlẹ lorilẹede Naijiria, Goodluck Jonathan ti rọ awọn ọmọ orilẹede Naijiria lati yago fun awọn oloṣelu ti ko fẹran ilu, ti wọn yoo fi owo ra ibo ninu eto idibo ti yoo waye lọdun 2023. Jonathan sisọ loju ọrọ yii nigbati o darapọ awọn mọlebi Okunbo nibi bi ayẹyẹ iranti ọdun kan ti Idahosa Okunbo jade laye niluu Abuja Aarẹ tẹlẹ wa rọ awọn eeyan pe ki wọn ro ọjọ ọla awọn ọmọ wọn ti wọn ba ti fẹ yan awọn oludari fun eto iṣejọba, ti wọn si ma jẹ ki ẹnikẹni gbe ẹtọ wọn lọwọ wọn ninu eto idibo orilẹede Naijiria lọdun 2023. “Saaju eto idibo ọdun 2023, awọn oloṣelu to wa ipo kan, ti setan lati fi ipologo ba wa sọrọ. “Sugbọn erongba wa ju ọdun 2023 lọ, Nkan ti o kan ju ni bi orilẹede Naijiria yoo ṣe ri adari ti yoo mu tẹsiwaju lati bọ si ipo to ye ko wa ni awujọ awọn orilẹede ile adulawọ yoku, Imọran mi fun awọn eeyan ni wọn ọjọ ọla awọn ọmọ won ti wọn ba ti  n dibo lati yaa adari tuntun. “Ani lati yago fun awọn oloṣelu fẹranjẹkọ, ti wọn fẹ fi birẹdi tan awọn eeyan jẹ, ki a si ri pe a ko yan awọn oloṣelu ti wọn yoo ba ọjọ ọla jẹ fun awọn ọmọ wa ati arọmọdọmọ wa “A gbọdọ ri pe a yan oloṣelu ti yo fi itan to da silẹ, ti yoo si mu alaafia ati ifọkanbalẹ wa si orilẹede Naijiria.”",0,yoruba "Seyi Makinde ti ẹgbẹ́ òsèlú PDP ní àwọn ènìyàn dìbò yàn gẹ́gẹ́ bí gómìnà tuntun ní ìpínlẹ̀ Ọyọ. Ajimobi ninu atẹjade to fi lede ni gbogbo isẹ Makinde lo n fihan wi pe, o fẹ fi ọwọ rọ gbogbo isẹ ti oun ti se fun ọdun mẹjọ ni ipinlẹ Ọyọ. Ninu ọrọ rẹ, o ni ẹgbẹ oselu PDP yẹ ki wọn bẹrẹ si ni sọ ohun ti wọn ni fun awọn eniyan, ati lati mọ le akasọ lori awọn ipinlẹ ti oun ti fi silẹ gẹgẹ bi isẹ ti oun ti se. Kidnapped Girl: Iyá Ikimot ní lẹ́yìn ọ̀pọ̀ ìdààmú àti owó láti wá ọmọ náà, òun sọ ìrètí nù O ni ohun to buru jai ni lati ma a lo ẹrọ ayelujara lati fi tabuku oun lawujọ. Gomina ipinlẹ Ọyọ naa wa parọwa fun wọn lati dawo gbogbo ise yii ku, ki ipinlẹ Ọyọ le tẹsiwaju.",0,yoruba ẹ bá n gún un kó fẹ́lẹ́ kí ẹ fi ṣara rindin,0,yoruba ni ara eni lo ni ẹ̀ká àwẹ eyti o gbe lori iwa rere.,0,yoruba "Olisah Metuh n jẹjọ nitori owo ipolongo ibo to gba lọwọ PDP Ni kete ti adajọ Okon Abang to n gbọ ẹjọ naa foju kan Ọgbẹni Metuh lori ibusun alaisan ti wọn fi gbe wa lati ile iwosan lo ba kaanu rẹ, to si sun igbẹjọ naa siwaju. Agbẹjọro fun Olisa Metuh, Agba amofin Onyeachi Ikpeazu lo kọkọ bẹ ileẹjọ pe ko sun igbẹjọ naa siwaju lasiko tigbẹjọ naa waye losu kinni ọdun yi. Olisa Metuh yi si lo ti gbe iwe to gba latọdọ dokita to n tọju rẹ kalẹ fun ileẹjọ wipe ara oun ko da. Igun Olupẹjọ ri iwe dokita Metuh bii ọ̀na lati sa lọ Nigba to n fesi lori iwe yi, agbẹjọro fun igun olupẹjọ, Sylvanus Tahir, rọ ileẹjọ lati wọgile oniduro Metuh ti wọn gba, ko si ri aiyọju Metuh sile ẹjs gẹgẹ bii ete lati sa lọ. Ninu idajọ rẹ, Ọgbẹni Abang fi idaniloju han pe iwe ti dokita fọwọsi pe ara Metuh ko ya yi to, lati gba ẹbẹ. Amọ sa, Adajọ Abang ni ko si ẹri kankan lati fi idi rẹ mulẹ pe iwe ọhun jẹ ojulowo lati ọdọ dokita kankan. Ọpọlọpọ eeyan si lo ti n sọrọ Metuh yi lori awọ̀n oju opo ayelujara:",0,yoruba Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó ṣe pàtàkì. (Item 199),0,yoruba kòkòrò àrùn Kòrónà láti má wọ orílẹ̀ - èdè Nàìjíríà .,0,yoruba Ọ̀pọ̀lọpọ̀ iléeṣẹ́ agbóhùnsáfẹ́fẹ́ — tí àwọn ènìyàn fẹ́ràn fún ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ìròyìn tí kò figbákanbọ̀kan ní Burundi — ni a ṣán pa .,0,yoruba "Ó l'óhun tí a wá ṣe ní yàrá, jẹ́ k'á bẹ̀rẹ̀!"""""""""""""""" - ní ohùn Fẹlá Aníkúlápó Kútì.",0,yoruba bi olopa ba mu e o ni ètó láti mo ìdí ti won fi mu e tàbí èsè re ni warensesa,0,yoruba "Bill Gates ati iyawo rẹ, Melinda lo da ajọ naa silẹ Abajade naa ti wọn pe orukọ rẹ ni 'Goalkeepers Report' ti ọdun 2018 ni ebi, iku awọn iyalọmọ, iku ọmọ ọwọ ni o jẹ oun ti ko jẹ ki igbe aye ni orilẹede Naijiria muna d'oko. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: OsunDecides: Omisore ní ẹni tó bá fẹ́ ra ìbò, àwọn yóò lọ lásọ mú ni Abajade naa ni nigba to ba fi maa di ọdun 2050, awọn akuuṣẹ eniyan bi miliọnu mejilelaadọjọ (152 million) ni yoo wa ni orilẹede Naijiria ninu awọn eniyan bi ọgbọnlenirinwo miliọnu (429 million) ti yoo maa gbe orilẹede yii ni ọdun naa. Bill Gates ni ọdun mẹtalelaadọta ni ọpọ ọmọ Naijiria nku Abajade naa ni nitori orilẹede Naijiria ko kọbi ara si idagbasoke ọmọ eniyan ni yoo fa ti iṣẹ yoo fi pọ ni orilẹede naa. Ajọ ti o ṣe iwadi lati gbe abajade naa sita, ti Bill Gates ati iyawo rẹ Melinda da silẹ lo ti n ṣe afihan ọrọ iṣẹ ati iya ni agbaye lati ọdun 2000. Laarin ọdun 2000 titi di iwoyi, bi biliọnu kan eniyan ni ajọ naa ni o ti bọ lọwọ iṣẹ ni agbaye, ṣugbọn o jọ bi ẹni pe, ni Afrika, iṣẹ ati iya ni pọ si ni. 'Ilé ìwòsàn ṣi abẹ́rẹ́ Formalin gún mí; n kò lè dá ìgbẹ́ àti ìtọ̀ dúró mọ́' Ò sòro láti bímọ sí Nàíjíríà - Bill Gate Ẹ o ranti wipe, ni oṣu kẹta ọdun 2018 ni Ọgbẹni Bill Gates sapejuwe ilana imupadabọsipo ati agbega ọrọ aje tijọba apapọ dawọle gẹgẹ bii eyiti ko ba aini awọn araalu pade. Bakanaa lo ni ko ba san fun orilẹede Naijiria ju bayi lọ, to ba jẹ pe o dokoowo pupọ lẹka eto ẹkọ ati ilera, dipo kijọba maa dojukọ ipese awọn ohun eelo taa lee fojuri, eyi to nsakoba fun idagbasoke ọmọniyan. Gates si asọ loju ọrọ yii pẹlu alaga ajọ alaanu Dangote, Alhaji Aliko Dangote, nibi akanse ipade igbimọ awọn eleto aje lorilẹede yii eyi to waye ni gbọngan apejẹ to wa nile ijọba nilu Abuja. Akori ipade naa, eyiti igbakeji aarẹ Yẹmi Ọsinbajo dari rẹ ni ""idokowo ninu agbega ọmọniyan lati se atilẹyin fun afojusun idagbasoke ọrọ aje awọn mẹkunnu"" Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Awọn gomina mẹrẹẹrindinlogoji to wa lorilẹede yi pẹlu awọn minisita tọrọ aje kan, ati gomina banki apapọ ilẹ wa lo jẹ ọmọ igbimọ naa. Bill Gates ni, ""Orilẹede Naijiria jẹ ara awọn orilẹede to lewu julọ lati bimọ lagbaye, nitori ilẹ wa lo nse ipo kẹrin lọwọlọwọ lagbaye, taa ba nsọrọ iku awọn iyalọmọ, to si n lewaju orilẹede Sierra Leone, Central African Republic ati Chad. Koda, ọkan ninu mẹta awọn ọmọde ni Naijiria ni ko ri ounjẹ asara loore jẹ."" Bill Gates ati Aliko Dangote rọ Buhari lati dokowo ninu araalu ""Ni awọn orilẹede towo to nwọle fun wọn ti gbe pẹẹli, ọjọ ori ọpọ awọn eeyan ibẹ ki wọn to ku, maa nwọ ọdun marundinlọgọrin, lawọn orilẹede ti owo to nwọle fun wọn ko ti gbewọn to bẹẹ, ọjọ ori ọpọ wọn ki wọn to ku maa nwọ ọdun mejidinlaadọrin sugbọn lorilẹede Naijiria, ọdun mẹtalelaadọta lọpọ ọmọ Naijiria ndagbere faye."" O wa daba pe ipese awọn ohun eelo amayedẹrun gbọdọ maa lọ nifẹgbẹ-kẹgbẹ pẹlu eto idokowo ninu awọn araalu eyiti yoo mu ki ọrọ aje tọjọ.",0,yoruba "joko, Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìwà: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn.",0,yoruba ni ìwájú. Ọmọ lo ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.,0,yoruba ìwúrí ló jẹ́ fún mi ní òwúrọ̀ yìí o ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ìwé ìròhìn ni wọ́n gbé àwòrán awọn ọmọ wa yọ,0,yoruba .@user ati Erelu Bisi @user ni ile ibugbe ijoba @user https://t.co/XfObYk17WM,0,yoruba "yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Oṣu mẹfa ni iyanṣẹlodi naa fi waye Ijọba sọ pe oun yoo san owo naa diẹdiẹ laarin oṣu Karun-un ọdun 2021 si oṣu Keji, ọdun 2022. Nibi ipade ti awọn aṣoju ijọba ati awọn adari ẹgbẹ awọn olukọ fasiti, ASUU, ti aarẹ wọn, Ọjọgbọn Biodun Ogunyemi, ṣe ni alẹ Ọjọbọ ni wọn ti kede eyi. Gẹgẹ bi iwe iroyin Punch ṣe jabọ, ijọba tun ṣelelri lati na biliọnu lọna ogun Naira, lati fi ṣe atunṣe eto ẹkọ ni Naijiria. Gbogbo igbesẹ yii ni ireti wa pe yoo fi opin si iyanṣẹlodi oṣu meje ti ẹgbẹ ASUU wa lori rẹ. Chris Ngige, Minisita fun ọrọ oṣiṣẹ ni Naijiria Ṣaaju ni iroyin sọ pe Minisita fun ọrọ awọn oṣisẹ ni Naijiria, Chris Ngige sọ pe iyanṣẹlodi naa fi aaye silẹ fun awọn oluwọde End Sars lati ma a lo awọn akẹkọọ fun iwọde naa. End SARS, End SWAT: Ó pé mi bí SARS kò ṣe sọ mí dolówọ́- Fulani Kwajafa Ngige sọ pe lati bi ọsẹ kan ni ijsba ti n ṣiṣẹ lati fi opin si iyanṣẹlodi naa, to si sọ pe adura awsn ni pe ki ipade ti wọn ṣe naa so eso rere.",0,yoruba Femi Fani-Kayode: Iléèwòsàn Kubwa l'Abuja wú ẹ̀rí sítà tó fihàǹ pé FFK parọ́,0,yoruba igboro ti daru eni wo ankara lo ma je semo,0,yoruba eḳọ nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba àkerekere. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba "Gẹgẹ bi akọsilẹ to wa lori ayelujara itakun agbaye ijọ CCC Genesis Global ṣe sọ, oun ni ijọ Celestial to tobi julọ, to si n yara dagba soke julọ ni agbaye. Eeyan to le ni ẹgbẹrun mẹta lo ma n jọsin ninu ijọ naa ninu isin ọjọ Aiku. Oludasilẹ ijọ naa, Alufaa Isreal Oladele Ogundipe, ni Oluṣọ ijọ naa. Lẹyin rẹ, awọn oludari ati iranṣẹ Ọlọrun mejidinlogoji lo tun wa lẹyin rẹ. Awọn ọkunrin ọlọla Eyi ni ẹgbẹ awọn ọkunrin to n jọsin ninu ijọ CCC Genesis Global. Ohun ti wọn n ṣe ninu ẹgbẹ naa ni lati ma a kọ ara wọn ni ẹkọ lati jẹ ọkunrin gidi, gẹgẹ bi ọkọ, baba, oṣiṣẹ inu ijọ ati adari. Ile ijọsin awọn ọmọde Ibi yii ni awọn ọmọ wẹwẹ ati ọdọ ti ọjọ ori wọn wa labẹ ọdun kan si ọdun mẹtadinlogun ti ma n jọsin. Ẹgbẹ awọn woli ọkunrin ati obinrin Awọn wọnyii ni ariran, agbẹnusọ, iranṣẹ, oluṣọ. Ati aṣoju ninu ijọ naa, to ma n fi adura jagun. O jẹ akojọpọ awọn awọn woli to ma n sọ asọtẹlẹ, awọn to ma n la ala, ariran ati awọn to ma n fi ede oriṣiriṣi sọrọ. Ẹgbẹ awọn ọmọ Sioni Ẹka yii ni ti iṣẹ iranṣẹ awọn obinrin inu ijọ. Ikorajọpọ wọn ni lati ma a kọ awọn obinrin lati dagba ninu ẹmi. Awọn obinrin ti ọjọ ori wọn bẹrẹ lati ọdun mejidinlogun soke lo wa ninu ẹgbẹ naa. Ẹgbẹ awọn aladura Awọn wọnyii lo ma n fi adura jagun fun awọn ọmọ ijọ naa, ati ẹnikẹni to ba fi ẹbẹ adura ranṣẹ sinu ijọ naa. Ẹka igbani nimọran Awọn to wa ninu ẹgbẹ yii lo ma n gba awọn ọmọ ni imọran lori lori ohunkohun ti wọn ba n la kọja. Awọn aṣọna Awọn wọnyii lo ma n duro ni awọn ẹnu ọna to wọ inu ṣọọṣi naa. Lara wọn lo tun ma n tun pẹpẹ ile ijọsin ṣe, ti wọn si tun ma n gba ọrẹ. Yatọ si awọn ti a ka silẹ yii, awọn ẹka oriṣiriṣi lo tun wa ninu ijọ CCC Genesis Global, to ma n ko ipa lasiko isin. Awọn akọrin-Ẹka awọn to n mojuto igbohunsafẹfẹ eto isin ninu ijọ naa. Awọn lo ma n ya aworan ati fidio ti isin ba n lọ lọwọ, ati amojuto iṣẹ iranṣẹ ori amohunmaworan ijọ naa. Ẹgbẹ awọn olukini -Awọn eeyan to ma n ki awọn alajo kaabọ sinu ijọ naa. Ẹgbẹ awọn olufifunni -Awọn to wa ninu ẹgbẹ yii lo ma n ṣoju ijọ lati fun awọn ọmọ ijọ ti ko ni i, ni ounjẹ, owo ati aṣọ. Wọn tun ma n ṣeto fifun awọn alaini awujọ ni iranlọwọ loṣooṣu. Ẹgbẹ eleto ilera - Eyi ni ẹgbẹ awọn onimọ iṣegun oyinbo to ma n tọju awọn alaisan lasiko iṣẹ iranṣẹ ilera ọfẹ, ati ẹnikẹni to ba nilo itọju lasiko ti isin n lọ lọwọ. Awọn eleto aabo - Ojuṣe awọn to wa ni ẹka yii ni lati daabo bo ile ijọin, awọn oṣiṣẹ ati awọn olujọsin ati dukia wọn, lọwọ ole, ati awọn iṣẹlẹ buruku miran. Ikọ awọn alatunṣe - Awọn to wa ninu ikọ yii lo ma n tun inu ati ayika ile ijọsin ṣe lasiko ijọsin ati lẹyin rẹ. Awọn olubẹwo - Awọn eeyan yi lo ma n ṣe amojuto awọn to ba ṣẹṣẹ darapọ mọ ijọ CCC Genesis Global. Wọn si tun ma n bẹ wọn wo lẹyin rẹ. Awọn ajihinrere - Awọn to wa ni ẹka yii lo ma n kede ihinrere kaakiri lati jere ọkan fun Jesu.",0,yoruba "A ò bá à ṣ’aájò gbékúdè ẹgbẹ̀rún ọdún, yóò ku ọjọ́ kan. Bí òwe àgbà “ìgbà wo ni Mákùú ò ní kú!” #Yoruba",0,yoruba "RT @user: """"""""""""""""""""""""""""""""@user: Ọmọ ìyá mi"""""""""""""""""""""""""""""""" da??",0,yoruba Doctors‘ Strike: Àwọn dókítà tó ń woṣẹ́ níran ní UCH sọ̀rọ̀ lórí ẹ̀dùn ọkàn wọn,0,yoruba "ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba Ọlọ́pá YouTube naa ní ègé olóótọ fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí.,0,yoruba òní nu ọjọ́ ìtàn ìlú abẹ́òkúta lórí ìkànnì pẹ̀lú oluwafemi ọmọ makinde ́òkúta bbcnewsyoruba yoruba,0,yoruba àgbà ri pe jẹ́ pàtàkì wey ti o nuni ti o dun.,0,yoruba "Elisha Abbo Adajọ ile ẹjọ naa, Abdullahi Ilellah sọ wi pe awọn oniduro rẹ mejeeji gbudọ ni adirẹsi ile ti wọn n gbe ni Abuja pẹlu aridaju. Adajọ Ilellah wa sun ẹjọ naa siwaju di ọjọ ikejilelogun oṣu keje ọdun yii. Gbogbo igbiyanju ati jẹ ki ekuru ọrọ Sẹnetọ Elisha Abbo to lu obinrin abilekọ kan ni ile itaja eroja ibalopọ ni ilu Abuja tan lawo, pabo lo ja si tori ọrọ rẹ ti de ile ẹjọ bayii. Gẹgẹ bi igbakeji Supretendenti to tun jẹ agbẹnusọ ọlọpaa, Anjuguri Manzah ṣe fi aridaju rẹ han fun akọroyin BBC to ba a ni gbolohun lori ẹrọ ibanisọrọ, wọn ti gbe e lọ si ile ẹjọ. Ṣugbọn Anjuguri ko fẹ ṣafihan orukọ ile ẹjọ ti wọn gbe e lọ. Ṣaaju eyi naa ni ọpọlọpọ eekan oloṣelu ti kọwe si ile iṣẹ ọlọpaa ti awọn naa ko si jafinra lori iwadii ọrọ naa. Ọjọ Iṣẹgun ọjọ ikeji oṣu keje ni fidio iṣẹlẹ kan to ti ṣẹlẹ ṣaaju ọjọ naa jade to ṣafihan bi Sẹnetọ naa ṣe n lu obinrin kan nile itaja eroja ibalopọ. Fulani Kidnapping: Owó púpọ̀ la san kí wọ́n tó fi mi sílẹ̀ Bo tilẹ jẹ wi pe Elisha ti tọrọ aforijin pe ""Ẹ má bínú, mo kábàmọ́ pé mo na obìnrin -Elisha Abbo"" lọwọ awọn ọmọ orilẹede Naijiria, awọn abiyamọ, ati obinrin to na pe ki wọn fi ori ji oun, oun ko ni hu iru iwa aidaa bayii mọ, o f da bi ẹni pe eyi ko ta leti awọn ọmọ Naijiria. Abbo, to ni ọmọ kii mọ ẹkọ jẹ ko ma ra lọwọ, tun tọrọ aforijin lọwọ ijọ Ọlọrun lagbaye lori iwa aidaa ti oun hu yii, nitori o ni gẹgẹ bii asoju Kristi, iru iwa yii ko tọ si oun. Awọn eniyan ni awọn gba pe o tọrọ aforiji o ṣugbọn bi ofin ba ti tọwọ bọ ọrọ, ko si pẹlẹ ma binu labẹ ofin. CAN: Samson ni ọrọ awọn ajinigbe ti gba àpérò ní Naijiria",0,yoruba Àwọn agbébọn tún gbẹ̀mí àlùfáà ìjọ Àgùdà míì ní Edo,0,yoruba "Suleiman Hashimu lo ọjọ́ méjìdínlógún fi rin ọ̀nà Èkó sí Abuja, bàtà bíi mẹ́fà ló já mọ́ ọ lẹ́sẹ̀ kí ó tó dé ọ̀hún. #Nigeria",0,yoruba Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó ṣe pàtàkì. (Item 134),0,yoruba "2023 Presidential Election: Ajulo ní ó ti ń rúgbó bọ̀ láàrin Tinubu àti Osinbajo, àwọn àgbà Yorùbá kò gbọdọ̀ wòran",0,yoruba "Agbẹjọro fun ijọba, Akin Onigbinde lo sọ ọrọ naa niwaju adajọ Mashud Abass, nibi igbẹjọ to n lọ lọwọ lori họwuhọwu to bẹ lẹyin idaduro awọn alaga ọhun. O ni ijọba ti pinnu pe ki wọn lọ yanju ọrọ naa laarin ara wọn, ki alaafia lee jọba nipinlẹ Oyo. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Onigbinde sọ fun adajọ naa pe, wọn yoo pada si ile ẹjọ ti wọn ba kuna lati pari aawọ laarin ara wọn. Ṣugbọn awọn agbejọro fun awọn alaga ijọba ibilẹ ti wọn da duro, Niyi Akintola ati Kunle Sobolaju sọ pe, igbesẹ yii ko tẹ awọn lọrun. Wọn ni ile ẹjọ gbọdọ da ẹjọ naa nu, ki wọn to lee pari aawọ naa ni itubi inubi. Lẹyin atotonu awọn agbẹjọro mejeji, adajọ Mashud Abass ki awọn agbẹjọro ku iṣẹ takuntakun, to si ni ki wọn lọ yanju ẹjọ naa laarin ara wọn, ki wọn si tun ri daju pe alafia jọba nipinlẹ Oyo. Female Genital Mutilation Day: Ọ̀mọ̀wé kan ní obìnrin tí kò bá dá abẹ́ yóò ṣe ìṣekúṣe Ile ẹjọ ọhun wa sun ẹjọ naa si ọjọ kejila Oṣu Keji ọdun 2020, lati mọ ibi ti ọrọ de duro, bi bẹẹkọ, oun yoo tẹsiwaju lati gbọ ẹjọ naa. Ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu Karun un ọdun 2019 ni gomina Seyi Makinde yọ awọn alaga ijọba ibilẹ naa bi ẹni yọ jiga, to si yan awọn alaga fidihẹ. Sugbọn awọn alaga naa fẹ fi tipatipa pada ṣẹnu iṣẹ eyi to da rogbodiyan silẹ.",0,yoruba Ẹ nlẹ́ o ẹ̀yin ará mi. Ẹ kú ọjọ́ gbọgbọrọ bí ọwọ́ aṣọ.,0,yoruba "Eyi ko ṣẹyin ipade to waye laarin Minisita fun eto Ẹkọ,Malam Adamu Adamu ati awọn kọmisọnna fun eto Ẹko ni ilu Abuja. Iroyin ni aṣẹ naa ko ṣẹyin ipade ati atilẹyin lati ọdọ awọn gomina ipinlẹ, adari ileewe, awọn adari awọn akẹkọọ ati awọn akẹkọọ. Wọn ni gbogbo wọn fi ọwọ si wi pe ki awọn ileewe ṣi pada kaakiri Naijiria. Akọwe agba fún ilé iṣẹ́ eto Eko ni Naijria lo fi idi ọrọ naa mulẹ Amọ, ijọba ni gbogbo awọn akẹkọọ ati olukọ lo gbọdọ tẹle awọn ofin to rọmọ didẹkun itankalẹ arun Coronavirus lorilẹede Naijiria. À ó ṣe àtúngbéyẹ̀wò àsìkò ìwọ́le àwọn akẹ̀kọ̀ọ́-Ìjọba apapọ̀ Ìjọba àpàpọ̀ ni ni òun yóò ṣe àtúngbéyẹ̀wò àsìkò ìwọ̀lé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ní Nàìjíríà. Sáájú ni ìjọba ti ní àwọn akẹ́kọ̀ọ́ yóò padà sílé ìwé ni ọjọ́ kejìdílógun, oṣù kíní ọdún 2021, sùgbọ́n ojoojúmọ ni ààrùn Coronavirus n péleke sí. Mínísítà fún ètò ẹ̀kọ́, Adamu Adamu ló sọ èyí di mímọ lásìkò tó n dáhùn ìbéèrè àwọn akọròyìn níbi ìpàdé àwọn oníròyìn ti ìgbìmọ̀ amúṣẹ́ ṣe lórí Covid-19 ti ààrẹ yan nílùú Abuja. Mínísítà ní "" Lórí ìwalé ọjọ́ kejìdílógún, a ó ṣe àtúngbéyẹ̀wò rẹ̀."" A tí sọ níbi ìpàdé PTF tí a ṣe lónìí, tó bá di ọ̀la, ilé iṣk ètò ẹ̀kọ́ yóò mọ ìgbésẹ̀ tó kù."" Sáájú àsìkò yìí ni ìjọba ti kéde pé, kí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ní gbogbo ipele padà sí ilé ẹ̀kọ́ ni ọjọ́ kejìdínlógún , oṣù kíní ọdún 2021. Lagos School resumption: Ìpínlẹ̀ Eko kéde ọjọ́ tuntun Jan. 18 fún ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Ijọba ipinlẹ Eko ti pada kede ọjọ kejidinlogun oṣu kini ọdun 2021 gẹgẹ bii ọjọ iwọle tuntun fun awọn akẹkọọ fun saa eto ẹkọ keji. Atẹjade kan ti ileeṣẹ eto ẹkọ ni ijọba ipinlẹ Eko, fi sita ṣalaye pe kọmiṣọna eto ẹkọ nipinlẹ Eko Arabinrin Fọlaṣade Adefisayọ lo kede eyi ni ""ibamu pẹlu aṣẹ ati idari ijọba apapọ ati ọwọja ọwọ keji ajakalẹ aarun COVID-19 to n ja lọwọlọwọ."" ni opin ọsẹ to kọja ni ijọba ipinlẹ Eko ti kọkọ kede pe gbogbo awọn ileewe alakọbẹrẹ ati girama ko ni lee wọle bayii ayi pe iwọle wọn di ọjọ mii ọjọ ire. O wa rọ awọn ileewe lati ṣeto aye to tọ fun awọn akẹkọọ tabi olukọ ti ara wọn ko ba ya lati maa kọ ẹkọ tabi ṣiṣẹ wọn lati ile nipasẹ ayelujara iyẹn, ""Virtual learning"" tabi ""Virtual work"" Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi",0,yoruba "Wo awọn oju obinrin ti wọn le di minista lẹyin ayẹwo ile igbimọ aṣofin to n lọ lọwọ Lọjọ Iṣẹgun ni Aarẹ Mohammadu Buhari fi orukọ awọn minista mẹtalelogoji ranṣẹ sile igbimọ aṣofin ni AbujaDalung, Audu Ogbe, Shittu Adebayo àti Isaac Adewole kò wọlé. Ninu orukọ awọn mẹtalelogoji ti Buhari fẹ ki ile igbimọ ṣe ayẹwo fun, o yani lẹnu pe obinrin meje pere ni o wa ninu orukọ mẹtalelogoji naa. Eyi ja si pe ida mẹrindinlogun ninu ọgọrun un pere ni abo to maa ba ijọba Buhari ṣiṣẹ ni saa keji ijọba rẹ yii. Bẹẹ naa lo ṣe jẹ pe obinrin mẹfa pere naa lo ṣe minista pẹlu aarẹ Buhari ni saa iṣejọba rẹ akọkọ ninu awọn minista mẹrindinlogoji to yan nigba naa. Eyi ja si pe ida mẹrindinlogun naa ni o tun n tun fẹ lo lasiko yii. Bi awọn ọmọ ile igbimọ aṣofin ṣe ni ki awọn kan foribalẹ ki wọn maa lọ naa ni wọn beere ibeere lọwọ awọn miran. Leyin eyi ni ijọba aarẹ Buhari ṣeto ipagọ idanilẹkọọ ọlọjọ meji fawọn ti wọn fẹ yan naa. Awọn obinrin meje ti orukọ wọn pada wọnu iwe awọn tile igbimọ n ṣayẹwo fun ni: 1) Pauline Tallen: Labẹ ijọba Oluṣẹgun Obasanjọ, Baba Iyabọ ni arabinrin Pauline ti kọkọ ṣiṣẹ pọ. O jẹ ọmọ ọgọta ọdun oloṣelu lati ipinlẹ Plateau. Pauline ni obinrin akọkọ to jẹ igbakeji gomina ni ariwa Naijiria Pauline lo ṣe minista abẹle fun ileeṣẹ ijọba to n ri si imọ sayẹnsi ati imọ ẹrọ lọdun 2007. Oun ni igbakeji gomina ipinlẹ Plateau ko to o tun dije dupo gomina ipinlẹ naa lọdun 2011 ki Jonah Jang to jawe olubori. O ka ẹkọ nipa imọ ẹda ni fasiti Jos. O bẹrẹ oṣelu rẹ pẹlu ẹgbẹ PDP ko to ṣi lọ si ẹgbẹ oṣelu APC 2) Mariam Katagun: Mariam Katagun ti jẹ aṣoju Naijiria si ajọ iṣokan agbaye ni eto ẹkọ ati àṣà UNESCO. Ipo yii lo di mu titi di oṣu kẹfa, ọdun 2009. Oun ni igbakeji oludari nileeṣẹ ijọba to n mojuto eto ẹkọ ko to lọ gba iṣẹ akọwe agba ni UNESCO lọdun 2001. Fasiti Ahmadu Bello lo ti kẹkọọ gboye ko to lọ gba iṣẹ ọkan lara awọn igbimọ Commonwealth of Learning. Obinrin ti setan lati ba Aare Buhari sise ni saa yii. 3) Sadiya Farouq: Arabinrin Sadiya ti figba kan jẹ kọmiṣonna ijọba apapọ fun ajọ to n mojuto ọrọ awọn aṣatipo. Lọdun 2011 si 2013 lo fi ṣe akapo ẹgbẹ oṣelu Congress for Progressive Change (CPC) ti aarẹ Buhari dije ninu rẹ fun ọpọlọpọ ọdun ko to darapọ mọ APC. Bakan naa lo tun ba aarẹ Buhari ṣiṣẹ ninu ẹgbẹ CPC gẹgẹ bi akapo gbogboogbo lọdun 2013 si 2014. O je akapo egbe oselu CPC ti o koko gbe Aare Buhari jade 4) Gbemisola Saraki: Gbemisola Saraki jẹ ọkan pataki lara awọn ti oju gbogbo n wo ninu awọn ti Aarẹ Buhari forukọ wọn ranṣe sile igbimọ aṣofin. Gbemi jẹ ọmọ bibi inu agba ọjẹ oloṣelu Oluṣọla Saraki to n dari iṣelu ipinlẹ Kwara fun ọpọlọpọ ọdun ko to di oloogbe. Oun naa ni aburo aarẹ ile igbimọ aṣofin agba to kogba wọle laipẹ yii, iyẹn Bukọla Saraki. Lọdun 1999 ni wọn yan an sile igbimọ lati ṣoju ẹkun Asa / Ilorin nipinlẹ Kwara. Opo gba pe Gbemi ṣiṣẹ lodi si iyansipo ẹgbọn rẹ titi o fi togẹ ni Kwara Gbemi jẹ ọmọ ọdun mẹrinlelaadọta to kẹkọ gboye nipa imọ eto ọrọ aje ni fasiti Sussex nilu Ọba. O jẹ senetọ ẹkun aarin gbungbun Kwara titi di ọdun 2011 nigba to dije dupo gomina ipinlẹ Kwara lẹyin ti Bukola Saraki ẹgbọn rẹ fipo naa silẹ. O pada lọ darapo mọ ẹgbẹ oṣelu APC lọdun 2015 ni eyi ti awọn neiyan gba pe o ṣiṣẹ lodi si ẹgbọn rẹ ninu idibo to kọja lọ to fi to gẹ ni Kwara. Okunrounmu: Ijọba Buhari jẹ ijiya Ọlọrun fun Naijiria 5) Zainab Ahmed: Odu ni ninu iṣẹ minista kii ṣe aimọ fun oloko. Zainab ni o jẹ minista abẹle fun eto iṣuna ati ilana aatẹle fun ijọba apapọ lọdun 2015. Oun lo pada di minista fun inawo ni Naijiria lọdun 2018 nigba ti o gba iṣẹ lọwọ Kẹmi Adeọṣun. Fasiti Ahmadu Bello ni Zaria lo ti kọ ẹkọ nipa iṣiro owo ko to gba oye keji ni Fasiti Olabisi Onabanjọ ni ipinlẹ Ogun. Zainab ni o jẹ minista abẹle fun eto iṣuna ati ilana aatẹle fun ijọba apapọ lọdun 2015. Zainab ti jẹ akọwe agba fun Nigeria Extractive Industries Transparency Initiative tẹlẹ. Omo bibi Yahaya Hamza to jẹ baba to tọ Nasir El Rufai dagba to jẹ gomina ipinlẹ Kaduna. Lateef Adedimeji: Owó wa kò bá máa jóná ṣùgbọ́n aàyè ọpẹ́ ń yọ fún wa 6) Sharon Ikeazor: Sharon Ikeazor jẹ akọwe agba fun ajọ to n ri si owo ifẹyinti awọn oṣiṣẹ, iyẹn, Pension Transitional Arrangement Directorate (PTAD). Oun ni olori awọn obinrin ninu ẹgbẹ oṣelu CPC ti aarẹ Buhari ti kọkọ dije ko too darapọ mo ẹgbẹ oṣelu APC. Bakan naa lo ṣiṣẹ bii olori awọn obinrin fidiẹ fun ẹgbe APC lẹyin ti wọn darapọ lọdun 2014. Wọn pada yan an sinu awọn ọmọ igbimọ alamojuto ẹgbẹ APC ti aarẹ Buhari ba wọle lati 2015. Wọn pada yan an sinu awọn ọmọ igbimọ alamojuto ẹgbẹ APC ti aarẹ Buhari ba wọle lati 2015. 7) Ramatu Tijjani: Ramatu Tijjani jẹ ọmọ ọdun mọkandinlaadọta. Oun ni olori awọn obinrin ninu ẹgbẹ oṣelu APC ti aarẹ Buahri lo fi n tukọ Naijiria bayii. O kẹkọọ nipa aato ile kikọ ni agbegbe ni Fasiti Ahmadu Bello ni Zaria. Oun ni igbakeji alaga obinrin akọkọ fun aarin gbungubn ariwa Naijiria. Oun ni olori awọn obinrin ninu ẹgbẹ oṣelu ANPP ti Buhari ba dije tẹlẹ. Lọdun 2014 lo di olori awọn obinrin ni ẹgbẹ oṣelu APC. Obinrin ti to gabngba sun lọyẹ ninu iṣelu Naijiria Lẹyin ti ile igbimọ aṣofin ba ti pari ayẹwo ti wọn bẹrẹ loni ni a maa mọ awọn to ba wọle gẹgẹ bii minista ati ipo ti wọn maa di mu. Badagry: Erékùṣù tí àwọn ọmọde ti n wọ odo ńlá láti lọ sílé ìwé",0,yoruba ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó ga jù.,0,yoruba Ekaáro eyin eyan mi gbogbo #TweetinYoruba,0,yoruba lóòótọ́ bí a bá wo ìtàn yewájọbí tí a bá nínú ifá ó ní ṣe pẹ̀lú ìkúnlẹ̀ abiyamọ ó sì ní ṣe pẹ̀lú ọrọ̀ ọmọ,0,yoruba Ṣàyẹ̀wò Àwọn Àtòjọ-ẹ̀yàn,0,yoruba #TweetYoruba 2014 - Saturday 1st March 2014 Yoruba to so wipe ile la n wo kia to s'omo l'oruko o kuku puro http://t.co/VV3pEE5sUx,0,yoruba "tí Bàbá fè mú, Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa àwọn ènìyàn: ti o nuni ti o jare.",0,yoruba Báwo ni Nàìjíríà ṣe gboyè orílẹ̀èdè tí ìtànkálẹ̀ òtútù ìgbá àyà tí pọ̀ jù lọ?,0,yoruba Super Flamingoes Nàìjíríà yóò kojú Amẹ́ríkà ní ìpele ‘Quarter finals’ ìdíje ‘FIFA U-17 World Cup’,0,yoruba nise ni a o tun maa jeri won wipe awon ni won daa ju lagbaye mtcheeew,0,yoruba nìkan. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ẹkọ́: ti o nuni ti o nuni ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó wáyé..,0,yoruba "Òwò làwọn ará ibí ń fi wá ṣe bí a ṣe ń gbójú sókè sí wọn fún ohun gbogbo. Wọn kò kọ̀ kí ẹ̀mí bọ́, àpò ara wọn ni wọ́n ń dù! #Iseselagba",0,yoruba "@user Ẹ kú iṣẹ́! Àmọ́ ó kù o, láì gbáṣà ga, ẹ ò tíì ṣe lààmìlaaka nípa ti ètò ìgbafẹ́. Kí ẹ tẹpẹlẹ mọ́ ìṣẹ̀ṣe. #August20",0,yoruba "Falana sọ fun BBC pe, oun ni ẹri pe Buhari n gbero ati ṣe saa kẹta Falana lo sọ ọrọ naa ninu ifọrọwerọ kan pẹlu BBC. Ṣaaju ni Aarẹ Buhari ti sọ loṣu kẹwa ọdun 2019 pe, oun ko ni ipinu lati du ipo Aarẹ lẹyin to ba pari saa keji to n ṣe lọwọ. Garba Shehu, to jẹ oluranlọwọ pataki lori ọrọ iroyin ati igbohunsafẹfẹ fun Aarẹ Buhari ni, erongba Buhari ni lati pari saa keji to n ṣe lọwọ, ko si fẹyinti. Ṣugbọn Falana sọ fun BBC pe, oun ni ẹri pe Buhari n gbero ati ṣe saa kẹta. Lẹnu ọdun diẹ si asiko yii ni awọn Aarẹ ilẹ Africa kan ti n gbiyanju lati ṣejọba fun saa kẹta. Loṣu kẹwa ọdun 2019 ni awọn ọmọ orilẹ-ede Guinea gunle ifẹhonuhan lodi si aba Aarẹ Alpha Conde lati dije sipo Aarẹ orilẹ-ede ọhun fun igba kẹta. Ìbànújẹ́ ló pọ̀ nínú òṣèlú Nàìjíríà tórí a ti lo Pásítọ̀, Wòlìí, Ọ̀jọ̀gbọ́n",0,yoruba "♫ Ijó ọpẹ́ẹ rẹ̀ dàà? Ijó ọpẹ́ẹ mi rè é."""""""" ♫",0,yoruba "Adeboye, Iginla sọ nípa Pastor David Yonggi Cho tó d'olóògbé",0,yoruba "Oluwakemi Famugbode amọ ti inagijẹ rẹ lori itage n jẹ Irawo kẹnu bọ ọrọ ilẹ kun lori nnkan ti obinrin to ba pe ara rẹ ni onilu tabi onijo n ri paapaa eyi to ba wa nile ọkọ ninu wọn. Irawo ni nnkan ti oju oun ri fẹẹ mu ẹmi oun lọ nidi iṣẹ Onilu, DJ, ati Onimọran nipa iṣẹ ti orin n ṣe lara (Music Therapist). ""Ile ẹkọ girama ni mo ti bẹrẹ ilu lilu lẹyin ti mama mi ti kọ bi wọn ṣe n lu gangan lati kekere. Awọn to ju mi lọ ni ile ẹkọ n lu, wọn o lu u daadaa ni mo wa lọ gba a lọwọ wọn"". ""Mo pada roo pe bi mo ba fẹ da yatọ, afi ki n pada sidi ilu gangan"". Irawo ni inu oun ko dun si iṣẹ imọ iṣiro ti oun kọkọ n kọ ni Fasiti afi igba ti oun pada si ibi imọ Tiata. Irawo ni nnkan ti oju obinrin n ri nidi iṣẹ yii kii ṣe kekere paapaa ẹni to ba fẹ ọkọ to ba n jowu tabi ti ko nifẹ rẹ pẹlu iṣẹ to n ṣe. ""Haa, wahala ni o, ẹni ti mo fẹ, mo ro pe o n ti mi lẹyin ni tori o maa n tẹle mi lọ fun ""rehearsal ki n to di iyawo ile rẹ, aṣe irọ ni o n pa."" Irawo ni bi oun ṣe de ile tan bayii ni ọkọ oun yiwọ to ni rara, oun o gbọdọ lọ fun yala rehearsal ni tabi ode ere gan ti wọn ti pe e fun ti wọn yoo si sanwo iṣẹ fun un. ""Gbogbo awọn to n ba mi ṣiṣẹ lo ni wọn n fẹ mi, o bẹrẹ si ni ti mi mọle. Bi mo ṣe bẹrẹ si ni kuna lati le lọ fun ode ilu lilu niyẹn ti olgbaninimọran mi yoo maa bẹ wọ."". Igba to ya ni ara ni oun sọ pe o to gẹ bi ọkọ oun ko ba ti le gba oun tọwọ tẹsẹ pẹlu iṣẹ ti oun n ṣe torinaa o gba awọn obinrin nimọran",0,yoruba eni lo ni àṣà ìdílé ni nfàn ojú kakaaki.,0,yoruba "Ní igba mi owó àkokò, Olùwo ri A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà. ti Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba Láti mú kí àwọn ọmọ ìbílẹ̀ àti ọmọ àgbáyé ó fi ọkàn sí ìdájọ́ àti fún ìdásílẹ̀ẹ Alaa ní ọjọ́ 17 oṣù Ẹrẹ́nà .,0,yoruba nípa àìkú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "Ìjọba fi òté lẹ títa oògùn ikọ́ olómi Codeine Awọn ile iṣẹ apoogun naa ni Emzor, Peace Standard ati Bioraj. @pharm_dezzz sọ pe, awọn ile iṣẹ ti wọn n ṣe oogun Codine kọ ni iṣoro, bi koṣe awọn alagbata ti wọn n ko kaakiri End of Twitter post, 1 @purrples woye pe, igbesẹ NAFDAC le se okunfa ọwọn gogo oogun nilẹ Naijiria. Ero ti @ChinnyPillz ni pe, kii se oogun ikọ olomi Codine nikan ni ile iṣẹ Emzor ati awọn ile iṣẹ oogun meji yoku nse. Kilode ti wọn fi di titipa, sebi oogun ikọ nikan lo yẹ kijọba wọgile? ""Ori bibẹ kọni oogun ori fifọ."" Ohun ti @GbemiDennis sọ si ọrọ naa niyi. O beere pe kin ni yoo sẹlẹ si awọn oogun mii ti wọn n se ati awọn to n siṣẹ nibẹ? @zhurg_ sọpe igbesẹ ajọ NAFDAC ku diẹ kaato nitori yoo só ọpọlọpọ di alainiṣẹ.",0,yoruba "Ọba fè joko, Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..",0,yoruba màlúù tí kò ní ìrù ọlọ́run ni í lé eṣinṣin fún un god himself is the one who fends off flies for a cow that has,0,yoruba "Kọmisọnna fún ètò ìsúná nípínlẹ̀ Ondo ní pé òkun tó jìn jùlọ ní ilẹ̀ Afirika àti bitumen wà nì ìpínlẹ̀ Ondo. Kọmisọnna fun eto isuna ni ipinlẹ Ondo, Emmanuel Igbasan fi idi ọrọ yii mulẹ, lẹyin ti igbakeji aarẹ orilẹede Naijiria, Yemi Osinbajo sọ pe ipinlẹ Ondo ni ọpọlọpọ ohun alumọni kaakiri ipinlẹ naa. Kọnisọnna Igbasan fikun ọrọ rẹ wi pe ipinlẹ Ondo ni ibudokọ okun to jin julọ ni ilẹ Afirika(largest sea port) to le gba awọn ọkọ nla nla , eyi ti o le pese ibudokọ fun awọn oko oju omi ti wọn ba n kẹru bọ lati oke okun wa si Naijiria. Ọba Olutayọ: ìgbésẹ̀ Ọọni àti Alaafin ti ń mú ìṣọ̀kàn dé sáàrin àwọn Ọba Yorùbá Ohun alumọni to wa ni ipinlẹ Ondo Ki lo sẹlẹ si awọn ohun alumọni ipinlẹ Ondo? Kọmisọnna fun eto isuna ni ipinlẹ Ondo ninu ọrọ rẹ sọ wi pe aibikita lo mu ki awọn ohun alumọni to wa ni ipinlẹ Ondo ni ifasẹyin. Ninu ọrọ rẹ, Emmanuel Igbasan fikun wi pe epo bẹntiroolu ti ijọba gbe ọkan le lo mu ki wọn fi ọwọ yẹpẹrẹ mu awọn ohun alumọni ti Ọlọrun ti fi fun ipinle naa. O fikun wi pe nitori epo bẹntiroolu ti lọ silẹ lagbaye bayii, ijọba ti pada si ohun alumọni ati agbẹ to lere gẹgẹbi ọna lati mu ki ibugboro ba ọrọ aje Naijiria. Kọmisọnna naa fikun wi pe laipe si isinyii ipinlẹ Ondo yoo ma a pese ""sweet"" ati ohun ipanu awọn ọmọ ile iwe bii ""sunshine chocolate"" lati ara cocoa. Aṣòfin 18 sá àsálà kúrò nípínlẹ̀ Ondo Awọn aṣofin mejidinlogun ti wọn yọ olori ile aṣofin ipinlẹ Ondo ati igbakeji rẹ, ti sa fi ipinlẹ naa silẹ. Ohun ti awọn aṣofin naa ni o faa ti wọn fi sa kuro ni ilu Akurẹ ko ṣẹyin bi wọn ṣe ni abo to peye ko si fun ẹmi awọn lati igba ti wọn ti yọ olori ile naa tẹtẹ nipo. Olori tuntun ti wọn ṣẹṣẹ yan fun ile naa, Ọlamide George ni ilu Ibadan ni awọn sare wa fi ara pamọ si nitori abo ẹmi wọn Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Lẹyin ti awọn aṣofin naa yọ Bamidele Ọlẹyẹloogun ati igbakeji rẹ Ogundeji Iroju nipo ni awọn janduku ti iroyin sọ pe wọn jẹ ọmọ ẹgbẹ awakọ ero NURTW nilu Akurẹ ya bo ile aṣofin naa ti wọn si lu awọn aṣofin ati oṣiṣẹ ti ọwọ wọn ba. Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ, olori tuntun ti wọn ṣẹṣẹ yan fun ile naa, Ọlamide George ni ilu Ibadan ni awọn sare wa fi ara sinko si nitori abo ẹmi wọn. Kọmisọnna fún ètò ìsúná nípínlẹ̀ Ondo ní pé òkun tó jìn jùlọ ní ilẹ̀ Afirika àti bitumen wà nì ìpínlẹ̀ Ondo. ""A ni lati sa kuro nilu nitori ko si abo fun ẹmi wa mọ. Ẹmi mi, ẹbi mi ati awọn aṣofin ẹgbẹ mi lo wa ninu ewu, idi si niyii ti a fi fi ilu silẹ wa fi ara pamọ si ilu Ibadan."" ""A si ti fi asiko yii kigbe iranwọ si aarẹ Buhari ati ọga ọlọpa lorilẹede yii lati wa gba wa silẹ.""Ni ọjọ ẹti ti o kọja ni awọn aṣofin mejidinlogun ninu mẹrindinlọgbọn to wa ni ile naa dibo yọ olori ile naa ati igbakeji rẹ lori ẹsun iwa aitọ, ṣiṣe owo baṣubaṣu, ṣiṣi agbara lo ati aikun oju iwọn lẹnu iṣẹ. 'Gómìnà Akeredolu lọ́wọ́ nínú wàhálà ilé aṣòfin Ondo' Olamide George lori olori tuntun ile asofin Ondo Aṣofin Olamide George ti wọn yan sipo lẹyin ti awọn aṣofin kan panupọ yọ olori ile aṣofin ipinlẹ Ondo nipo ti fi ẹsun kan gomina ipinlẹ naa, Rotimi Akeredolu pe o lọwọ ninu wahala ti o n waye laarin aṣofin ipinlẹ naa. Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC News Yoruba, aṣofin George ni idi ti awọn aṣofin mejidinlogun fi gbe igbesẹ ati yi adari ile naa pada ko ju wi pe awọn aṣofin ipinlẹ naa ko lanfani lati ṣe ojuṣe wọn gẹgẹ bii iṣẹ ti awọn araalu fi ran wọn. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ''Oúnjẹ òkèlè àti òróró le fa ẹ̀jẹ̀ rúru àti àrùn rọpárọsẹ̀'' O ni gomina Akeredolu lo ko awọn agbofinro fun olori ile ti wọn yọ, Bamidele Ọlẹyẹlogun lati pada lọ ṣi ijoko ile lẹyin ti wọn ti yọọ. ""Gomina lọwọ sii ni. Nitori a gbọ pe lẹyin ti a yọ awọn adari ile tẹlẹ kuro, a gbọ pe awọn mẹfa ko ara wọn jọ lati pada lọ joko yi ohun ti awa mejidinlogun fi ẹnu ko le lori. Ti gomina si ko agbofinro tẹle wọn. Eyi ko yẹ ko ri bẹẹ rara. Nigba to n sọrọ siwaju, o ni irọ ni pe awọn ti ko ni anfani ati pada ni wọn n da wahala silẹ. "" Emi ti mo n sọrọ yii, mi o ra fọọmu pe mo fẹ dibo, nitorinaa ko si ẹni to lee sọ pe aini anfani ati pada si ile aṣofin lẹẹkan sii lo n faa."" Bakan naa lo fi kun un pe bi ọrọ ṣe ri yii, ẹsẹ ofin ni awọn yoo tọ lori ọrọ naa. 'Awọn aṣofin naa fẹ yọ emi ati gomina ipinlẹ Ondo nipo ni' Ondo Assembly: Gómìnà Akeredolu ń ti àwọn tó ń da ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Ondo rú- Amọṣa, olori ile naa ti wọn yọ nipo, Bamidele Ọlọyẹloogun ni mimi kan ko mi ohun kuro lori aga olori ile naa. Ninu ọrọ ti oun pẹlu ba BBC News Yoruba sọ, awọn aṣofin ti ọrọ kan fẹ yọ oun ati gomina ipinlẹ naa nipo ni. Wọn ya mi laṣọ, wọn na gbogbo awọn amugbalẹgbẹ mi. Mo si bi wọn pe ko si ijoko loni, emi nikan gẹgẹ bii olori ile nikan lo lee pe ipade ijoko ile."" Aṣofin Ọlẹyẹloogun ni ko si ohun to jọ janduku ni ile aṣofin naa ati pe awọn agbofinro wa nikalẹ. O ni o ṣeeṣe ko jẹ ẹhonu lori awọn ẹtọ to yẹ ati bi awọn kan ko ṣe ni anfani ati dije fun ijoko ile naa ni ibo ọdun 2019 wa lara ohun ti o n fa ikunsinu wọn. O fi kun un pe igbesẹ alaafia yoo bẹrẹ ni ọsẹ ti o nbọ lati pa ina aawọ laarin wọn. Ondo: Yánpọnyánrin ní ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Ondo nítorí olórí tuntun Ẹsun ti wọn fi kan awọn mejeeji ti wọn yọ nipo naa ni iwa ibajẹ lẹnu iṣẹ Ọrọ di iṣu ata yan-an-yan-an ni ile aṣofin ipinlẹ ondo lọjọ ẹti pẹlu bi awọn aṣofin meji ṣe n pe ara wọn ni olori ile naa. Gẹgẹ bi BBC News Yoruba ṣe gbọ, ọrọ naa bẹrẹ ni owurọ ọjọ ẹti nigba ti awọn aṣofin mejidinlogun ninu mẹrindinlọgbọn to wa ni ile naa dibo yọ ni ile olori ile aṣofin ipinlẹ Ondo, Bamidele Oloyelogun ati igbakeji rẹ, Iroju Ogundeji kuro nipo. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Oloyelogun ti wọn yọ nipo wa lori ijoko ni gbogbo asiko ti ariwo ati ys loye fi n waye. Iroyin ọhun tun fi kun un pe idarudapọ waye ninu gbọngan ile aṣofin ọhun lẹyin ti igbesẹ ati yọ olori ile naa ati igbakeji rẹ ti waye tan pẹlu bi awọn janduku kan, ti awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn sọ pe wọn jẹ ọmọ ẹgbẹ ọlọkọ ero, NURTW ti ṣe ya wọ ile aṣofin naa ti wọn si le gbogbo awọn aṣofin atawọn oniroyin to fi mọ awọn oṣiṣẹ nile aṣofin naa da sigbo. Koda iroyin naa fidi rẹ mulẹ pe awọn janduku naa tun ya aṣọ mọ olori ile naa tẹlẹ, Jumọkẹ Akindele lọrun lasiko ti gbogbo rukerudo yii fi waye. Ògidì ọmọ Yorùbá gbọ́dọ̀ mọ 'áayan ògbufọ̀' dáadàa Lẹyin eyi ni olori ile naa ti wọn ys nipo, Bamidele Oloyelogun atawọn to jẹ tirẹ ni ile aṣofin naa lọ ko ara jọ pọ ni ile rẹ nibi to ti ba awọn oniroyin sọrọ pe oun ṣi ni olori ile naa ati pe ohun ti ko lẹsẹ nlẹ ni igbesẹ naa. Ni kete ti o pari ipade pẹlu awọn oniroyin yii ni o pada laarin ọpọ ọkọ, awọn janduku ọmọ ẹgbẹ ọlọkọ ero NURTW ati awọn oṣiṣẹ alaabo lọ si ile aṣofin naa nibi ti oun ati awọn aṣofin mẹwa ti wọn fẹ tirẹ ni ile naa tun ti gbe ijoko mira kalẹ ti wọn si yọ paṣẹ lọ rọkun nile fun awọn aṣofin marundinlogun ti wọn ni wọn fi gbogbo ara kopa ninu igbesẹ lati yọọ nipo. Kini ohun ti o n rugbo lagbo oṣelu nipinlẹ Ondo? ""Kii ṣe aṣiri to bo rara laarin agbami oṣelu nipinlẹ Ondo ati laarin awọn onwoye oṣelu nibẹ pe ọdọ gomina Rotimi Akeredolu ni olori ile aṣofin ipinlẹ Ondo, Bamidele Oloyelogun ti wọn yọ kuro nipo fi ara ti si"" Eyi ni ọrọ ọpọ awọn onwoye to ba BBC News Yoruba sọrọ sọ. Ìnú mi kìí dùn nígbà trí mo ń ṣiṣẹ́ ni bánkì tó ìgbà ti mo bẹ̀rẹ̀ mẹkáníìkì Ni oṣu diẹ sẹyin ni wọn ti kọkọ yọ Bamidele Oloyelogun kuro ni ipo gẹgẹ bii olori ile naa ṣugbọn ti wọn ni gomina ipinlẹ naa, Rotimi Akeredolu paṣẹ ki wọn daa pada sipo. Amọṣa ohun ti wọn ni o ṣeeṣe ko fa ti ọtẹ yii ko fẹẹ ṣẹyin bi pupọ awọn aṣofin ile naa ko ṣe ni anfani ati oreọfẹ pipada dije fun ijoko ile ni ọdun 2019 naa lasiko idibo abẹle ti ẹgbẹ oṣelu APC ṣe kọja. Ni bayii, olori ile aṣofin ipinlẹ Ondo, Bamidele Oloyelogun ati igbakeji rẹ, ti wọn yọ kuro nipo atawọn aṣofin mẹwa to jẹ tirẹ ti so ijoko ile aṣofin naa rọ di ọjọ miran ọjọ ire. Nigba ti awọn akọroyin bere idi ti o fi ti ile pa, aṣofin Oloyelogun ni ""ofin ilana ile fun oun laṣẹ lati ṣe bẹẹ."" Ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Ondo yan olórí tuntun Nigba ti awọn akọroyin bere idi ti o fi ti ile pa, aṣofin Oloyelogun ni ""ofin ilana ile fun oun laṣẹ lati ṣe bẹẹ."" Iroyin to tẹ BBC news Yoruba lọwọ ṣalaye pe nibi ijoko ile naa to waye ni ọjọ ẹti lawọn aṣofin mejidinlogun to wa nile aṣofin naa. Nibayii, wọn ti yan Ọlamide George lati ẹkun ididbo ipinlẹ ti Akurẹ North gẹgẹ bii olori ile aṣofin naa nigba ti Abimbọla Fajolu lati ẹkun idibo Oluji/Okeigbo si bs si ipo igba keji. Ẹsun ti wọn fi kan awọn mejeeji ti wọn yọ nipo naa ni iwa ibajẹ lẹnu iṣẹ. Alaga igbimọ ile lori eto iroyin, aṣofin Fatai olotu ṣalaye fun awọn oniroyin lẹyin ijoko ile pe ẹsun ṣise owo baṣubaṣu, aikun oju iwsn lẹnu iṣẹ ati ẹsun miran ni wọn tun fi kan Bamidele Oloyelogun ati igbakeji rẹ, Iroju Ogundeji ki wọn to yọọ Tenancy: Njẹ́ o mọ ẹ̀tọ́ rẹ̀ gẹ́gẹ́ bi ayálégbé? Wọn ti yọ olori ile aṣofin ipinlẹ Ondo, Bamidele Oloyelogun ati igbakeji rẹ, Iroju Ogundeji kuro nipo. Iroyin to tẹ BBC news Yoruba lọwọ ṣalaye pe nibi ijoko ile naa to waye ni ọjọ ẹti lawọn aṣofin mejidinlogun to wa nile aṣofin naa. Iroyin ọhun tun fi kun un pe idarudapọ waye ninu gbọngan ile aṣofin ọhun lasiko ti igbesẹ ati yọ olori ile naa ati igbakeji rẹ fẹ waye. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ni bayii, wọn ti yan Ọlamide George lati ẹkun idibo ti ariwa Akurẹ North gẹgẹ bii olori ile aṣofin naa nigba ti Abimbọla Fajolu lati ẹkun idibo Oluji / Okeigbo si ipo igba keji. Ẹsun ti wọn fi kan awọn mejeeji ti wọn yọ nipo naa ni iwa ibajẹ lẹnu iṣẹ. Alaga igbimọ ile lori eto iroyin, aṣofin Fatai olotu ṣalaye fun awọn oniroyin lẹyin ijoko ile pe ẹsun ṣise owo baṣubaṣu, aikun oju iwsn lẹnu iṣẹ ati ẹsun miran ni wọn tun fi kan Bamidele Oloyelogun ati igbakeji rẹ, Iroju Ogundeji ki wọn to yọọ. 'Ó ṣojú mi kòró, ẹ wọ bí ìgbà ayé Bàbá Fagunwa ṣe rí'",0,yoruba rere. Ọba lo ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.,0,yoruba "Sanwo-Olu gbe igbimọ ẹlẹni mẹjọ kalẹ ti yoo ṣe amujuto atunṣe ohun gbogbo tawọn janduku bajẹ. O tun sọ fun igbimọ naa lati ṣiṣẹ lori ọjọ iwaju ipinlẹ Eko ki wọn si tun ṣiṣẹ lori ọna lati wẹ oju egbo ti iwọde EndSARS da san. Awọn ọmọ igbimọ naa wa lati ileeṣẹ ijọba, alaadani atawọn ajọ agbaye ti wọn ti yọnda ara wọn fun iṣẹ atunṣe ipinlẹ Eko lẹyin iṣẹlẹ EndSARS. Ọgbẹni Yemi Cardoso ni alaga igbimọ ọhun nigba ti Ọjọgbọn Kanyisola Ajayi, Ọgbẹni Gbenga Agboola, Arabinrin Bola Adesola, Ọgbẹni Sam Egube, Ọgbẹni Jimi Hotonu, Ọgbẹni Abubakar Suleiman ati ọmọ ẹgbẹ ajọ agbgaye alaanu kan jẹ ọmọ ẹgbẹ igbimọ ọhun. Sanwo-Olu tun ṣe ifilọlẹ igbimọ mẹfa miiran ti yoo ri si bi ipinlẹ Eko yoo ṣe pada bọ sipo ni kiakia. Gomina Sanwo-Olu ni asiko ti to lati gbagbe ohun to ṣẹlẹ ki gbogbo ara ipinlẹ Eko fọwọ sọwọpọ lati tun Eko ṣe pada. Orlando Owoh: Èmí àti Oladipupo Owomoyela jọ lọ ẹ̀wọ̀n Alágbọn- Caroline Owoh, aya Orlando Gomina ipinlẹ Eko ni ọgọọrọ eeyan lo yọnda lati ṣiṣẹ pọ pẹlu ijọba lati ṣatunṣe ipinlẹ naa lẹyin rogbodiyan to ṣẹlẹ. O ni ijọba yoo gbe abadofin lori ati tun ipinlẹ Eko ṣe lọ si iwaju ile igbimọ aṣofin lai pẹ.",0,yoruba "Kò tíì ṣí ọjọ́ kan ní pàtó nígbà tí ilé - ìwé yóò wọlé - Emeka Nwajiuba Mínísítà ìpínlẹ̀ fún ètò ẹ̀kọ́ lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà , Emeka Nwajiuba ti ní ohun kò leè sọ ọjọ́ tàbí ìgbà tí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ yóò padà lọ sí ilé - iwé wọn .",0,yoruba Pánẹ́ẹ̀lì Igun Òkè,0,yoruba "ibile. Nitori eyi, ara eni lo ni iwa rere lojiji.",0,yoruba Ṣẹ̀dà àdírẹ̀sì àwòrán “%s”,0,yoruba Bẹ̀_rẹ̀ Ìṣàfarawé Kọ̀ǹpútà,0,yoruba Ọ̀kan lára òṣìṣẹ́ Aláàfin Ọ̀yọ́ kan tí a ò bárúkọ rẹ̀ nínú àlàyé tí a gbà ni Òkòló í ṣe. Iṣẹ́ẹ rẹ̀ ni láti pa koríko fẹ́ṣin ọba. #ItanDowe,0,yoruba "Angel Gomes: Angel Gomes, agbábọ́ọ̀lù Manchester United ṣàlàyé ohun gan tó gbé e dé ṣọ́ọ̀ṣì T. B Joshua",0,yoruba owo ṣẹlẹ ni Ibadan ti gbogbo eniyan sọ o dara. (2021),0,yoruba "Ẹgbẹ agbabọọlu Super Eagles ti Naijiria ti pari ifẹsẹwọnsẹ wọn ninu idije ilẹ Afirka, lẹyin ti wọn pari pẹlu ipo kẹta ninu idije Afcon 2019. Tunisia ni Super Eagles naijiria fi se ifajẹ ti wọn se ipo keta. Bi awọn kan se n sọ wi pe Ighalo lo fakọyọ julọ ninu ẹgbẹ agbabọọlu Super Eagles ni idije Afcon naa. Amọ, awọn miran ni Chukwueze ati Ighalo tiraka ṣugbon Etebo ni fun awọn, ti awọn miiran si ni ẹni miran lo se moriya fun wọn. Bakan naa ni awọn kan ni gbogbo igba ni ikọ Super Eagles ma n se ipo kẹta, eleyii ti wọn tilẹ pe ni ""ogun ibi wa lorilẹede Naijiria"".",0,yoruba ẹ̀yin ogun ọ̀run ò ẹ ṣéun o,0,yoruba "àkerekere, Ìyá ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa iṣẹ́: ti o wulo.",0,yoruba "Bí o bá fẹ́ mú yàn lẹ́rú, gba gbogbo nǹkan tó fi ń ṣe agbára. #Yoruba",0,yoruba "Ẹmọ́ jíire lópòó ilé, àfèèbòjò jíire nísà. Ẹ̀yin ọmọ Oòduà ẹ ò jíire bí? #Ekaaaro",0,yoruba """Mi ò kí ń ṣe olóṣèlú rárá àti rárá, ẹ ò sì lè ríi kí n gbè lẹ́yìn èèyàn kan torí ọmọ mí pọ̀"". Alufaa agba ijọ Redeemed Christian Church of God, RCCG, pasitọ Enoch Adeboye ti sọ pe oun ko mọ boya eto idibo yoo waye lọdun 2023. Adeboye ni Ọlọrun ko tii sọ fun oun boya eto idibo naa yoo waye tabi bẹẹ kọ. Oludari agba ijọ naa lo sọ ọrọ ọhun lasiko eto isin idupẹ to waye ni olu ijọ naa to wa ni Ebute Meta, ipinlẹ Eko laarọ ọjọ Aiku. O ni Ọlọrun ba oun sọrọ nipa eto idibo ọdun 2019 laarin ọdun kan ṣaaju eto idibo naa, amọ bẹẹ kọ lo ri fun eto idibo ti ọdun 2023 yii. Ẹwẹ, o sọ siwaju si pe o ṣeeṣe ki Ọlọrun ṣi ba oun sọrọ nipa eto idibo naa ṣugbọn lọwọ yii ko ti kan si oun nipa rẹ. Ninu ọrọ rẹ, o ni iṣekupani lemọ-lemọ to n waye ni ipinlẹ Kaduna n kọ oun lominu, to fi mọ bi awọn eeyan kan ṣe n ji epo Naijiria ta, bi Naijiria ṣe jẹ obitibiti gbese ati eto ọrọ aje to dẹnukọlẹ. Baba Adeboye sọ ni gbangba pe oun ko ṣatilẹyin fun oludije kankan. Gẹgẹ bii oun to ṣo, o ṣe pataki lati ṣalaye ni kikun lẹyin ti awọn eeyan kan bẹrẹ si n bu ẹnu atẹ lu ijọ RCCG nitori bi wọn ṣe da ẹka to n bojuto ọrọ oṣelu silẹ ninu ijọ naa. O ni ""Ẹ gbọ mi daadaa... Mo n ba yin sọrọ gẹgẹ bii ọmọ mi, ṣe ẹ fẹ gbọ ootọ?"" ""Lọwọ ti mo duro siwaju yin yii, mi o le sọ boya eto idibo yoo waye lọdun 2023 tabi bẹẹ kọ."" ""Ẹ ma ṣo pe pasitọ Adeboye sọ pe ko ni si eto idibo lọdun to n bọ o; kii ṣe ohun ti mo sọ niyẹn."" ""Idi ti mi o ṣe tii mọ ni pe Baba mi ko tii ba mi sọrọ nipa rẹ."" ""Nigba ti a dipo kẹyin, o ba mi sọrọ ni nnkan bi oṣu Kẹfa ọdun to ṣaaju eto idibo naa... ko tii pẹ ju ṣa, amọ ko tii ba mi sọ ohunkohun lọwọ yii."" Ẹni ọgọrin ọdun naa pari ọrọ rẹ pe ki awọn eeyan lọ gba kaadi idibo wọn, ki wọn si dibo fun ẹni ti ọkan ba n fẹ lọjọ idibo.",0,yoruba yì í tún ṣe àwọn iṣẹ́ tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ẹkọ́: ti o nuni ti o nuni ti o ní wúlò.,0,yoruba "Nítorí ọlá ò ń lo ipò lódì-lódì, kóra ẹ ní ìjánu, mọ̀ pé ipò á fi onípò sílẹ̀ lọ́jọ́ kan.",0,yoruba "Ipinlẹ Borno Akọroyin kan sọ fun BBC pe eniyan mẹta to gbe ado oloro si ara wọn jẹ ki ado oloro naa ro gbamu lara wọn. Éégún tó wà nídí Yoruba Bollywood, Samo Baba f'ojú hàn o! Eyi waye ni iwaju ita gbọngan kan ni ilu Konduga nibi ti awọn ololufẹ ere bọọlu ti maa n woran lori ẹrọ amohumaworan. Oṣiṣẹ ajọ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri ni ipinlẹ naa, usman Kachalla wi fun ile iṣẹ iroyin AFP pe ""iye ẹmi to nu ti to ọgbọn ti o si le ni ogoji to fara pa. Ladoja",0,yoruba mo ma ti gbagbe wi pe eni ni ojo naa #TweetInYoruba https://t.co/hn4i8DxNPf,0,yoruba "Ọmọ tí yóò rò papa re yóò ri Nitori eyi, ara eni lo ni ọ̀gbọ́n.",0,yoruba "rere. Ọba lo ni Nitori eyi, ara eni lo ni àṣà yorubá eyti o gbe lori ọ̀run dídì.",0,yoruba tìkẹ́ gbé mú yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba "D’ijú, kí o se bi ẹni kú, wàá ri wipe ìsẹ́jú kan lo jẹ awọn ará ibí Ayé ò lopin, ẹni ti o ba kú ni aye rẹ̀ pin #YorubaPoem #Yoruba",0,yoruba "Awọn ile iwe alakọbẹrẹ ati girama ti ọrọ naa kan ni agbara ti ya wọ bayii. Oluranlọwọ pataki lori ọrọ iroyin fun ijọba ipinlẹ Ondo, Ojo Oyewamide sọ fun BBC pe, bi wọn ṣe ti awọn ile iwe naa jẹ ọna lati wa ojutu si iṣelẹ omiyale naa. Oyewamide ni ki ṣe gbogbo ile iwe ni ipinlẹ Ondo ni ọrọ naa kan, bikoṣe awọn ile iwe to wa ni ijọba ibilẹ Ilajẹ ati Ẹsẹ odo. O ṣalaye pe ijọba ti gbe igbimọ kan kalẹ lati boju wo agbegbe ti iṣẹlẹ ọhun ti waye, lọna ati wa ọna abayọ si. Ijọba ipinlẹ Ondo, labẹ iṣakoso gomina Rotimi Akeredolu ti dari awọn oluṣakoso ile iwe lagbegbe naa, lati ri pe wọn ko ohun elo ikawe ti omi le bajẹ kuro lagbegbe ọhun, titi di igba ti ijọba yoo wa ojutu si ọrọ naa. Bangladesh Brothel: Ọ̀pọ̀ àwọn àṣẹ́wó tó wà níbẹ̀ ni wọ́n bí sílé aṣẹ́wó náà",0,yoruba "Awọn ọlọpaa naa padanu ẹmi wọn nitori oniruru ikọlu ti awọn agbebọn naa ṣe ni ipinlẹ Rivers ati Akwa Ibom laarin ọjọ keje si ọjọ kẹsan an, oṣu Karun un, ọdun 2021 ti a wa yii. Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Akwa Ibom, Odiko Macdon, lo fidi ọrọ naa mulẹ ninu atẹjade to fi ṣọwọ si awọn akọroyin lẹyin ikọlu to waye lọjọ Aiku. Odoro Ikpe Police Station, for Ini LGA of Akwa Ibom State. Ikọlu to waye lopin ọsẹ yii ni wọn ṣe si agọ ọlọpaa ti wọn ko lo mọ ni Essien Udim ati Ikot Odon ni ijọba ibilẹ Abk nipinlẹ naa. Ileeṣẹ ọlọpa sọ fun BBC pe awọn agbebọn naa kọlu agọ ọlọpaa to wa ni Odoro Ikpe, nibi ti wọn ti pa ọlọpaa marun un, to fi mọ iyawo ọkan lara awọn ọlọpaa naa to lọ bẹ ọkọ rẹ wo lẹnu iṣẹ. Ni ipinlẹ Rivers, awọn agbebọn pa ọlọpaa meje ni ikọlu mẹta ọtọtọ. Iroyin ni awọn agbebọn ọhun gbe ibọn Ak-47 lọwọ lati ṣe awọn akọlu naa, ninu eyii ti awọn ọlọpaa kan ti farapa ti wọn si tun jo awọn ọkọ ti wọn fi n ṣiṣẹ. Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ naa ni awọn ti bẹrẹ si n tọpinpin awọn agbebọn to lọwọ ninu awọn ikọlu ọhun. Ni Anambra, awọn agbebọn kọlu agọ ọlọpaa to wa ni Ozubulu, iyẹn ni ijọba ibilẹ Ekwusigo nipinlẹ ọuhn. Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ naa, DSP Ikenga Tochukwu sọ pe iṣẹlẹ ọhun waye ni nnkan bii aago meje aṣalẹ lọjọ kẹsan an, oṣu yii. Tochukwu ni iwadii ti bẹrẹ lati fi oju awọn aṣebi to wa nidi awọn ikọlu naa lede. Iye awọn ọlọpaa ti awọn agbebọn naa ti ṣekupa ti kun awọn ti ẹmi wọn ti sọnu ni Naijiria nitori awọn ikọlu lemọlemọ bayii. Nnkan bii ọsẹ diẹ sẹyin ni awọn agbebọn naa bẹrẹ si n kọlu agọ awọn ọlọpaa ni iha ila-oorun Naijiria, ti ko si sẹni to mọ irufẹ eeyan ti awọn agbebọn naa jẹ tabi ohun gan ti wọn fẹ ni pato.",0,yoruba "Ohun tó pa Yemi Adegunju, òṣèré tíátà tó jáde láyé rèé",0,yoruba "Ọ̀ṣun ló pàṣẹ pé obìrin ò gbọdọ̀ wọ aṣọ agbádá mọ́? Ifá ló wí bẹ́ẹ̀, Ọmọ Yobá kọ́ #orisa #Osun #Osogbo #yoruba #agbada",0,yoruba Eṣinṣin tí kò bá gbọ́ ìkìlọ̀ ló ńbá ọ̀gẹ̀dẹ̀ wọ ẹnu ọ̀bọ. / Only a disobedient housefly accompanies (a bite of) banana into the monkey's mouth. [Moderation is it; lack of self-control can be costly.] #Yoruba #proverb,0,yoruba Ibo odun 2015: Awon oloselu koju ija buruku sira won http://t.co/8L9fs0rfuc,0,yoruba irúgbìn = crop òjò rọ̀ irúgbìn ta ► rain falls the crop germinate,0,yoruba "Onírúurú ikú ni yóò pa gbogbo àwọn olùgbée 20 , 000 Yau Ma Tei .",0,yoruba "òun tí a ní nípa ire àti ìbàdandun, àwọn ẹ̀kọ́ ọmọ aláwọ̀ wà níṣẹ̀.",0,yoruba "Awọn kan sọ pe ìgbésẹ̀ ọ̀ún jẹ́ eyi tó tọ́ tó sì yẹ, nigba ti awọn mìíran ríi gẹgẹ bii oun tí kò tọ̀nà rárá. Díẹ̀ lara awọn orilẹede ti wọn sọ sí ọ̀rọ̀ naa nìyí: Orilẹede Amerika Aarẹ Donald Trump sọ pe, ìgbésẹ̀ naa jẹ èyí to mu èròngbà awọn wá sí ìmúsẹ. O ni àseyege gbaa ni ni ìkọlù naa jẹ́, ti ó sì tún dúpẹ́ lọ̀wọ̀ awọn orilẹede to fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹlu rẹ̀. Orilẹede China China ni tirẹ̀ ni awọn kò faramọ́ ikọlu naa nitori pe ó lòdì si òfin ìbásepọ̀ laarin awọn orilẹede lágbàáyé. China pe fun àtúntò ètò òsèlú lagbaye, ati pe, o ni ó tó ki awọn orilẹede agabye ''maa tẹ̀lé ìlànà to'tọ́"". Orlẹede Isreal Benjamin Netanyahu ti orlẹede Isreal ní tirẹ̀ sọ pe, lati ọdún to kọjá ni oun ti sọọ́ pe, oun faramọ́ ki aarẹ Amerika Donald Trump ""gbé ìgbésẹ̀ to tọ́ lori lílo Kẹ́míkà olóró"" láàárín awn orilẹede lagbaaye. Orilẹede Russia Russia ni gbogbo ara lòún fi lòdì si bi orilẹede Amerika se kọlu orilẹede Syria ""níbití orilẹede Russia ti n se ìrànlọ́wọ́ fun ìjọba to ba òfin mu lorilẹede Syria lati koju awọn ajìjàgbara."" Ó ní oun n pè fun ìpàdé pàjáwìrì ninu àjọ ìsọ̀kan àgbáyé. Saudi Arabia Saudi Arabia ni awọn faramọ́ bi Amerika, France ati ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì se kọlu Syria, nitori pe ikọlu ọun |""jẹ́ ìdáhùn si awọn ìwà ọ̀daràn ti ìjọba Bashar al-Assad n hù."" Turkey Orilẹede Turkey ni ""awọn fi ọwọ́ mẹ́wẹ̀ẹ̀wá si ikọlu naa, nitori pe, o mu ẹ̀rì ọkàn fun ìwà ọmọnìyàn kuro, lẹ́yìn ìkọlù to wáyé ni Douma.""",0,yoruba "Owa Ooye ti ilu Okemesi Ekiti Oba Gbadebo Adedeji lo sọ eyi nigba to fi n tẹpẹlẹ mọ lilo awọn nkan amusagbara isẹnbaye Yoruba lati koju ipenija aabo to n koju Naijiria. Owa Ooye ti ilu Okemesi Ekiti ni iru awọn nkan amuyẹ wọn yi le koju ijinigbe ati awọn iwa ọdaran mii to gbogo lawujo. 'Ẹ kálọ sí ìlú mi'... Ètò ńlá tó bẹ̀ sílẹ̀ kìjà lórí BBC Yorùbá Lasiko to n ba awọn akọroyin sọrọ saaju ifilọlẹ eto ajọdun asa Okemesi Cultural Festival tọdun yi ni ọba naa salaye pe kani awọn ọba alade ko fi ọwọ yẹpẹrẹ mu asa wọn ni, awọn ajinigbe ko ba ma ribi maa nawọ gan wọn laafin wọn. O ni bi wọn ba lo awọn nkan amusagbara yi bo ti se yẹ ni, ko le si ajinigbe tabi awọn janduku kankan to le se ikọlu si wọn tabi agbegbe wọn. Oowa Oye naa ni lawọn orileede mii, asa jẹ ohun amuyangan ti awọn eeyan fi n pa owo wọle sugbọn , ọrọ ko ri bẹ ni Naijiria. ''Ikọlu tawọn agbebọn n se si ori ade ti n peleke lẹnu ọjọ mẹta yi.Bawo lawọn janduku yoo ti se maa se ikọlu sawọn Kabiyesi ti wọn yoo maa pa wọn bi ẹni pa adiẹ?'' ''Mo ni igbagbọ pe bi a ba fi ẹsẹ ile tọ ọrọ yi, gbogbo rẹ ni yoo niyanju''. Ohun tí ìyàwó Adeboye ṣe ní ìgbà akọkọ tó fojú hàn lẹ́yìn ikú ọmọ wọn Dare Àwọn ẹni ibi kan ń wá gbogbo ọ̀nà láti tú orílẹ̀èdè Nàíjíríà ká - Ààrẹ́ Buhari 'Tééyàn bá kú a lè yọ yọ ojú yẹn tẹ́ẹ bá gbà wá láyé, a lè dá a sí fún ẹlòmíràn' Kabiyesi tẹsiwaju pe laye atijọ ti awọn eeyan maa n kogun ja ara wọn, o ni bi awọn Yoruba se n jagun. O ni ''awọn eeyan kan ko ni igbagbọ si isẹsẹ wa mọ nitori awọn ẹsin tuntun to yẹpẹrẹ agbara awọn babanla wa'' Koda o ni awọn Kabiyesi kan a maa sọ pe awọn ko le se irọra lati fi daabo bo ara wọn. O ni iwa yi jẹ iwa ti ko bojumu. ''Awa ni olusọ asa wa, a kii se ẹni to n fi asa wa rare nilẹ.Ki lo de ta fi n sa kuro nidi asa wa?'' Lẹnu ọjọ mẹta yi ni ilẹ Yoruba ati lawọn aaye miran ni Naijiria, ijingbe paapa tawọn oriade ko jẹ nkan tuntun mọ. Ni ipinlẹ Ekiti, awọn ajinigbe ti se ikọlu sawọn ọba kan ti wọn si ti ji awọn kan pe to fi mọ awọn mii to padanu ẹmi wọn lọwọ awọn olubi wọn yi. Pupọ araalu lo ti n kesi ijọba lati wa wọrọkọ fi sada lori ọrọ yi nitori inu ibẹrubojo lawọn araalu ati awọn lọbalọba naa n gbe.",0,yoruba ó ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó wáyé.,0,yoruba "Ni aarọ ọjọbọ ni ajọ TI abọ iwadi rẹ sita nilu Abuja, to si kede pe orilẹede Naijiria tun ti ja walẹ pẹlu ipele meji, ninu iwadi to se lori bi Naijiria se n gbogun tiwa ibajẹ si lọdun to kọja. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Naijiria lo gbe ipo kẹrinlelogoje laarin awọn ọgọsan orilẹede ti wọn se iwadi le lori. Ajọ TI ni bi ilana ofin Naijiria se n se ojusaaju nidi awọn eeyan to n lo ida ofin le lori nipa iwa ijẹkujẹ, lo mu ko ja walẹ lori akaba iwa ijẹkujẹ, to si jẹ pe awọn mẹkunnu lo n jiya iwa ajẹbanu, tawọn olowo si n rọna yọ. Nigba to n fesi lori ọrọ naa, agbẹjọro agba ati Minisita feto idajọ, Abubakar Malami ni ko si ẹri to daju ti ajọ TI fi gbe ara rẹ lẹsẹ lori esi to gbe jade naa. ""Ta ba ni ka sọrọ nipa gbigbogun ti iwa ibajẹ, a ti n se ju ti atẹyinwa lọ, ta si tun setan lati se ju bẹẹ lọ yatọ si ohun ti ajọ TI gbe jade. Bẹẹ si ni ko si ohun ti orilẹede yii ko tii se lati sẹ eegun ẹyin iwa ajẹbanu lorilẹede yii"" Láì rọ lápa rọ lẹ́sẹ̀, ẹ wo ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń lọ́ ara lóríṣi ọ̀nà",0,yoruba "RT @user: Àyájọ́ òní ní ọdún 1930 ni bàbá baba Fẹlá, Josiah Jesse Ransome-Kútì yún'sẹ̀ òrìṣà, tí ó gba èkuru jẹ lọ́wọ́ ẹbọra. #Yorub…",0,yoruba "tó kún jú, àwọn ènìyàn ni ó pa Ọmọ lo joko.",0,yoruba "Abẹṣẹkubiojo ọmọ Naijiria to fi orilẹede UK ṣe ibuje, Anthony Joshua ti sọ pe oun ti ṣetan lati ba Tyson Fury ja. Bo tilẹ jẹ pe ọmo ilẹ Ukraine, Oleksandr Usyk ti gba bẹniti rẹ mẹtẹẹta lẹyin to lu u lalubami, AJ ni oun si le ja lai si awọn bẹniti yii. Usyk ya agbado ha sawọn eeyan lẹni lalẹ ọjọ Abamẹta lẹyin to fi ẹṣẹ gbade ori Joshua. Ṣugbọn ohun ti Joshua n sọ bayii ni pe oun kọkọ fẹ gba bẹniti oun pada lọwọ Usyk. O ni lẹyin naa ni oun le rona ati ba Fury ja. Ó bà ni kò bàjẹ́, ẹ wo ọ̀rọ̀ tí Anthony Joshua sọ lẹ́yin tí Usyk fẹ̀ṣẹ̀ gbadé orí rẹ̀ láìròtẹ́lẹ̀ Iku ogun nii pa akinkanju, iku odo nii pa omuwẹ, odo ti a ba foju di nigba mii maa n le gbe ni lọ. Abẹṣẹkubiojo Anthony Joshua ti sọrọ soke lẹyin ti akẹṣẹ jẹun ọmo ilẹ Ukraine, Oleksandr Usyk fẹṣẹ gbade lọwọ rẹ niluu London lalẹ ọjọ Abamẹta. Iyalẹnu lo jẹ fun ọpọlọpọ awọn ololufẹ AJ nigba ti Usyk bẹrẹ si ni rọ ojo ẹṣẹ le e lori ti ko si lee ta putu. Gbogbo awọn oludajọ ija lo ni Usyk lo bori AJ pẹlu ayo 117-112, 116-112, 115-113 ni papa iṣere ẹgbẹ agbabọọlu Tottenham niluu London. Ọpọ lo ti ro pe Joshua yoo fi ẹṣẹ dabira si Usyk lara ṣaaju ija wọn, ọrọ bẹyin yọ nigba ti wọn bẹrẹ si ni lewọ sira wọn. Ẹwẹ, Joshua ti fi ọrọ ranṣẹ sawọn ololufẹ rẹ lẹyin to fidi rẹmi tan niluu London. AJ ni o ba ni, ko bajẹ, ''ọmọ akin, maṣe ba ọkan jẹ, koda gbogbo aye le maa wo lulẹ niwaju rẹ. Ẹyin araalu London mo nifẹ yin gan an, ẹ ṣe mo dupẹ gbogbo eeyan, ẹ ku gbogbo igba ti ẹ n gbaruku ti mi.'' 'Eniola Badmus wọ pátá lọ sí ààfin Oba Elegushi, ""ọ̀ín"" kí ló burú níbẹ̀?' Ọmọ ẹgbẹ́ PDP Oyo tí inú bá ń bí, ẹ kó ""mo kó - mo rò"" yín wá ká yanjú ẹ̀ - Makinde Ọkùnrin kan tó jẹ gbèsè N4.6m ni wọ́n so mọ́lẹ̀ bíi ewúrẹ́ Onigbọwọ Joshua naa, Eddie Hearn ti sọ ero rẹ lori bi Joshua ṣe fidi rẹmi ninu ija oun ati Usyk. Hearn ni o ṣeeṣe ki Joshua ti fi oju ṣeṣe tori ko le riran daadaa mọ nigba ti ija naa de ipele kẹsan an. Usyk ti di abẹṣẹkubiojo lagbaaye bayii lẹyin to gba bẹniiti mẹta lọwọ Joshua.",0,yoruba "O ti pẹ ti awọn ọlọpa ti kede pe awọn n wa melaye Gẹgẹ bii iroyin naa ṣe sọ, awọn ọlọpaa mu Sẹnetọ Melaye ni papakọ ofurufu Nnamdi Azikiwe nilu Abuja. Asiko to n lọ si orilẹede Morocco fun isẹ ilu ni wọn mu Melaye. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: O ti pẹ ti awọn ọlọpa ti kede pe awọn n wa melaye lori ẹsun didi ihamọra nnkan ija ogun fun awọn janduku kan. Awọn janduku naa ni wọn darukọ Sẹnetọ Melaye nigba ti ọwọ awọn agbofinro tẹ wọn ni ipinlẹ Kogi.",0,yoruba "Bonkẹlẹ lo ṣe e ṣa toripe gbogbo eto igbeyawo ọhun ko han si awọn ololufẹ rẹ rara ni gbangba. Wo ohun tí Professor Peller wí tó kó bá a gẹ́gẹ́ bí ìyàwó rẹ̀, Lady Peller ṣe tú u síta Ninu awọn fọto ati fidio to fi sita lori ayelujara funrarẹ ni awọn akẹgbẹ rẹ ti n ki i ku oriire to fi mọ awọn ololufẹ rẹ gẹgẹ bi o ṣe ro dẹdẹ to kan dẹdẹ ninu aṣọ igbeyawo funfun balau to balẹ dẹdẹ. Awọn ami taa ri lati mọ boya Sotayo ṣe igbeyawo Sotayo Gaga kọ ọ sita si oju opo rẹ pe ""bo tilẹ jẹ kii ṣe eni (ọjọ Satide) ni igbeyawo yii waye, mo kan yan lati fi sita loni ni, Mo dupẹ lọwọ gbogbo eniyan fun ọrọ ikini ati adura. Ọlọrun a bunkun yin"". O tun dupẹ lọwọ awọn ileeṣẹ to ṣe e loge ara, awọ, aṣọ ati irun to jẹ ara ọtọ fun igbeyawo rẹ. Bakan naa ni ọjọ bii mẹta ṣaaju ọj to fi fọto sita, lara awọn esi lori fọto kan to fi sita to ti wọ iro ati buba ni ọkan lara awọn akẹgbẹ rẹ ti ki i ku imura iyawo amọ to tilẹ n ya awọn ololufẹ rẹ mii lẹnu pe imura iyawo kẹ. Nigba ti a fi n ko iroyin yii jọ, atẹjade rẹ ti fa ọpọlọpọ esi mọra lati ọdọ awọn oṣere akẹgbẹ rẹ ti wọn n yẹ ẹ si atawọn ololufẹ rẹ gbogbo. Lara awọn akẹgbẹ rẹ to ti ki i ku oriire ni ni Odunlade Adekola, Iyabo Ojo, Wumi Toriola, Kolawole Ajeyemi, Itele, Funke Akindele, Femi Adebayo, Bimbo Oshin, Bimpe Akintunde, Temitope Solaja. Bẹẹ naa ni awọn to sun mọ ọ n tun fọto rẹ lo loju opo tiwọn naa lati ba a yọ ayọ igbeyawo. Amoṣa lori ọrọ aridaju, iroyin kan n fihan pe awọn kan sibẹ lagbo oṣere n sọ pe ko ṣegbeyawo rara. Ẹwẹ, iyawo funrarẹ naa ko kọ orukọ tabi fi fọto ọkọ rẹ si oju opo rẹ rara.",0,yoruba "Bayelsa: Douye Diri di gómìnà Bayelsa lẹ́yìn ìbúrawọlé, iléeṣẹ́ ọlọ́pàá kéde kóńlé ó gbélé",0,yoruba iya mi baba won bi mi da emi gangan mo tun tunra bi lorukoo mi shayn ga si ka soro ka ba be ni iyi omoluwabi,0,yoruba bí a bá ní sùúrù ohun tí kò tó ṣì ńbọ̀ wá ṣẹ́kù if we are patient whatever is insufficient would be excessive,0,yoruba "Ojúmọ́ ire ni o. Ojúmọ́ ire ni. Ojúmọ́ ire ni o. Ojúmọ́ ire ni, Ilẹ̀ t'ó mọ́ mi lónìí o, Ojúmọ́ ire ni!",0,yoruba ìtàn yìí jẹ́ ohun tí ó ṣẹlẹ̀ ni ìgbà ogun abẹ́lé nàìjìrìà ni ọdún sì ọdún lójijì ni mo ké pé fáyà ohun tí,0,yoruba "Ọba fè se, Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "Nígbà àkerekere, Ọba ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba ènìyàn yì í tún ṣe àwọn iṣẹ́ tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ẹkọ́: ti o ní wúlò.,0,yoruba "ọba. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba àìmọ́. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa òkè: ti o ní wúlò.,0,yoruba "Amọ ti Wolii obinrin Mistura Oseni Akintunde yatọ, ẹni to n sisẹ wolii nilana ẹsin Islam yatọ. Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ lori iwa ifipabanilopọ, Wolii Akintunde ni kii se bi obinrin ba se mura lo n fa iwa ifipabanilopọ, gẹgẹ bi awọn eeyan kan se lero. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Amọ o salaye pe bi a ba se wo ara wa loju si, boya ọkunrin ni abi obinrin lo n fa iwa ifipabanilopọ. Akintunde fikun pe, kii se awọn ọkunrin nikan lo n huwa ifipabanilopọ, gẹgẹ bi awujọ wa se lero, amọ awọn obinrin gan n fipa bani lopọ, ko si yẹ ka maa pariwo awọn ọkunrin nikan. O wa tako ẹwọn ọdun mejidinlogun ti wọn n fun awọn eeyan to n fipa bani lopọ, eyi to ni ko to fun ijiya ẹsẹ wọn . Bakan naa lo rs awọn eeyan lati ye ko awọn ti wọn ba fi tipa ba lopọ laya jẹ lori ayelujara, amọ n se lo yẹ ki wọn sewuri fun wọn lati jade sita sọ tẹnu wọn.",0,yoruba "ọ̀gbọ́n. Alàji lo ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba ilera ṣẹlẹ ni Ibadan ti gbogbo eniyan sọ o dara. (1998),0,yoruba Àìmọ́ ni ó pa Ọmọ lo ojú odò. ọsẹ àlùfáà. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba "Kọmisọnna ọlọpaa ni ipinlẹ Eko, Imohimi Edgal to fi eyi lede ninu atẹjade bu ẹnu atẹ lu ọrọ ti Ọga ọlọpaa Abayọmi Shogunlẹ sọ ni Ọjọ Isẹgun pe awọn ọmọ Naijiria lẹtọ labẹ ofin lati ofin lati ni ibalopọ ninu ọkọ ni ojutaye. Edgal ni ile isẹ eto idajọ ni ipinlẹ Eko ti gba ile isẹ ọlọpaa ni imọran wi pe ohun itiju ati ohun to ba ni loju jẹ ni ki akọ ati abo ma a ba ara wọn ni ibalopo ni ita gbangba. O fikun wi pe iwe ofin ipinlẹ Eko to nii se pẹlu iwa aito lawujọ sọ wi pe ẹni to ba wu iru iwa bẹẹ lawujọ yoo fi ẹwọn ọdun meji si mẹta jura gẹgẹbi iwe ofin to niise pẹlu iwuwasi lawujọ to wa ni Section 134 (a) ati section 136 ti iwe ofin ipinlẹ Eko. Kọmisọnna ọlọpaa ipinlẹ Eko naa wa parọwa si awọn araalu ni ipinlẹ Eko lati se akiyesi ofin wọnyii, ki wọn ma ba A lu ofin ibalopo ni gbangba ni ọjọ iwaju. Kò sí ẹ̀ṣẹ̀ nínú ìbálópọ̀ nínú ọkọ̀ - Ọlọ́pàá Igbakeji Kọmisana Ọlọpaa (ACP), Abayọmi Shogunlẹ lo kede loju opo ikansira ẹni Twitter rẹ pe kii se ẹsẹ rara fun awọn akọ ati abo lati ni ibalopọ ninu ọkọ nita gbangba. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Òkè Ìdànrè: Òkè tó kéré jùlọ jẹ́ ẹsẹ̀ bàtà 3000 Shogunlẹ, ẹni to bo ọrọ yii loju boro, lasiko to n dahun ibeere kan ti ẹnikan ju si loju opo naa, fi kun pe, bi o tilẹ jẹ pe iwa ibalopọ ninu ọkọ ko sẹ si ofin Naijiria, sibẹ, awọn gbedeke kan rọ mọ isẹlẹ yii. Gẹgẹ bo se wi, lara awọn gbedede naa ni iwọnyii: Shogunlẹ ko sai fi kun pe ti ẹnikẹni ba dun ikoko m ọmọ Naijiria kankan lori igbesẹ naa lẹyin ti wọn ba ti tle awọn ilana ofin to rọ mọ sise bẹẹ, ki wọn yara kan si ohun kia-kia. Sugbọn lati igba ti Shogunlẹ ti n sọrọ yii, ni awn ọmọ Naijiria ti n gba ọrọ naa mọ ara wọn lọwọ, ti wn si n fi ero wọn han nipa rẹ loju opo Twitter wọn bẹẹ naa ni wn n fesi si ohun ti Shogunl sọ loju opo Twitter rẹ. Bi awọn eeyan kan si se faramọ abala ofin naa ni awọn kan ta ko ofin yii @Ibukun_olu, o ni bi o tilẹ jẹ pe ko si ofin kankan to tako ibalopọ ninu ọkọ loju taye, sibẹ, wọn lee gbe awọn eeyan to ba da asa yii wo pẹlu ẹsun aini iwa ọmọluabi. O ni abala ojilerugba o din mẹsan ofin iwa ọdaran ilẹ wa lo sọrọ nipa awọn iwa kotọ lawujọ. O si wa lọwọ ileẹjọ lati sọ boya nini ibalopọ ninu ọkọnita gbangba jẹ iwa kotọ , paapa, taa ba wo wo ọkọ ti wọn lo jẹ dukia adani. @OsaAOsula, o dup pupọ lọwọ Shogunlẹ fun alaye to se lori ọrọ yii, amọ o wa n beere pe ki wa ni itumọ sisi ara silẹ lọna aitọ? @PatrickOkouzi, iwa nini ibalopọ ninu ọkọ ni ita gbangba lee sokunfa ijamba ọkọ tabi iwa ajẹbanu, ko si yẹ ka gbaa laaye.",0,yoruba Nítorí ìfẹ́ tí ẹyẹlé ní sí olówó rẹ̀ làwọn àgbà fi ní “ẹyẹlé kì í bá onílé jẹ́; bá onílé mu kí ó di ọjọ́ ikú kò yẹ orí”. #BiEyekoSeDiEyele,0,yoruba @user Rẹpẹtẹ ni. Èmi ò lè wá kú o :),0,yoruba "Burna Boy Loju opo ayelujara awọn alakoso eto ami ẹyẹ Grammy, ni wọn ti kede pe orukọ Burna Boy wa ninu akọsilẹ orukọ awọn eeyan ti wọn n woye fun ami ẹyẹ. Isọri ami ẹyẹ ti wọn si fi orukọ Burna si ni ami ẹyẹ fun orin agbaye to fakọyọ julọ (Best World Music Album), orukọ awo orin rẹ to gbayi ti wọn fi faa kalẹ ni African Giant. Ikede yii ti wa n mu ki awọn ọmọ Naijiria, akọrin ati awọn ololufẹ rẹ maa kan sara si loju opo Twitter rẹ pe o ku oriire. Awọn akọrin miran ti wọn ti fa kalẹ fami ẹyẹ Grammy ṣaaju: Angelique Kidjo lakọrin kan to ti gba ami ẹyẹ ni ipele ti wọn fa Burna Boy kalẹ fun yii. Lọdun 2016 si lo gba ami ẹyẹ naa. Bi a ba ni ki a wo awọn akọrin lorilẹede Naijiria ti wọn ti fa kalẹ fun ami yii, wọn ṣe bii ẹni pọ diẹ. Lara wọn la ti ri King Sunny Ade ti wọn fa kalẹ lẹẹmeji ọtọọtọ lọdun 1983 fun awo orin rẹ ti wọn pe ni 'Synchro System'. Bẹẹ ni wọn fa awo orin rẹ miran 'Odu' kalẹ lọdun 1998 ni isọri ami ẹyẹ ti Burna Boy n dije fun bayii. Awọn akọrin miran to tun ti kọrin gba idanimọ yii ni:",0,yoruba Ìbàdandun ni ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn. (Item 164),0,yoruba Fún àwon atọ́ka-árò lágbára lórí àwọn bọ́tìnì ìpamọ́,0,yoruba "Ile igbimọ Asofin agba ni ẹka asofin to ga julọ lorilẹede Naijiria Ile asofin agba buwọlu aba to fofin de tita siga leyọ ẹyọ Adari ipolongo fun ajọ Environmental Rights Action ati ti Friends of the Earth Nigeria (ERA/FoEN) Philip Jakpor, nigba to n ba BBC sọrọ, wipe idunnu lo jẹ fun awọn nigba tawọn asofin agba fọwọsi aba lati fopin si tita siga layika ile-ẹko, ti ko si si eni to tako aba ofin naa. Iparọwa si gbogbo awọn tọrọ naa kan lati ri wipe aba ofin naa mulẹ lorilẹede Naijiria Adari ipolongo naa wa parọwa si gbogbo awọn tọrọ naa kan lati ri wipe aba ofin naa mulẹ nigbogbo ẹka ati ẹya to wa lorilẹede yi, ki ọjọ iwaju awọn ọdọ le wuyi pẹlu ilọsiwaju to lamilaaka lorilẹede yii. Igbese ti ajo ERA gbe lati koju tita siga lagbegbe ile ẹkọ Senato Remi Tinubu, nigba to n ba ile igbimọ asofin agba sọrọ wipe, siga mimu le fa aisan jẹjẹrẹ ọna ọfun ati awọn aisan mii to le se ipalara fun ẹjẹ ati ọkan awọn eniyan. O si ran awọn asofin leti wipe sise ipolongo siga fun awon eniyan tako ofin orillẹede Naijiria lori isakoso taba fifin ti wọn n pe ni (Framework Convention on Tobacco Control (FCTC ) ati ti (National Tobacco Control Act ) tọdun 2015.",0,yoruba "Ti eeyan ba wa ninu igbeyawo oni jagidijagan, awọn iwa ipa naa ma n wa lemọ lemọ ni, bii eebu ati ilu bara Koda, ajọ iṣokan orilẹde agbaye, UN, ti sọ pe ajakalẹ arun kan ni ki obinmrin maa ni idojukọ ninu igbeyawo wọn, papa pẹlu ọkọ oniwa ipa. Kini ohun to yẹ ki eeyan ṣe to ba n ni idojukọ ninu igbeyawo rẹ lasiko yii? A bere lọwọ awọn to ti la iru nnkan bẹ kọja lati sọ iriri wọn ati awọn ohun ti eeyan lee ṣẹ to ba n ni idojukọ ninu igbeyawo rẹ, pẹlu ọkọ oniwa ipa.. Arabirin kan, Esther ṣalaye fun akọroyin wa pe ""Ti eeyan ba wa ninu igbeyawo oni jagidijagan, awọn iwa ipa naa ma n wa lemọ lemọ ni, bii eebu ati ilu bara."" O tẹsiwaju pe ""Opin ọsẹ lo ma n lekenka ju nitori ko ki n si ẹnikẹni ninu ile. Fun idi eyi, ololufẹ ẹni ma n ni aye lati ṣe bo ṣe wu nigba ti ọwọ wọn ba ti dinlẹ, igba yẹn gan ni wọn ma n ri aye lati fa wahala lẹsẹ."" O ni ""Wọn ma n bẹrẹ pẹlu awọn ọrọ kobakungbe to maa mu inu bi eeyan, eyi tyo jẹ ọna ti wọn ma n gba lati fa ijọgbọn lẹsẹ."" Bi ẹni wa ninu ahamọ ""Ti idawa opin ọsẹ ba le mu ki ọkunrin lu eeyan, ẹ ro ohun ti iru ọkunrin bẹ le ṣe ti eeyan ba wa pẹlu rẹ fun oṣu. Ibẹru lọsan atoru ni iru obinrion bẹ ma n wa."" Esther ni awọn ti ko ba le fi igbeyawo naa silẹ gbọdọ wa ọna lati laa kọja O ti to ọdun diẹ bayii ti Esther ti fi ọkọ rẹ silẹ, bo tilẹ jẹ pe ko rọrun, ṣugbọn igboya lo fi gbe igbesẹ to gbe. Esther sọ pe ""Ni ṣe lo dabi ẹni pe mo wa nin u ẹwọn ti wọn fi irin yika ti mi o si le jade, o jẹ ohun to ṣoro funmi, bẹẹ naa ni mo tun n ro ti awọn ọmọ mi pẹlu. ""Nigba miran ẹwẹ, papa nile adulawọ ti iya eeyan mọ pe ọmọ rẹ obinri ti ṣegbeyawo, irufẹ obinrin bẹ ko ni fẹ kokuro nile ọkọ rẹ."" Yoo ṣoro diẹ fun ọpọ awọn obinrin ti wọn n fẹ lati kuro nile ọkọ lasiko yii nitori ofin konile-o-gbele to wa lode lasiko arun Covid-19. Ti iru obinrin bẹẹ ba dede jade kuro nile lọwọ alẹ, awọn agbofinro le da duro lọna lati ṣalayae ibi to n lọ, tabi ko ma ri ọkọ loju popo. Ọpọ awọn orilẹ-ede lo ti ṣagbekalẹ ẹrọ ibaraẹni sọrọ ti awọn eeyan le pe ti ọkọ wọn ba n lu wọn nile, ọpọ awọn obinrin lo si ti bẹrẹ si n pe awọn ẹro ibaraẹni sọrọ naa. 'Iṣẹlẹ naa n peleke sii' Ni ọsẹ akọkọ ofin konile-o-gbele, ileeṣẹ ọlọpaa South Africa gba ipe to le lẹgbẹrun meji, eyi to jẹ ti iwa ipa akọ si abo to pọ ju bo ṣe ri tẹlẹ lọ pẹlu ida mẹtadinlogoji. Nilẹ Zimbabwe, iye awọn to ti fẹjọ sun ijọba lori iwa ipa akọ si abo ti le ni ida mẹta. Ajafẹtọ ọmọniyan lori iwa ipa akọ si abo kan ni Naijiria, Dorothy Njemanze sọ fun BBC pe bi iṣẹlẹ ọhun ṣe n peleke si ni Naijiria n kọ oun lominu. Awọn orilẹede kan nilẹ Afrika ti gbe iranlọwọ dide fun obinrin to n ni idojukọ yii; fun apẹrẹ, ijọba Tunisia ti gbe nọmba ipe kalẹ fun awọn obinrin. Awọn orilẹede kan nilẹ Afrika ti gbe iranlọwọ didie fun obinrin to n ni idojukọ yii Ni Zimbabwe, awọn agbalagba mọkanlelogun ati ọmọde meje lo n gbe ile kan ti ileeṣẹ ti wọn n pe ni ""Roots One Stop Shelter"" gbe kalẹ. Adari ileeṣẹ ọhun, Beatrice Savadye ni wọn n gbiyuanju ati gba awọn eeyan naa la kurọ lọwọ iwa ipa ti wọn n dojukọ ninu ile wọn. 'Ibi ti awọn obinrin le foripamọ si' Bakan naa ni ilẹ Kenya, oṣiṣẹ awujọ kan, Dianah Kamande ni ileeṣẹ oun ṣi ni aye lati fun awọn obinrin ni abo si lẹyin to ti gba obinrin mẹtadinlogun la ni Nairobi nikan. Ni Naijiria, bo tilẹ jẹ ọpọ ibi tawọn obinrin lee foripamọ si ti di titi pa nitori ofin konile-o-gbele, awọn eeyan kan ṣi n ran awọn obinrin lọwọ lati gbawọn la kuro lọwọ ọkọ oniwa ipa. Ṣugbọn adari ile tawọn obinrin Kenya le fori pamọ si julọ, Nana Sunnu ni wọn kole gba ẹnikẹni bayii nitori ajakalẹ arun to wa lode, ati pe ibi tawọn eeyan le gbe fun anfani idanikan wa ko to nkan. Esther to ru igbeyawo oniwa ipa la ti bẹrẹ si n ṣiṣẹ pẹlu awọn akẹgbẹ rẹ to ti la iru nkan bẹ kọja ri. O rọ awọn obinrin lati kan si awọn ajafẹtọẹni loju opo ikansiraẹni ti wọn le fọkan tan. Onimọ ijinlẹ kan nipa bi eeyan ṣe n ronu nilẹ South Africa, Nthabiseng Ramothwala ni o yẹ ki awọn ara adugbo jẹ oluranwọ aladugbo wọn ti wọn lero pe o le ma la igbeyawo to ni iwa ipa kọja. Bẹẹ naa lo tun rọ awọn obinrin lati kan si awọn to sunmọ wọn fun iranlọwọ. O ni ""Ẹ mọ nọmba pajawiri ti ẹ le pe, ẹ jẹ ki awọn aladugbo yin mọ ohun ti ẹ n la kọja, ẹ sọ awọn apẹrẹ ti wọn le ri lara yin funwọn lọna ati le ran yin lọwọ. O tẹsiwaju pe ""Ẹ fun wọn ni nọmba awọn ẹbi yin ti wọn lee pe lati wa gba yin nigba ti wahala ba ṣelẹ."" Fun awọn ti wọn ko le ṣa asala fun ẹmi wọn, Esther ni imọran mii. O sọ pe ""Ko yẹ ki o dakẹ nitori pe o ko fẹ ṣẹ ẹlomiran, ti wọn ba ti n sọrọ to ba bi ẹ ninu, iwọ ṣaa maa wo ni tiẹ."" Ti wọn ba gbiyanju ati mu ẹ binu, wa nnkan mii ṣe, bii ki o kawe ti o ba fẹran tabi ohunkohun to le mu ọkan rẹ jina rere si sakani wọn."" Ti o ba le ṣaṣeyọri ninu eyi fun nnkan bi oṣu meji tabi mẹta titi di igba ti ofi konile-o-gbele yoo fi kasẹ nilẹ, o ti n bopri diẹ diẹ niyẹn."" Esther pari ọrọ rẹ pe ""A ko tii le sọ pe ọna ababyọ kan gboogi ni eyi o, ṣugbọn ti ẹmi ba wa, ireti n bẹ.""",0,yoruba Rọ́ọ̀nù Ìṣàmúlò-ètò,0,yoruba RT @user: @user @user @user @user Be ni o. Mo ka letter kan ti won ko si Oba ni Lisbon ki won ma le…,0,yoruba ayin. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọmọ lo lọ.,0,yoruba Ẹ tún fẹ́ gbé wa mọ́ra àbí? Ẹ ti pawó sápò yín tán àbí bẹ́ẹ̀ kọ́? #Nigeria @user,0,yoruba ìbadandun. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba iwa rere. Alàji lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba "ojú onà. ti Nitori eyi, ara eni lo ni ọ̀gbọ́n.",0,yoruba ọsẹ àlùfáà. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìṣẹ̀: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn wà ní ìṣẹ́ ọ̀pọ́lọ̀.,0,yoruba "Awọn eeyan ti iji Cyclone Idai ṣe akoba fun ko tii bọ lẹyin iṣẹlẹ ọhun. Awọn obinrin wọnyi ni Mozambique n to lati gba nnkan eelo lọjọ Iṣẹgun to kọja. Iya n ronu; ọmọ n roka lo ri ni Mozambique. Bi awọn iya ti ṣe n to lawọn ọmọdebinrin wọnyi n ṣa ododo nibi awọn ile ti o wo ni ilu Beira lọjọ Aiku. Jangilofa epo mọtọ! Nilu ti iji ti sọṣẹ niṣe ni awọn ọmọkunrin wọn yi n ṣere lori igi agbọn ti iji wo lọjọru Lorile-ede Kenya, awọn akẹkọọ da muso fun olukọ wọn ni papakọ ofurufu Kenya nigba to dari lati ibi ti o ti gba ẹbun $1m (miliọnu dọla kan) gẹgẹ bi olukọ to pegede julọ lagbaye Igbakeji aarẹ Naijiria ati iyawo rẹ, Dolapo Osinbajo nibi ayẹyẹ isin idupe lẹyin ti wọn wọle gẹgẹ bi igbakeji aarẹ nidibo Naijiria tó kója nilu Ikenne, ipinlẹ Ogun Lọjọ Aiku, alatilẹyin ẹgbẹ agbabọọlu Zimbabwe yi n dawọ idunnu bi ikọ rẹ ti ṣe fi ami ayo 2-0 sagba Congo-Brazzaville ninu ifẹsẹwọnsẹ lati kopa ninu idije Africa Cup of Nations Lọjọ Abamẹta, ajagunfẹyinti orile-ede Ethiopia yi n fẹsẹ rajo nibi ayẹyẹ kan ti wọn ṣe lati fi gba alejo irun ori Emperor Tewodros II ti ile iṣẹmbaye ilẹ Gẹẹsi, National Army Museum da pada si Ethiopia Lọjọ keji, oludibo yi n yẹ orukọ rẹ wo loju patako lati le kopa ninu idibo aarẹ Comoros Islands Fọfọ ni igboro Algiers kun nibi iwọde to waye lọjọ Eti. Awọn eetan orile-ede naa fẹ ki aarẹ Abdelaziz Bouteflika kọwe fipo silẹ Titi di ọjọ Ajẹ awọn eeyan Algeria ko dawọ iwọde naa duro",0,yoruba what do we call email in yorùbá language kíni a lè pe email ní èdè yorùbá also what do we call email address without using the word àdírẹ̀sì in yorùbá àti wípé kíni a lè pe email address láì yá ọ̀rọ̀ àdírẹ̀sì lò ni èdè yorùbá,0,yoruba Olùwo se. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba Rọ́ọ̀nù Ìṣàmúlò-ètò...,0,yoruba "@user Ṣé mo jọ Sányẹ̀rì ni? Ọ̀rọ̀ àwàdà kọ́ l'ọ̀rọ̀ #BBNaija yìí o. Gẹ́gẹ́ bí CDQ ti ṣe kọrin, ó ní """"""""""""""""""""""""""""""""k'ólóṣó jọ sínú ilé bíi ti..."""""""""""""""""""""""""""""""" Kò sì purọ́.",0,yoruba "Tony Bellew ṣíná fún David Haye Gbájugbajà akànṣẹ́ kù bi òjò, Bellew Tony, tó jẹ́ ọmọ ọdún marundinlogoji ti na David Haye, to jẹ́ ọmọ ọdún mẹtadinlogoji. Ilu London ni ìdíje náà ti wáyé nibi ti Ballew kò ti náání pé Haye ju òun lọ ni ọjọ́ orí àti ni ìwọn bi ó ṣe wúwo tó. Ẹẹ̀kejì rè e ti àwọn mejeeji má a pàdé Ipele karun un ìjà náà ló ti jáwé olúborí, lọ ba fayọ̀ gbé àmì ẹyẹ lọ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Tony Bellew ni ó ṣeéṣe pé ti òun kò ba pàdé ẹni tó tó ajanaku, tó kọja mo rí ǹkan fìrí, òun kò ni jà mọ́",0,yoruba ".@user pelu gbo gbo giran giran yin, ewo bi ero se ya wo @user ni Ipinle @user efara bale! http://t.co/V9HPjqsIe5",0,yoruba Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ògbufọ̀ tí ẹ̀rọ ṣe ni kò nítumọ̀ .,0,yoruba "Ko si bi eeyan ṣe lee darukọ orilẹ€de Naijiria ti a ko ni ranti oloye Oluṣẹgun okikiọla Arẹmu Ọbasanjọ. Ọmọ atapatadide to la oniruuru ipenija kọja lati de oke tente tabili irinajo rẹ laye. Ajagunfẹyin, Ọgagunagba ati oloṣelu to dantọ ti gbogbo agbaye ko lee fọwọ rọ sẹyin ni Ọbasanjọ jẹ. Ohun si ni ọmọ orilẹede Naijiria akọkọ ti yoo jẹ aarẹ gẹgẹ bii ologun ati gẹgẹ bii alagbada. Ni ọjọ karun oṣu kẹta ọdun 1937 ni a bi Oloye Ọbasanjọ ni ilu Abẹokuta. Oni yi gan an si ni o pe ọdun mẹtalelọgọrin loke eepẹ.",0,yoruba lóòótọ́ ilé gbogbo ayé ni ilé jẹ́ àtipé gbogbo wa la lèkó bí gómìnà ti ṣe sọ ọmọ èkó gbé èkó ga,0,yoruba yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba "Aarẹ South Africa, Cyril Ramaphosa ti sọ pe ọwọ ẹgbẹ oṣelu oun ni ọjọ ọla oun wa bayii, eyii to jẹ ọrọ akọkọ ti yoo sọ lati igba ti wọn  ti fẹsun iwa ibajẹ kan an. Ṣaaju ni awọn ọmọ ẹgbẹ alatako ti kọkọ sọ pe o gbọdọ kọwe fi ipo silẹ ni, lẹyin ti igbimọ awọn agbẹjọro kan fẹnuko pe o ṣeeṣe ko ti ṣẹ si ofin. Amọ agbẹnusọ rẹ sọ lopin ọsẹ pe yoo tẹsiwaju lati maa ja fun ẹtọ rẹ. Aarẹ ọhun funra rẹ ti wa sọ pe ọwọ awọn adari ẹgbẹ oun ni ọrọ naa ku si bayii lati sọ igbesẹ to kan fun oun. Awọn adari ẹgbẹ naa, Africa National Congress, ANC, ti n ṣe ipade lọwọ bayii ni niluu Johannesburg lati mọ igbesẹ to kan. Nigba to ba awọn akọroyin sọrọ nibi ipade ọhun, o ni igbimọ ẹgbẹ ANC fun oun laye lati má darapọ mọ ipade naa ki wọn le ni anfaani lati sọrọ bo ṣe ri lọkan wọn lai si ibẹru kankan. O ni “Ọwọ awọn ọmọ igbimọ adari ẹgbẹ lo ku si bayii, oun ti wọn ba si sọ ni mo maa tẹlẹ.” Wahala naa bẹrẹ fun Ramaphosa ninu oṣu Kẹfa ọdun 2022 yii, nigba ti agba ọtẹlẹmuyẹ ọmọ South Africa kan, Arthur Fraser kọ iwe si agọ ọlọpaa, to si fẹsun kan Aarẹ Ramaphosa pe o lu owo ti iye rẹ  miliọnu mẹrin dọla ni ponpo nipaṣẹ oko rẹ, Phala Phala game farm lọdun 2020. Ramaphosa ni lootọ ni owo naa sọnu, amọ owo naa ko ju ẹgbẹrun lọna ẹgbẹta dọla lọ, dipo miliọnu mẹrin ti ọkunrin naa pe. Ramaphosa tun sọ pe owo naa wọle lẹyin ti oun ta ẹranko ẹfọn kan, amọ igbimọ oluwadi to n ṣe iwadii ẹsun naa ni o ṣoro lati gba ọrọ Ramaphosa gbọ. Wayi o, agbẹnuṣo Ramaphosa, Vincent Magwenya ti sọ pe Aarẹ ọhun ko ṣetan lati kọwe fi ipo rẹ silẹ nitori ẹsun ti ko lẹsẹ nilẹ.",0,yoruba RT @user: Asa igbeyawo ile yoruba Ifojusode Alarina Isihun Itoro Idana Ipalemo Igbeyawo How person go just dey ifojusode for ages.…,0,yoruba ó ku ọjọ́ mẹ́wàá fi iṣẹ́ rẹ ránṣẹ́ sí wa wo,0,yoruba "Julian sọ pe to ba jẹ pe oun feti si ọrọ awọn eniyan ni, oun i ba ti maa ro pe otitọ ni nkan ti wọn n sọ. Lẹyin ọdun mejila to mọ nipa ailera rẹ yii lo sọ itan igbesi aye rẹ fun BBC. ""Wọn bi mi pẹlu ipenija ilera kan ti wọn n pe ni Mayer-Rokitansky-Kusher-Hauser syndrome (MRKH). Ailera yii tumọ si pe ẹni naa ko ni i ni ile ọmọ, tabi oju ara obinrin, o si tun le jẹ kindinrin kan pere ni iru ẹni bẹ yoo ni. Obinrin to ba ni MRKH kii ṣe nkan oṣu. Igba ti mo wa ni ọmọ ọdun mẹtadinlogun ni mo ri i pe mo ni ailera ni ẹsẹ mi i, nitori pe gbogbo igba lo maa n wu. Nkan akọkọ ti dokita kọkọ beere lọwọ mi ni pe igba wo ni mo ṣe nkan oṣu kẹhin. Ṣe emi ti mi o mọ bi nkan oṣu ṣe n ri? Wọn ya aworan (scan), iyẹn si fihan pe mi ko ni ile ọmọ tabi oju ara obinrin. Ibẹ si ni wọn ti sọ pe mo ni ailera MRKH. Mo sun ṣege ẹkun lọjọ akọkọ, ọjọ keji ati ọjọ kẹta, ki n to o gba kamu. 'Obinrin jẹ amuludun' Ọmọde ṣi ni mi, ọmọ ọdun mẹtadinlogun. Nkan to si wa ni ọkan mi ni bi maa ṣe pada sileewe. Iya a mi tẹle mi lọ si ileewosan, nkan ti dokita si sọ fun ba a l'ẹru. Ọpọlọpọ ibeere lo wa ni ọkan rẹ lati beere. Lo ba bẹrẹ si ni ro o pe ta a ni oun ṣẹ to fi iru nkan bẹ kan ọmọ oun. 'Nkan to ba wu ẹlẹnu ni ko fẹnu rẹ sọ, fila ma wo ibẹ ni mo de' Ẹnikan tilẹ sọ fun mi pe ki n lọ si ibi ti wọn yoo ti gbadura fun mi. Julian Peter da ẹgbẹ kan silẹ fun awọn to ni aarun yii, wọn si maa n gba ara wọn ni imọran Ẹlomiran sọ pe aye mi ri bẹ nitori ibi ti mo ti wa, Ukambani (agbegbe kan ti wọn sọ pe awọn ajẹ wa). Awọn miran sọ pe iya-iya mi lo wa nidi ọrọ mi. Wọn le sọ nkan to ba wu wọn. Nkan to ṣe koko ni ipa to ni lara mi. To ba jẹ pe mo feti si ti wọn ni, mi o ba ti maa ro pe otitọ ni nkan ti wọn n sọ. Ẹ̀mí kan náà ló n darí ìrìnàjò wa táa fi jọ kọ́lé papọ̀- Ìbejì 'Mi o kọkọ fẹ ẹ ṣe iṣẹ abẹ naa' Nitori pe mo ti kọ ẹkọ nipa ẹya ara tẹlẹ, oye nkan ti dokita sọ nigba akọkọ ye mi. Mo sọ fun iya mi pe mi o ti i ṣetan lati ṣe iṣẹ abẹ, nitori pe mo kọkọ fẹ ẹ pari ẹkọ mi. Ọdun mẹwa lẹyin rẹ, mo lọ sileewosan naa, wọn ṣe iṣẹ abẹ fun mi, o ṣi yọri sirere. Iru ailera MRKH ti mo ni tumọ si pe mi ko ni oju ara obinrin, ile ọmọ, ati pe kindinrin kan ṣoṣo ni mo ni. Jawahir Roble:Hijab tí mò n lò kó jẹ́ kọ́kọ́ jẹ́ ìyàlẹ́nu fún àwọn agbábọ́ọ̀lù mi Igbaye mi ri boṣeyẹ ko ri, nitori pe aarun naa ko ni ipa lori bi mo ṣe fẹ gbe igba-aye mi. Ṣugbọn fun awọn eniyan kan, o maa n ba wọn ni ọkan jẹ, wọn si gbọdọ ri awọn akọṣẹmọṣẹ to le ranwọn lọwọ lati gba kadara lori aarun naa. Ti o ba ni oye ipa ti aarun naa n ni ni ara, o ko ni yọ ara rẹ lẹnu pe o fẹ ẹ bimọ. Mo ti ya fọto ara (scan) lẹẹmẹrin, wọn ko si ri ọpa to n gbe ẹyin lọ sile ọmọ, pe boya wọn le ri ẹyin ọmọ lati lo ilana igbalode IVF, fun mi ki n le di ọlọmọ,ṣugbọn ko ṣe e ṣe. Obinrin Akansẹ: Ẹsẹ kiku bi ojo kọ mi lati di alagbara Mi mọ pe o ko dabi awọn obinrin yooku jẹ ọgbẹ ọkan, ṣugbọn o kan nilo lati gba bẹ, ki o si wa ẹni ti o le fi ọrọ lọ. Mo ti ṣalabapade ọpọ eniyan ni Kenya yii to ni iru aarun yii, a si n sọ iriri wa fun'ra wa. Mo ti gba kadara tipẹ-tipẹ. Sisọ fun awọn ololufẹ mi Mo ti rinrinajo ifẹ lọpọlọpọ. Ṣugbọn, mi o ki n jẹ ko pẹ ti mo ti maa n jẹ ki ẹni naa o mọ nkan ti mo n ba a finra. Ti wọn ba fẹ ẹ gba, wọn a gba. Ṣugbọn, ṣe ẹyin naa mọ pe eniyan ẹlẹran ara naa ni eniyan yoo ma a jẹ. Ọpọlọpọ awọn ti mo sọ fun fimi silẹ. Awọn kan ti ẹ sọ pe irọ ni mo n pa, pe ọna lati le awọn lọ ni mo ṣe sọ bẹ ẹ. Lọwọlọwọ, mi ko ni ololufẹ kankan. Àwọn ọkùnrin tó wà nínú ayé wa gbúdọ̀ bọ̀wọ̀ fún wa - Adarí FIN To ba jẹ tori ibalopọ ni, mo ṣe iṣẹ abẹ l'ọdun 2018, eyi ti yoo mu ki o ṣeeṣe fun mi. Ṣugbọn, mi o ti i ṣetan lati ni ibalopọ, mi o si ṣetan lati ṣegbeyawo. Ti asiko ba to, a o gba ọmọ tọ. O gba mi to ọdun mẹwaa ki n to pinnu lati sọ ọrọ aye mi sita. Awọn eniyan wa ti ko mọ nipa MRKH, mo fẹ ẹ polongo faraye.",0,yoruba "ó tìkẹ́ gbfi yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba Sex party: Ìjọba gbé ilé ijó oníhòhò tì pa lórí ẹ̀sùn títàpá sí ìlànà àti dẹ́kun coronavirus,0,yoruba "Ǹ jẹ́ ó wù yín kí gbogbo ọmọ tí ẹ bí jẹ obìnrin? Ajọ iṣokan agbaye U.N.O. lo ya ọjọ naa sọtọ lọdun 2012 lati jẹki awọn eeyan mọ awọn ipenija ti awọn ọmọbinrin n koju ninu eto ẹkọ, ounjẹ jijẹ, ati fifi ọmọdebinrin lọkọ. Iwadii fi han pe awọn ọmọbinrin to wa lagbaye le diẹ ni biliọnu kan. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Orilẹede Naijiria naa darapọ mọ gbogbo eeyan lagbaye lati sayẹyẹ ayajọ ọjọ ọmọbinrin. Ọrọ pọ ninu iwe kọbọ lori ayajọ ọjọ ọmọbinrin lagbaye lori ayelujara Twitter. Malala Yousafzai to jẹ ajafẹtọ ọmọbinrin, to si ti gba ami ẹyẹ Nobel Peace, sọrọ loju opo rẹ pe o ṣe pataki lati mu ra ọmọbinrin silẹ loni fun iṣẹ lọjọ ọla. O fi kun ọrọ rẹ pe o tun ṣe koko lati din iyato to wa laarin owo oṣu ọkunrin ati obinrin ku lagbaye. Akẹkọọbinrin kan ti orukọ rẹ n jẹ doyinsola sọ pe o ṣe pataki lati fun ọmọbinrin ni ẹkọ to ye kooro nitori eyi lo maa jẹki idagbasoke ba orilẹede lapapọ O salaye pe oun fẹ lọ kẹkọ ni fasiti pẹlu erongba lati ṣe imoriwu fun awọn ọmọbinrin lagbaye. Arabinrin Georgina Ndukwe ni oun nigbagbọ ninu awọn ọmọbinrin pe wọn lagbara lati yi aye pada si rere ti wọn ba fun wọn laaye. Afolabi Olajide sọ pe o yẹ ki awọn eeyan maa bọwọ fun ọmọbinrin lawujọ, o ni o ṣe pataki lati ṣe itọju wọn daadaa.",0,yoruba "àìlẹ̀, Ọba ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa òkè:.",0,yoruba orò ló ni àròpe ọdẹ ló sun ìjálá ìyẹ̀rẹ̀ n tifá ni ti egúngún,0,yoruba "oníṣẹ́ ìṣẹ́ ni a ní nípa ire àti ìbàdandun, àwọn ẹ̀kọ́ ọmọ aláwọ̀ wà níṣẹ̀.",0,yoruba owuro lojo eni ma rire e ku ojumo oooo,0,yoruba Ó jẹ́ agbègbè kan tí ó lọ́rọ̀ jù ní àgbáyé .,0,yoruba ìṣẹ́ ni a ní nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò.,0,yoruba Ó kọ ọ́ sínú ìwé náà wípé :,0,yoruba "Ààrẹ Muhammadu Buhari wa lorílẹ̀èdè China làti lọ se ìpàdé tó dá lórí ìbásepọ̀ láàárín ilẹ̀ Afirika ati China. Loju opo Twitter rẹ o sọ wi pe ki awọn eeyan ma se ka ọrọ ti awọn kan n sọ wipe panpẹ ni ẹ̀yáwó $328 million ti Nàìjíríà fẹ yà lọ́wọ́ orílẹ̀èdè China jẹ kun. ''Orileede Naijiria lagbara ti o si setan lati san gbogbo owo ti wọn ba ya pada nigba to ba yẹ ni ibamu pẹlu eto inawo to yanranti.'' End of Twitter post, 1 Buhari so pe ibasepọ laarin Naijiria ti orileede China laarin ọdun mẹta sẹyin ti se okunfa sise isẹ lori awọn nnkan amayerọrun orisirisi ti owo wọn le ni billionu maarun dola. O ni laipe yi ni Naijiria ati China buwọlu iwe adehun lati fikun ise lori ọkọ oju irin ti wọn sẹsẹ se ati lori ètò ìbáraẹnisọ̀rọ̀ àti ìmọ̀ ẹ̀rọ. Laipe yi ni iroyin kan ti awọn kan si bẹnu atẹ lu bi Aarẹ Buhari ti se fẹ gba ẹ̀yáwó $328 million lọ́wọ́ orílẹ̀èdè China. Ẹ̀yáwó yí jẹ́ àfikún un gbèsè $73 billion tí orílẹ̀èdè Nàìjíríà ti ń jẹ tẹ́lẹ̀. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Nínú àtẹ̀jáde tí ilé iṣẹ́ ààrẹ gbé jáde lọ́sẹ̀ tó kọjá, wọ́n ṣàlàyé wí pé ó wà láàrin ilé iṣẹ́ Galaxy Backbone ti Nàìjíríà àti Huawei Technologies ti China fún ìdàgbàsókè ìbaraẹnisọ̀rọ̀ àti ìmọ̀ ẹ̀rọ gẹ́gẹ́ bí àlàkàlẹ̀ ètò ìṣèjọba ààrẹ Buhari. Buhari ṣe ìpàdé pẹ̀lù àwọn ọmọ Nàìjíríà ní China Aarẹ orileede Naijiria Muhammadu Buhari ti se ipade pẹlu awọn ọmọ Naijiria to wa ni orileede China. Nibi ipade naa,o fi da wọn loju pe oun ko ni ifoya nipa sise eto idibo eleyi toyanrantin ''Eru idibo ti ko lẹjanbakan ninu ko ba mi nitori iru idibo bẹẹ lo gbemi wọle'' Loju opo Twitter iile isẹ ijọba orileede Naijiria ni fọnran fidio ti Aarẹ Buhari ti sọ ọri yi wa. Ìpàdé FOCCAC yoo ma jiroro lori ọna ati tunbọ mu idagbasoke ba orileede Afrika ni ifọwọsowopọ pẹlu China Ipade oun to waye ni ile ise orileede Naijiria ni China ni akọkọ ipade Buhari lati igba to ti gunlẹ si China fun ipade ẹlẹẹkeje ti yoo waye ni ọjọ kẹta si ikẹrin ni Beijing. Awọn aworan miran re lati ibi ipade naa: Aworan yi se afihan Aarẹ Buhari pẹlu awọn ọmọ Naijria ni China to n kẹkọ nipa irinajo ọkọ oju irin Asisat Oshola agbabọọlu OBINRIN Naijiria to n gba bọọlu jẹun ni China naa sọrọ nibi ipade oun Sẹnetọ mẹrin ati Gomina Ipinle Akwa Ibom tẹlẹri, Godswill Akpabio to sẹsẹ kuro ni ẹgbẹ oselu APC lọ si PDP wa lara awọn to tẹle Aarẹ Muhammadu Buhari lọ si China. Awọn minisita mẹsan ati gomina mẹrin lati ẹgbẹ oselu PDP naa wa lara awọn adari osisẹ ijọba to tẹlẹ Aarẹ Buhari. Orukọ awọn ti yoo tẹle Aarẹ Buhari lọ si China. 'Wiwa ọkọ Baalu da bi ki ẹ lọ da duro sori apata'",0,yoruba ohun tí à ń wá lọ sí ṣókótó wà lápòo ṣòkòtòo wa ọ̀kanòjọ̀kan igi ń bẹ nílẹ̀ yìí tí yó fọ ẹnu mọ̀ ṣáká,0,yoruba a wí fún yín kí ẹ dá padà ẹ kọ̀ ṣé ó wá tán báyìí àbí kò tán,0,yoruba ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún àwọn olórogun...,0,yoruba "Ire owó dà wá o, igìrìrì, igìrìrì. Ire gbogbo! #Iwure",0,yoruba "ojú òní. ti Nitori eyi, ara eni lo ni ìwájú.",0,yoruba Ènìyan ti nilo oṣiṣu fun ẹkọ́ tabi ìkalo.,0,yoruba "Abala 24 Òfin Ẹ̀ṣẹ̀ orí - ayélujára fi ẹ̀sùn kan “ ẹnikẹ́ni tí ó bá tan iṣẹ́ - ìjẹ́ tí kò ní òótọ́ kan nínú , tí ó lè fa ìbínú , ìnira , ewu , ìdíwọ́ , àfojúdi , ìdáyàfò ọ̀daràn , ọ̀tá , ìkórìíra , tàbí ìbínú láì ní ìdí sí ẹlòmíràn ká tàbí fa kí a fi irúfẹ́ iṣẹ́ - ìjẹ́ bẹ́ẹ̀ ránṣẹ́ . """"""""",0,yoruba "ni ìgbà mi owó àkokò, Olùwo ri Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba Àwọn aṣojú - ṣòfin tí ó wà lẹ́yìn ìwé àbádòfin ẹ̀rọ alátagbà náà,0,yoruba "Awọn agbagba naa sọrọ ni ilu Ibadan nigba ti adari wọn, Adajọ agba 'Demola Bakre (retd.) ba awọn oniroyin sọrọ. Bakre ni idibo awọn ọmọ Naijiria lati mọ ipinnu wọn lori atunto orilẹede Naijiria ni ọna abayọ, kii ṣe ki a fi ojojumọ ma a yi ofin orilẹede Naijiria pada. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ''Ofin Naijiria ti ọdun 1999 ṣe eke nipa sisọ wi pe awọn ọmọ Naijiria lo kọ ọ, nigba ti o jẹ wi pe awọn eniyan perete lo parapọ gbe ofin naa kalẹ.'' SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike ''Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari ko gbọdọ fi falẹ mọ, nipa gbigbe abadofin ti yoo fayegba awọn ọmọ Naijiria lati dibo boya wọn fẹ atuntọ Naijiria abi bẹẹ kọ.'' Ẹgbẹ awọn agbagba nilẹ Yoruba naa ni o kọ awọn lominu, pẹlu bi aarẹ Buhari ati ijọba rẹ ṣe kọ eti ikun, si ibeere awọn eniyan fun atunto orilẹede Niajiria. Bakan naa lori ijinigbe to wọpọ ni ilẹ Yoruba, YCE ni asiko ti to fun awọn gomina lati ṣiṣẹ ni kiakia, lori ikọ Amọtẹkun ki wọn le tete bẹrẹ iṣẹ. Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife Ninu ọrọ rẹ, Bakre ni ọwọ awọn gomina ni ilẹ Yoruba ni ọrọ naa kusi, nitori awọn Ile Igbimọ Asofin ni ipinlẹ kọọkan ti buwọlu abadofin naa, ti wọn si ti bẹrẹ igbanisiṣẹ lati koju ijinigbe lagbegbe wọn. Apẹẹrẹ awọn orilẹede to ti ṣe ibo lati yapa kuro lara ajọ kan ni Ilẹ Gẹẹsi .ti wọn kuro ni Ajọ Ilẹ Yuroopu (EU), lẹyin ti awọn eniyan dibo( referendum) lati kuro.",0,yoruba RT @user: Ǹjẹ́ ẹ mọ̀ pé Ọ̀rúnmìlà bàbá Àgbọnìrègún ma ń ran gbogbo àgbáyé lọ́wọ́ lọ́jọ́ ayée ẹ̀. @user #tweetYoruba #Ifa,0,yoruba "Ọkan tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.. Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "Iku n ro dede lori awon omoolomo, Ijoba wa se iwa si ni eyi ti e n wu yii e si n wo won niran #savebagega",0,yoruba kakaaki. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó ga ju lọ nínú Nàìjíríà.,0,yoruba "wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn ẹ̀kọ́ ọmọ aláwọ̀ wà níṣẹ̀.",0,yoruba yi gbe ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn olórogun...,0,yoruba "ni ìbàdandun àtọ́wọ́dá, àwọn oníṣẹ́ ìṣẹ́ ni a ní nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún gbogbo.",0,yoruba "“ Nígbà yẹn , nígbà tí mò ń wa ilẹ̀ , àwòrán - ìtọ́nà yìí ni mo tẹ̀lé .",0,yoruba "@user @user @user @user @user @user Have u forgotten so quickly what #yoruba say about 'ise logun ise, mura sise ore MI, Ise lafi n di eni giga'",0,yoruba nípa àlùfáà. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ìyá lo tun se joko.,0,yoruba "Onimọ nipa ọrọ eto aabo, Ọgbẹni Richard Amuwa to ba BBC Yoruba sọrọ, lo woye bẹẹ. Ọgbẹni Amuwa sọ pe awọn ara ilu to ba fẹ ṣiṣẹ ọlọpaa agbegbe, nilo lati gba owo oṣu, bi bẹẹ kọ, wọn ko ni ṣiṣẹ naa tọkantọkan. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Onimọ nipa ọrọ eto aabo tun sọ pe, kii ṣe ojuṣe ọga ọlọpaa lati ṣe eto gbigba ọlọpaa agbegbe. O ni awọn awọn alaṣẹ ipinlẹ kọọkan lo yẹ ki wọn wa awọn eeyan lawujọ lati ṣiṣẹ ọlọpaa agbegbe, nitori awọn lo mọ awọn eeyan wọn. Ọga agba ọlọpaa Mohammed Adamu lo paṣẹ fawọn ọga ọlọpaa ipinlẹ kọọkan lati forikori pẹlu awọn ọba alaye atawọn olori awujọ k'eto naa kẹsẹjari. Ṣugbọn Ọgbẹnu Amuwa ni ọga agba ọlọpaa ko ni ohun kan ṣe pẹlu ọlọpaa agbegbe nitori ko si lọwọ ijọba apapọ. O fi Gomina ipinlẹ Imo tẹlẹ, Rochas Okorocha ṣe apejuwe ijọba ipinlẹ to ti ṣe agbekalẹ ọlọpaa agbegbe ri. Ọgbẹni Amuwa ni Rochas forikori pẹlu awọn ọba alaye atawọn olori awujọ lati gba awọn eeyan ṣiṣẹ, bakan ni ijọba rẹ si n fun wọn lowo. Cancer Survivor: Àìsàn jẹjẹrẹ ọyàn ṣe wò, ta bá tètè ṣe àkíyèsí rẹ̀, ká sì lọ sílé ìwòsàn O ni ijọba apapọ ati ọga agba ọlọpaa ni Naijiria ko mọ itumọ ọlọpaa agbegbe. Onimọ nipa ọrọ eto aabo, Ọgbẹni Amuwa ni ko lee si eto aabo to mọyan lori ti ijọba ba kọ lati sanwo fawọn ti wọn fẹ gba gẹgẹ ọlọpaa agbegbe.",0,yoruba @user. Iru e ko le sai ma waye nigba ti o je wipe idije oloresore ni won gba,0,yoruba "Ẹ Kú ọjọ́ ìbí o @user. Ẹ ó gbòó. Ẹ ó tọ̀ ọ́. Ẹ ó f'ọwọ́ páwú, ferìgì jobì. Ẹ ò ní ráburú lọ́dún tuntun. Ire gbo gbo doríi yín. Àṣẹ",0,yoruba "Nínú Àkúrẹ́ ni wọ́n ti pa olóyè náà, tí ó tún mú kí ọ̀rọ̀ tó wà nílẹ̀, tún bọ̀ dàrú si. Fún ọdún mẹ́ta, rògbòdìyàn ń lọ, tí ó mú kí wọ́n pàdánù ọ̀pọ̀ ẹ̀mí àti dúkìá, èyí tí ó mú kí Benin rán àwọn ọmọ ogun lọ sí Àkúrẹ́ ní 1818. Ogun 1818 jẹ́ ogun tí kò pẹ̀ẹ́",0,yoruba olùparapọ̀ ri pe dara gan wey ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba Yoruba artists: Ṣé Yomi Fabiyi ti rí ìfẹ́ míràn ni lẹ́yìn tó kọ ìyàwó rẹ̀ òyìnbó tẹ́lẹ̀ sílẹ̀?,0,yoruba jẹ́ pàtàkì wey ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó wáyé..,0,yoruba "Aabo to peye yẹ ko wa fawọn olutoju alaisan lọwọ ajakalẹ arun. O fikun pe yoo daa kawọn naa si dẹkun lilọ gba itọju loke okun, ki wọ̀n baa le raye gbọ bukata to yẹ lori awọn ile iwosan to wa nilẹ yi, paapa lasiko ti ajakalẹ arun ba bẹ silẹ, kawọn olutọju alaisan aa ba lugbadi arun naa. Aabo to peye gbọdọ wa fawọn olutọju alaisan Lasiko to n sedaro awọn dokita mẹrin to ku nigbati wọn n setọju awọn alarun iba ọrẹrẹ, nipinlẹ Ebonyi ati Kogi ni o se ni laanu pe ọpọ igba lawọn olutọju alaisan maa n se agbako iku ojiji lẹnu isẹ wọn, paapa lasiko ti ajakalẹ arun ba bẹ silẹ, eyi to ni ko yẹ ko ri bẹẹ, nitori irufẹ isẹlẹ yi kii saba waye lawọn orilẹede to ti goke agba. Ijọba gbọdọ setọju awọn ile iwosan wa gbogbo ""Gbogbo ẹbi isẹlẹ yi kii se tawọn olutọju alaisan to ko arun abaadi yi, tabi pe wọn ko mọ isẹ wọn nisẹ ni. Amọ ọpọ ẹbi yi lo wa lọwọ awọn ijọba ni ẹlẹkajẹka nitori bi wọn kii se bikita nipa aabo awọn olutọju alaisan, ti eroja isẹ to peye lati daabo bo wa, ko si si lọpọ ilewosan lorilẹede yi."" Awọn olutọju alaisan gbọdọ daabo bo ara wọn Bẹẹ ba gbagbe, dokita onisegunoyinbo mẹrin lo padanu ẹmi wọn ninu osu kinni ọdun 2018 nipinlẹ Ebonyi ati Kogi lasiko ti wọn n setọju awọn eeyan to ni arun iba ọrẹrẹ, taa mọ si Lassa Fever.",0,yoruba "Agbabọọlu mejilelogun lo ti gunlẹ si ibudo igbaradi naa Awọn adari ikọ super eagles pẹlu awọn agbabọọlu mẹfa ni wọn side ibudo naa ni ọjọ aje sugbọn gbogbo nkan burẹkẹ sii nigba ti awọn agbabọọlu bii Victor Moses, Kelechi Iheanacho, Ahmed Musa, Wilfred Ndidi balẹ si ibudo naa ni ọjọ isẹgun. Igbaradi ẹẹmeji ọtọọtọ ni awọn agbabọọlu Super eagles yoo se lọjọọru Lọjọọru ni ireti wa wi pe Ikechukwu Ezenwa ati Daniel Akpeyi yoo darapọ. Igba meji ọtọọtọ ni awọn agbabọọlu Super eagles to ti gunlẹ si orilẹede Poland se igbadi ni ọjọ isẹgun Igba meji ọtọọtọ ni awọn agbabọọlu Super eagles to ti gunlẹ si orilẹede Poland se igbadi ni ọjọ isẹgun; eleyi ti wọn yoo tun se pẹlu ni ọjọọru. Ikọ agbabọọlu Super eagles yoo maa koju Poland gẹgẹbii ara igbaradi fun idije ife ẹyẹ agbaye ti yoo waye losu kẹfa ọdun 2018 lorilẹede Russia. Bakannaa ni Super eagles yoo koju Serbia ni ilu London ni ọjọ isẹgun, ọjọ kẹtadinlọgbọn osu kẹta.",0,yoruba RT @user: @user Eni to ba ni oyun,0,yoruba pe ṣe iyalẹnu wey ti o ní wúlò fún gbogbo.,0,yoruba "eḳọ nípa ire àti ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìṣẹ́ ọ̀pọ́lọ̀.",0,yoruba ọmọ ri pe lẹ ìkòkò wey ti o ní wúlò.,0,yoruba "lọ, Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde sí ara ilẹ̀.",0,yoruba "Ajọ to n risi eto idibo lorilẹede Naijiria (INEC) ti fi da awọn ọmọ orilẹede Naijiria loju pe esi idibo lọdun 2023 ni wọn yoo fi ayelujara ṣe agbatẹru rẹ. INEC ni awọn o tiyin ipinu awọn pada ati pe awọn ti fi opin si fifi ọwọ kọ esi idibo. Kọmiṣọna ajọ eleto idibo INEC, Festus Okoye lo ṣalaye ọrọ naa nigba to o fesi ọrọ kan to jakiri pe ajọ INEC ti pada si n fi ọwọ kọ esi idibo lọjọ aiku,. Okoye ni bi eto idibo ṣe waye ni eto idibo gomina ni ipinlẹ Osun ati Ondo nani yoo tẹsiwaju lọdun 2023 Iroyin nani ko dun mọ ọpọlọpọ ọmọ orilẹede Naijiria ninu, ti wọn si tun bọ sita lati pe akiyesi ajọ INEC si iroyin naa. Ọkan lara awọn to fẹhonuhan loril iroyin naa ni, oludije sipo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ oṣelu PDP, Atiku Abubaker, ẹni ti o fi ẹsun kan ajọ naa pe wọn gbero lati ṣe madaru eto idibo lọdun 2023. Atiku, ẹni ti o gba ẹnu agbẹnusọ rẹ sọrọ, Daniel Bwala ni ajọ naa ti apejuwe pe wọn ṣe madaru esi ibo lọdun 2023. Sugbọn Okoye ti wa fi ọkan onikaluku bale pe ajọ INEC ko ni erongba kankan lati fi ọwọ ko esi idibo lọdun 2023 tabi lọjọ iwaju O ni awọn eeyan kan lo si ajọ naa gbọ, ti wọn si iroyin naa sita fun ọmọ orilẹede Naijiria. “Ọrọ yii jina si otitọ.” “A fi da awọn ọmọ orilẹede Naijiria loju pe fifi esi idibo si ori ayelujara ti di ohun kan ti yoo wa titi ayeraye. “Koda fifi esi idibo si ori ayelujara mu isẹ ma rọrun, ti o si fi oto eto idibo han awọn ọmọ orilẹede Naijiria, ti wọn si le tẹle bi eto idibo ṣe n waye nibikibi.”",0,yoruba àmọ́ ìjẹ̀ṣà ń gún ògbólógbòó iyan o àti ìṣápá olódùmarè,0,yoruba gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ài: ti o ní wúlò.,0,yoruba Lórí Yes Media Academy Radio. E máa gbọ oooo #iroyinbeeni #yoruba #yesofGod #yesmaradio @user @user @user.ng @user @user YES Media Academy Radio https://t.co/g2LteIkE1C,0,yoruba "Idije Premier League Lẹyin ti Barcelona yọ wọn kuro ni idije UEFA Champions League, Everton fikun ijiya wọn pẹlu ami ayo mẹrin sodo. Idije Premier League Ẹlẹsẹ ayo Richarlison lo kọkọ gba bọọlu sawọn Man U lẹyin iṣẹju mẹtala ti ere bọọlu ọhun bẹrẹ. Helen Paul sọ idi tó fi gba orúkọ ní kékere Aaringbungbun Gylfi Sigurdsson lo fọba lee fun Everton lẹyin to gba goolu keji wọ le lati ọna jinjin ti aṣole fun Man U, David De Gea si wo goolu naa wọ le. Nibayii Manchester United ti wa ni ipo kẹfa bayii ninu idije Premier League, Arsenal wa ni ipo kẹrin nigba ti Chelsea tẹ le wọn ni ipo karun un. Everton to gbẹyẹ lọwọ Man U ti bọ si ipo keje bayii lẹyin ti wọn gbo ewuro soju Manchester United.",0,yoruba ilera ṣẹlẹ ni Lagos ti gbogbo eniyan sọ o ṣe pataki. (2004),0,yoruba yi yi ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Bàbá lo ìgbà ọkọ.,0,yoruba gbé fi yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba agba ri pe ṣe iyalẹnu wey ti o pẹ jú nìlọ̀ ni ọ̀nà tí ẹ̀ọ́ kan máa ń gbé ìyẹ̀ alẹ́.,0,yoruba "Alaafin ilu Oyo fi Wasiu Ayinde jẹ Mayegun ilẹ Yoruba lọjọ kẹtala, oṣu Kinni, ọdun 2020. Ọdọ oloogbe Sikiru Ayinde Barrister ni Wasiu Ayinde ti bẹrẹ isẹ gẹgẹ bi ẹni to maa n ba ẹgbẹ akọrin rẹ ko irinṣẹ. O ṣiṣẹ pẹlu ẹgbẹ akọrin Barrister, Supreme Fuji Commander, laarin ọdun 1975 si 1978. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Irinajo kan ti Barrister lọ si England lọdun 1974, ti gbogbo awọn ọmọ ẹgbẹ si duro de e la i ri nkankan ṣe, lo ru Wasiu Ayinde soke lati bẹrẹ ẹgbẹ akọrin rẹ. Awo orin rẹ akọkọ to gbe jade, Iba, lọdun 1980, ko ta daada. Ọdun 1984 to gbe awo orin miran to pe ni Talazo'84, ni ogo rẹ fi bẹrẹ si n tan kalẹ. Wasiu Ayinde: Èmi àti Aláàfin sọ fún Gani Adams nípa oyè Mayegun, a kò jà rárá Wasiu Ayinde ko pari ileewe girama ti ko fi lọ sileewe mọ nitori iku baba rẹ. Ṣugbọn igbesẹ to gbe lati gba ileeṣẹ alamojuto onkọrin to fi ilu London ṣebugbe, Dayo Adekunle Olomu, D.O & Associates gẹgẹ bi manija rẹ, ṣeranwọ fun lati sọ orin rẹ di itẹwọgba laarin awọn ọlaju ati awọn miran ni agbo faaji Naijiria. Awọn inagijẹ ti o wọpọ pẹlu Wasiu Ayinde ni: Igi Jegede Oba Orin Kwam1, K1 de Ultimate Ipa ti Wasiu Ayinde ko ni agbo amuludun ni Naijiria ti mu ko jẹ oye loriṣiriṣi nilẹ Yoruba, to si tun gba ami ẹyẹ kaakiri agbaye. Lara awọn oye naa ni Badabarawu ilu Ogijo - 1985 Ekerin Amuludun ilẹ Ibadan - 1986 Golden Mercury of Africa Title - 1986 Oluomo ti ilu Eko - 1999 Oluaye Fuji Music ni NTA Ibadan - 1993. Oluomo ilu Eko latọwọ Oba Adeyinka Oyekan ti Eko lọdun 1999 Ọjọ Aje, ọjọ kẹtala, oṣu Kinni, ọdun 2020, ni Alaafin ilu Oyo, Oba Lamidi Adeyemi kẹta fi Wasiu Ayinde jẹ oye Mayegun akọkọ nilẹ Yoruba. Ọdun mọkanla sẹyin ni Wasiu Ayinde ti n dafun tolo si oye Mayegun ilẹ Yoruba, ki Alaafin to o jawe oye le lori l'ọdun 2020. Awọn ami ẹyẹ bi i Honoris Causa of Music at Saint John University Bakerfield California USA in 1989. FAME Musician of the Year, Best Fuji Artiste at the Nigerian Music Awards Best African Artiste at the WOMAD Festival in Reading 1996 The Headies - Hall of Fame 2013 City People Lifetime Achievement Award - 2014 Wasiu Ayinde ti gbe ọpọlọpọ awo orin jade, bẹ ẹ si ni awọn eyi to kọ ni ode ere, sugbọn to gbe jade sori fọnran. Lara wọn ni:",0,yoruba ekúnasùnsínú ni fiimu ti gbogbo idile le wo ton ko ni leko to tun tonisona,0,yoruba """Ọbasanjọ ti foriji PDP ni ibamu pẹlu ohun ti Bibeli sọ.'' Oluranlọwọ fun Ọbasanjọ, Kehinde Akinyẹmi lo fi ikede naa sita fun awọn akọroyin. O ni alaga apapọ fun ẹgbẹ oselu PDP, Uche Secondus lo ko igbimọ ẹlẹni mọkanlelogun sodi, lati se abẹwo ikinni si ọdọ Ọbasanjọ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Lara ohun ti Secondus tun gbekalẹ nibi ipade naa ni ti iwe adehun ti awọn ẹgbẹ kan fọwọ si, lati da ẹgbẹ oṣelu Coalition of United Political Party, CUPP, silẹ. Alaga apapọ fun ẹgbẹ oselu PDP, Uche Secondus lo ko igbimọ ẹlẹni mọkanlelogun sodi, lati se abẹwo ikinni si ọdọ Ọbasanjọ. Ẹwẹ, o ni alaga PDP ọhun tun rawọ ẹbẹ si Ọbasanjọ lati tẹsiwaju ninu wiwa ojuutu si awọn iṣoro to n dojukọ eto ọrọ aje orileede Naijiria. Akinyẹmi ni, lootọ ni Ọbasanjọ ti foriji wọn ni ibamu pẹlu ohun ti Bibeli sọ, sugbọn ẹgbẹ alajumọṣe African Democratic Congress, ADC, ṣi ni yoo gbe e leke. Imọran ati itọni Ọbasanjọ se koko lori imurasilẹ PDP fun idibo 2019. Secondus, to ba awọn akọroyin sọrọ lẹyin ipade naa fidi rẹ mul pe 'lootọ lawọn oloye ẹgbẹ PDP lọ si Abẹokuta lati ni ijiroro pẹlu ọbasanjọ lori eto idibo ọdun 2019. O ni ṣiṣe ipade pẹlu ọbasanjọ se koko fun awọn lati gba imọran ati itọni lori imurasilẹ PDP fun idibo 2019.",0,yoruba "Idi ree ti ẹgbẹ Miyetti Allah to jẹ awọn olusin maalu lorilẹede Naijiria, ti wọn jẹ ẹya Fulani, naa fi n kede faraye pe awọn ko ni gbẹyin nibi ipade ita gbangba lori agbekalẹ ẹsẹ alaabo Amotekun ti yoo waye lọjọ Aje. Miyetti Allah ni awọn fẹ lọ sibi ipade ita gbangba ọhun lati fi ero awọn han lori ifilọlẹ ikọ alaabo ọhun lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria. Alaga ẹgbẹ Miyetti Allah nipinlẹ Ogun, Abdulmumin Ibrahim sọ fawọn akọroyin pe ko yẹ ko jẹ ẹya Yoruba nikan ni yoo wa ninu ẹsẹ alaabo Amotẹkun niwọn igba ti yoo dojukọ aawọ to maa n waye laarin awọn agbẹ ati darandaran. Ibrahim ni awọn ko fẹ ki wọn sọ ẹsọ alaabo Amotekun di ẹgbẹ ọmọbibi ilẹ Oodua, OPC, o si yẹ ki wọn gba awọn ọmọ ẹgbẹ Miyetti Allah sinu ikọ Amọtẹkun naa, ko lee fidi mulẹ bo se yẹ. Ko tan sibẹ, akẹẹgbẹ rẹ lati ipinlẹ Ondo, Alhaji Garuba Bello naa ni awọn ọmọ ẹgbẹ Miyetti Allah yoo bawọn peju sibi ipade gbangba lori Amotekun lọjọ Aje, to si fikun pe oun tijọba ba ni ki awọn se, lawọn yoo se. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Bẹẹ ba si gbagbe, ẹgbẹ Miyetti Allah yi lo ti n tako agbekalẹ eto alaabo Amotekun latẹyinwa, ti wọn si ni afojusun eto naa ni lati le ẹya Fulani jinna rere si ẹkun iwọ oorun guusu Naijiria. Fire Eater: Azonto ní àfojúṣùn òun ni láti lọ fi idán iná yìí pa owó lókè òkun Amọ awọn gomina to wa nilẹ Yoruba ti wa sọ fawọn Fulani pe ibẹru wọn yii ko lẹsẹ nilẹ, ko si tọ, bẹẹ ni ko pọn dandan.",0,yoruba "Òkúta, igi tàbí nǹkan míì ni a fi ń pààlè iye t'ọ́jà jẹ́ s'órí ọ́jà. Ta ló jẹ́ pààlè s'órí ọjà lóde ònìí tí ọ̀ṣà ò ní gbé e lọ́jà lọ. #Asa",0,yoruba "ìwé ẹ̀kó. Nitori eyi, ara eni lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..",0,yoruba "Lai lai, ko si ẹni to lee ni imọlara iru irora ti o la kọja bi ọga rẹ ṣe n ti ẹsẹ rẹ bọ inu iho ina to n jo hii hii. Ọpọ awọn ara ipinlẹ Gombe ni ọrọ yii ṣi n ya lẹnu idi ti oludari ileeṣẹ burẹdi naa, Idris Abubakar yoo kan ṣe dede jo ẹsẹ ọmọ ọdun mẹwa nina ninu ina aro ti wọn fi n ṣe burẹdi. Ẹgbẹ kan to n ja fun ẹtọ araalu Muryar Talaka sọ fun BBC pe ọwọ ti tẹ afurasi naa ṣugbọn ti wọn tun pada da a silẹ nigba ti oku ọmọ naa si wa nile rẹ. Ahmed Sulaiman to jẹ adari ẹgbẹ Muryar Talaka sọ fun BBC pe oun bẹ ọmọkunrin naa wo ti olukọ ile keu si ti n tọju ara rẹ. Ni agbegbe Bajoga ni ijọba ibilẹ Funakaye, ipinlẹ Gombe ni Usman wa lati wa kọ ẹkọ keu lati odidi Tafawa Balewa, ipinlẹ Bauchi. Ahmed ni ""oun to ṣẹlẹ ni pe ọludari ile iṣẹ burẹdi naa fi ẹsun kan ọmọkunrin ọhun pe o ji burẹdi lo ba ti i sinu iho ina ti wọn fi n yan burẹdi. Iroyin ti a gbọ ni wi pe ọga ileeṣẹ burẹdi yii ko ẹsẹ Nafiu sinu ina aro ti wọn da si abẹ burẹdi, nigba to yọ ọ jade to ri i pe ko jo o daadaa o tun ju u sinu ina lẹẹkan sii. Hepatitis: A kò leè kóo nípa dídìmọ́ ara ẹni Ko pẹ rẹ ni ọlọpaa tu ọga ileeṣẹ burẹdi naa silẹ ṣugbọn ọmọ ti wọn jo ẹsẹ rẹ nina ṣi wa ninu irora kikan. Nigba to kuro ni atimọle ọlọpaa, o lọ bẹ ọmọ naa wo nile ṣugbọn ọga ile keu kan ti tọju ara ọmọ naa. Ṣugbọn adari ẹgbẹ Muryar Talaka, sọ pe afurasi ọhun kuro ni atimọle lẹyin ti eekan kan ninu ilu lọ gba beeli rẹ. Bakan naa o ni lọgan ni wọn ti ṣe iwe ẹri sita pe arun ọpọlọ n da Idris ọga ileeṣẹ burẹdi ọhun laamu. ẹwẹ, nigba ti ileeṣẹ BBC kan si alukoro ọlọpaaa agbegbe naa o fesi pe oun ko tii gbọ nipa iṣẹlẹ yii ṣugbọn oun yoo kan si BBC pada lori bo ṣe jẹ bi wọn ba ti gbọ iroyin kankan.",0,yoruba Lọjọ Aiku ni aarẹ awọn oṣere tiata Yoruba Naijiria Bolaji Amusan Mr Latin fidi ọrọ naa mulẹ fun ileeṣẹ BBC Yoruba. O ti to ọjọ mẹta ti aisan ti n ba Pa Kasunmu finra. ''Eeyan daada ni wọn yatọ si pe wọn jẹ oṣere tiata.Iku wọn jẹ eleyi to fi ọwọ kan wa lẹmi'' Yatọ si Mr Latin awọn oṣere miran bi Foluke Daramola ti fi ikede iku Pa Kasumu i oju opo wọn ni Instagram pẹlu ọrọ ikẹdun iku rẹ. Ọjọ kẹrindinlogun oṣu Kẹta ọdun 1953 ni wọn bi Kayode Odumosu ni ilu Ibadan. Ọmọ Odogbolu ni ipinlẹ Ogun ni a gbọ pe Baba rẹ jẹ ti iya rẹ si jẹ ọmọ Abeokuta. O ti kopa ninu ọpọ ere sinima ti awọn eeyan si mọ gẹgẹ bi ogbontarigi ninu awọn adẹrinposonu ere tiata lede Yoruba ati Gẹẹsi.,0,yoruba "Ìle-Ìfẹ̀. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "YORÙBÁ SAYING / Ọ̀RỌ̀ YORÙBÁ Bí adìyẹ bá kú, a ò ní da ẹyin rẹ̀ nù... If a hen dies, we won't throw away its laid eggs ÌTUMỌ̀: bí èèyàn bá kú, a kò gbọdọ̀ ta ọmọ tó fi sílẹ̀ sáyé nù. MEANING: The child(ren) left behind by a deceased person shouldn't be neglected",0,yoruba "àkokò, Bàbá lo ni ìgbà mi owó àkokò, Ọmọ lo ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "òkè: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Bàbá lo ni ìgbà mi owó àkokò, Ìyá ri Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "RT @user: Where is the cake please. Use Àkàrà, Àkàrà is àkàrà, don't spoil the language please. https://t.co/63YPCta6PA",0,yoruba "Awọn ọna Meji - Apá 6 """"""""""""""""... Ẹniti o ba gba a gbọ ko ni da lẹbi; ṣugbọn ẹniti ko ba gba a gbọ lẹbi tẹlẹ, nitori ko gbagbọ ni orukọ Ọmọ bíbi kanṣoṣo ti Ọlọrun."""""""""""""""" Johannu 3: 16-18 #Ọlọrun #Jesu #EmiMimo #Bibeli #niife #Igbala #amojukuro #yoruba #Ioruba",0,yoruba ìyá abiamọ abọ̀já gbọ̀ọ̀rọ̀gbọrọ,0,yoruba ọsẹ àsa. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọmọ lo ìgbà ọkọ.,0,yoruba Ìbàdandun ni ó ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní.,0,yoruba "@user àlááfíà ni o, ṣé dáadáa ni ìyá wa? A ti ṣe bẹ́ẹ ti wí, ó pẹ́ díẹ̀. Ọjọ́ ti pẹ́. :)",0,yoruba ...tí mo bá tún ayé wa gan-an òun ni màá ṣe. #Ogboni #Yoruba,0,yoruba ọmọ ekiti àti bẹ́ẹ̀bẹ́ẹ̀ lọ ni a mọ ara wa sí,0,yoruba "Bí ìgbà-á bá ń gbáni, ká máa rọ́jú, nítorí ìgbà sì ń padà bọ̀, tí ìgbà yóò tún gbani sílẹ̀ lọ́wọ́ ìyà. #EsinOro🐎 #Yoruba #COVID19",0,yoruba "RT @user: A kí gbogbo ẹ̀yin olólùfẹ́ Àbáláyé Nigeria kú àyájọ́ ọdún olólùfẹ́. Àṣèyí ṣàmọ́dún o. We gret all our lovers, Happy Val…",0,yoruba Ọkan tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba "fi. Nitori eyi, ara eni lo ni àṣà yorubá eyti o gbe lori àìmọ́ kọ.",0,yoruba Ọ̀fíìsì Abánirojọ̀ Ìjọba Àpapọ̀ jẹ́rìí sí i èyí : 63 nínúu iṣẹ́ àtúnṣe 97 ìwé àdéhùn ìfìmọ̀ṣọ̀kan ti di àpatì .,0,yoruba Ìlẹ̀ Ọ̀yọ́ jẹ́ ìlú tí ó tó gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ àti ìbi tí wọn wà.,0,yoruba "Ìkìlọ̀: Ó jọ wí pé àṣẹ náà máa wúlò. Níwọ̀n ìgbà tí ápúlẹ́ẹ̀tì yìí kò wúlò, o lè má fẹ́ ṣe èyí. A gbà ẹ́ nímọ̀ràn gidi kí o má lo %s fún ohunkóhun tí yóò mú ápúlẹ́ẹ̀tì náà ""jẹ́ ṣíṣe"" tàbí wúlò.",0,yoruba "lọ, Nitori eyi, ara eni lo ni àṣà yorubá eyti o gbe lori àìmọ́ kọ.",0,yoruba olúwo ẹ dákun bóo ni ẹ ṣe lè ṣàlàyé bí ẹja akaragba ṣe rí tàbí orúkọ rẹ̀ mìíràn n óò máa retí èsì ire o,0,yoruba ẹ̀yin aláboyún ẹ ó rù ú ire ẹ ó sì sọ̀ ọ́ lẹ́sọ̀ wéré lewé ń bọ́ lára igi à á gbóhùn ìyá gbóhùn ọmọ,0,yoruba "Nínú oṣù Ọ̀wàrà 2019 , ilé ẹjọ́ gíga Tanzania ṣe ìdímú ṣinṣin ìdájọ́ ọdún - un 2016 tí ó pàṣẹ ó kéré jù , ọmọbìnrin àti ọmọkùnrin gbọdọ̀ pé ọmọ ọdún méjìdínlógún kí ó tó ṣe ìgbéyàwó .",0,yoruba "Lásìkò tí wọ́n péjọ láti ṣinu ààwẹ̀ ní òun àti àwọn onígbàgbọ́ míírà sàbẹ̀wò sí mọ́sálásí náà. Ilé iṣẹ́ ìròyìn Channels gbé àwọn fótò bí Bísọ̀ọ̀bù àgbà ọ̀ún ṣe ń pín ounjẹ náà fún àwọn mùsùlùmí láti ṣínu. Gẹ́gẹ́ bí ó ṣe sọ lásìkò tó n pín, ó ṣàlàyé pé Ọlọ́rùn fẹ́ràn kí krìstẹ́nì fi ìfẹ́ hán nítòrí ìfẹ́ ni òun fúnra rẹ̀, àti pé àwọn ń ṣe èyí láti jẹ́ kí àláfíà kó jọba láàárín krìsẹ́ní àti Musulumi. Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, Imaamu Mọ́sálásí Al- Habibyyah Fuad Adeyemi sọ pé, ǹkan tí adarí krìtẹ́nì ṣe yìí fi hàn pé ẹ̀sìn méjèèjì lé jọ́ jùmọ̀ gbé pọ̀ gẹ́gẹ́ bí ọ̀rẹ́ àti ni ìgbé àlàfíà.",0,yoruba "àìlẹ̀, Olùwo ri A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..",0,yoruba kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba Dejo Tunfulu: Yomi Fabiyi ní olóògbé kò dúró gba owó iṣẹ́ tí wọ́n jọ ṣe kẹ́yìn nítorí àisàn rẹ̀,0,yoruba àti iyin ekiti o àti ado ekiti o ti olúwa nilẹ̀,0,yoruba "Ìdánwò oògùn àrùn yírùnyírùn ìgbàa nnì ní Kano , orílẹ̀ - èdèe Nàìjíríà , gbin ọ̀pọ̀lọpọ̀ àìnígbágbọ̀ tí kò mú kí ìpolongo ìdánwò oògùn àrùn rọmọlápárọmọlẹ́sẹ̀ ó rinlẹ̀ .",0,yoruba Ìbàdandun ni ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn. (Item 127),0,yoruba ègé olóótọ fún àwọn ìṣẹ́ tí ó ga.,0,yoruba "iṣẹ́: ti o nuni ti o nuni ti o nuni ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Nitori eyi, ara eni lo ni ẹ̀ká àwẹ eyti o gbe lori iwa rere.",0,yoruba Àkójú ọ̀rọ̀ yi kún fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde sí ara ilẹ̀. (Item 96),0,yoruba "Nígbà tí Ọmọ fè mú, A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà.. Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba áwọn iṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba pa Ọmọ lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba "Singer Barry Jhay: Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa olórin tàkasúfé, Barry Jhay",0,yoruba a ó rẹ̀ ìwọ gíga ènìà sílẹ̀ a ó sì tẹ̀ orí ìgbéraga ènìà ba olúwa nìkan ṣoṣo li a ó gbé ga lí ọjọ́ náà,0,yoruba ìbòjú dúdú àti omi tí mo fi ńwòó rè é lóòótọ́ ló yọ àmọ́ kò pọ̀ ni ẹ ṣeun,0,yoruba ri Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "Atọ́kùn ètò ọ̀hún , olóṣèlú Diosdado Cabello , rò kàn pé Díaz lọ́wọ́ sí ìfẹ̀hónú hàn àìsí ináa mọ̀nàmọ̀nà tí ò lọ jákèjádò orílẹ̀ èdè èyí tí ó mú kí àwọn ọmọ Venezuela máa gbé nínú òkùnkùn fún ó lé ní wákàtí mẹ́rin lé lógún lọ́jọ́ 7 àti 8 Oṣù Ẹrẹ́nà",0,yoruba "Nígbà àkerekere, Baàlè ri Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba Yorùbá àwọn èrò àti àsà tí ó ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba iṣẹ́ ṣẹlẹ ni Eko ti gbogbo eniyan sọ o ṣe pataki. (1991),0,yoruba ojú kakaaki. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba kí ni ìyàtọ̀ tó wà láàárín igún àti àkàlà what are the differences between the buzzard and the vulture,0,yoruba "Thomas Dennerby yoo dari ikọ ọmọ ẹgbẹ Super Falcons di ọdun 2020 Olori Ile Isẹ igbimọ alakoso fun ere bọọlu orilẹede Naijiria, (NFF), Amaju Pinnick ti o fi ọrọ yi si ori opo ayelujare Twitta rẹ loni sọ wi pe adehun naa fun Dennerby lati dari awọn ọmọ ẹgbẹ agbabọọlu obinrin ti orile-ede Naijiria, Super Falcons fun ọdun meji. Ọgbẹni Pinnick sọ pe Dennerby yoo dari ikọ ọmọ ẹgbẹ Super Falcons di ọdun 2020 pẹlu asọtẹlẹ lori boya yoo gbawe isẹ tan tabi ki o tẹsiwaju gẹgẹbi akọni-mọọgba. Ẹgbẹ Super Falcons ti wa laini olukọni fun bii ọdun kan Dennerby, ti o lo ọdun mẹsan pẹlu Hammarby IF ti Allsvesnkan ti o dẹ gba bọọlu ninu idije fun Ife ẹyẹ ilẹ Yuroopu ni ọdun 1983 ati 1985. O ṣe akoso Ile-iṣẹ awọn agbabọọlu ọmọbinrin Sweden laarin ọdun 2005 ati 2012. O tun ṣe alakoso ọdọ-ọdọ fun Dubai FA ti o dẹ tun sisẹ ni awọn orisirisi ipo fun ọmọ ẹgbẹ Hammarby laarin 1993 ati 2001.",0,yoruba "Iro ibọn naa lo mu kawọn eeyan sí ni sọ nipa ogun Modakeke ati Ife mii eyi to mu ki ibẹrubojo gbalẹ. Amọ, agbẹnusọ fun ẹgbẹ Modakeke Progressive Union, Ven. Debo Babalola ṣalaye pe awọn adigunjale to yabo adugbo kan ni Modakeke lo dabọn bolẹ. Ninu ọrọ tiẹ, akọwe ẹgbẹ Ife Development Board, Lawrence Omidiora ni alaafia lawọn eeyan Ife wa. O rọ awọn eeyan pe ki wọn ye da ibẹrubojo bolẹ pẹlu iroyin ofege. Ṣugbọn iwadi fihan pe nkan o fara tẹlẹ laarin ilu mejeeji lẹnu ọjọ mẹta yii lẹyin tawọn yinbọn pa oniṣowo koko kan, Titilayo Gbadegesin ati ọmọkunrin rẹ, Reuben labule Alapata. Ẹwẹ, ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Osun ti ṣalaye ohun to ṣẹlẹ niluu Modakeke ati Ife nipinlẹ Osun lẹyin ti ọrọ naa gba ori ayelujara kan pe ija tun ti bẹ silẹ laarin ilu mejeeji. Fidio kan lawọn eeyan n pin kaakiri ori ayelujara lọjọ Aiku to n ṣafihan pe rogbodiyan tun ti bẹ silẹ. Ṣugbọn agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa, SP Opalola Yemisi Olawoyin, sọ pe irọ nla ni iroyin to lu ayelujara pa pe awọn kan wa da rogbodiyan silẹ lati ẹkun Famia. ""Iroyin ofege lasan ni, irọ nla pẹlu. Awọn ọlọdẹ fijilante lo n dan agbara wo nigbati ti wọn n le awọn ole. Awọn fijilante naa ṣe bẹẹ lati fi dawọn eeyan loju pe kò sí iyọnu fun wọn rara,"" SP Olawoyin lo sọ bẹẹ. Wọ́n rò pé mo ya wèrè ni Saudi lẹ́yìn ikú ọkọ mi Kọmiṣọnna ọlọpaa ipinlẹ Ọsun, Olawale Olokode fi dá àwọn eeyan ilu mejeeji loju pe ileeṣẹ ọlọpaa ko fi ọwọ yẹpẹrẹ mu ọrọ eto abo wọn. Bakan naa lo tun rọ awọn eeyan ilu naa lati fi to ọlọpaa leti ti wọn ba ti furasi ẹnikẹni ti o n ṣe nnkan ifura. Iganmu shanty demolition: Oníṣẹ́ ibi pọ̀ tó ń ṣọṣẹ́ lábẹ́ afárá Iganmu yìí ti pẹ́ ṣùgbọ́n.",0,yoruba "RT @user: Amin o, ire loju ojo nri o. Ayun lo, ayun bo lowo n yun enu """"""""""""""""""""""""""""""""@user: Ojúmọ́ ire o.""""""""""""""""""""""""""""""""",0,yoruba alákòó. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba Àwàdà ńlá ni ! ! !,0,yoruba Orin Ẹ̀yẹ Ilẹ̀ Olómìnira Nàìjíríà Dìde ẹ̀yin ará Wá jẹ́ ìpè Nàìjíríà ká fi fì ìfẹ́ sin Ilẹ̀ wa Pẹ̀lú òkun àti ìgbàgbọ́ Kí iṣẹ́ àwọn akọni wa Kó má ṣe já sásán Ká sìn ín tọkàntọkàn Ilẹ̀ tó lómìnira àti àlàáfíà Sọ́ di eyọ̀kan #naija #yoruba #oroyoruba,0,yoruba "Àjíire, Àrìnàkore, Ire níwá ire lẹ́hìn. Ire lọ́tùn-ún ire lósì. Ire wá yí wa po bí ọ̀bìrìkìtì.",0,yoruba "Eyi gan lo faa ti ahesọ iroyin nipa aawọ laarin oun ati gomina ipinlẹ Ọyọ lori idasilẹ ọwọ ẹka ọlọpaa kogberegbe Police Mobile Squadron si ilu Agọ Arẹ fi jẹ eyi ti ọpọ ko lee fi oju fo da. Amọṣa Ọbalaye naa, iyẹn Kabiyesi Iku baba yeye, Ọba Adeyẹmi Alaafin ti ṣalaye ọrọ pe ko si ija laarin oun ati gomina Makinde lori iṣẹlẹ naa. Alaafin sọ ọrọ yii nigba ti gomina Makinde bẹẹ wo laafin Ọyọ lasiko irinajo rẹ si ilu Iṣẹmbaye naa lati ṣi awọn akanṣe iṣẹ ti wọn fi n sọri ọdun kan iṣejọba Makinde gẹgẹ bii gomina ipinlẹ Ọyọ. Alaafin Ọyọ ni imulẹ nla lo n bẹ laarin oun ati Gomina Seyi Makinde, nitori naa ko si ohun to lee fa ikunsinu laarin oun ati gomina naa. O fi kun un pe oun kuro lara awọn ọba ti yoo maa ba awọn to ba wa nipo iṣejọba ta kangbọn nitoripe oun ko si lati maa tabuku tabi fi ẹrẹ yi awọn to ba wa nipo aṣẹ lara. ""Ko si aawọ laarin emi ati gomina. Bi eeyan ba ni ọgbọn ti o si kawe, iru eeyan bẹẹ yoo ms bi a ti n ba awọn to ba wa nipo alaṣẹ ṣe pọ"" Iku Baba yeye, Ọba Lamidi Adeyẹmi kẹta ṣalaye lori ohun to ṣẹlẹ nipa ti ọrọ idasilẹ ọwọ ileeṣẹ ọlọpaa kogberegbe naa. O ni oun ko ni ikunsinu kankan si gomina Makinde lori bi o ṣe ni ki ọga ọlọpaa lorilẹede Naijiria o gbe ọwọ naa lọ si Agọ arẹ dipo ilu Ọyọ ti alaafin n ja fun. Saaju si ni Alaafin ti kọ orisirisi lẹta bii mẹta si ọga agba patapata fun Ileesẹ ọlọpaa nilẹ wa, to si n beere pe oun n fẹ ẹka ibudo ọlọpaa kogberegbe (MOP 73) nilu Oyo, eyi ti aarẹ Muhammad Buhari ti fi ontẹ lu. Esi lẹta fun agbekalẹ Ileesẹ ọlọpaa kogberegbe naa silu Oyo lo de ni ọjọ kẹtala osu kinni ọdun 2020 pe ijọba ti fọwọsi pe ki wọn gbe Ileesẹ ọlọpaa kogberegbe naa silu Oyo ati ilu mẹfa miran ni Naijiria. Alaafin si tun kọ lẹta miran ni ọjọ kẹrinla osu keji ọdun 2020 lati dupẹ lọwọ ijọba, ni pe o seun lori bibuwọlu agbekalẹ Ileesẹ ọlọpaa naa. Amọ lasiko ayẹyẹ ọdun kan rẹ lori aleefa ni Gomina Makinde lọ si Ileesẹ ọlọpaa kogberegbe naa nilu Agọ Arẹ to wa ni agbegbe Oke Ogun, eyi to bi awọn ọmọ Oyo, Alaafin ati Oyomesi ninu. Ki lo fa Ija lọbalọba ni ilu Iwo Nigba to fi atẹjade sita lori ọrọ yii, akọwe eto iroyin si gomina, Taiwo Adisa ni irọ gbuu ni pe ilu Oyo lo yẹ ki Ileesẹ ọlọpaa naa wa nitori Makinde lo kọ lẹta lati beere fun Ileesẹ ọlọpaa naa, ti ọga agba ọlọpaa si fi ontẹ lu u pe ko wa nilu Agọ Arẹ, ti wọn si lo Ileesẹ asesiga ìjọun lati bẹrẹ Ileesẹ ọlọpaa naa. Yoruba ni bi ẹlẹjọ ba ti mọ ẹjọ rẹ ni ẹbi kii pẹ lori ikunlẹ, idi ree ti gomina Seyi Makinde fi n rawọ ẹbẹ si Alaafin pe ko ma binu, ko fi ọwọ wọnu. Gomina Seyi Makinde rawọ ẹbẹ naa lasiko to lọ silu Oyo lati si ibudo ilera alabọde kan nilu Oyo, ti Alaafin tilu Oyo, ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi kẹta si gbalejo rẹ . Ninu ọrọ rẹ si ni Gomina Makinde ti rawọ ẹbẹ si Alaafin pe ko jẹ eburẹ lori bi oun ṣe gbe ibudo Ọlọpa kan lọ si agbegbe Oke Ogun dipo ko wa nilu Oyo gẹgẹ bi Alaafin ti n fẹ. Gomina Makinde sọ fun Alaafin pe ko ma binu nipa ọrọ naa, oun ko mọ rara pe ọba naa ti gbe igbesẹ saaju nípa kíkọ lẹta lori ọrọ yii. ""Kabiyesi, n ko mọ pe ẹ ti kọ lẹta kankan nitori lati oṣù kẹsan-an ọdun 2019 ni ọga agba olopaa ti pàṣẹ pe ki wọn gbe Ileesẹ ọlọpaa kogberegbe ọhun wa si agbegbe Oke Ogun lati pinwọ iwa ijinigbe atawọn iwa ọdaran miran.",0,yoruba ààrẹ buhari sọ̀rọ̀ nàá nígbà tó n sọrọ níbi ìpàdé commonwealth ní westminster lọjọru ọsẹ ṣé lóòótọ́ ní àwọn ọdọ́ nàìjíríà kò fẹ ǹkan ṣe,0,yoruba Ẹ gbìyànjú láti máa béèrè ọ̀nà kí ẹ má ba à ṣìnà #languagelearning #yoruba #iyil2019 #indigenouslanguages https://t.co/iUt0w2HVoL,0,yoruba "Àmọ́ lẹ́yìn àtẹ̀jáde kan sí ilé ìròyìn tí Àjọ tí ó ń ṣàkóso Omi orílẹ̀ èdè náà ( IMA ) tẹ̀ jáde ní ọjọ́ 22 , oṣù Ògún ọdún - un 2019 , èyí tí ó kìlọ̀ wípé – ìwádìíi National Oceanic and Atmospheric Administration ( NOAA ) Coral Reef Watch sọ wípé — iyùn abẹ́ òkúta òkun Tobago ti bọ́ sì abẹ́ ìṣọ́ láti ṣe òfíntótó “ Ìkéde Ìpàwọ̀dàa Ìpele Ìkíni """"""""",0,yoruba "Olakunle to jẹ onimọ nipa imọtoto ayika lo wọ aṣọ Spider man lati tun agbegbe rẹ ṣẹ. Arakunrin ọmọ Naijiria, Jonathan Olakunle to n wọ aṣọ bii ''Spider Man'' ninu fiimu ti ileeṣẹ Marvel gbe jade, ti sọ idi ti oun fi n ṣe bẹẹ lasiko to ba n gbalẹ ni igboro ilu Osogbo. Olakunle, lasiko to n ba BBC sọrọ ni awọn eniyan ko kọ ibi ara si imọtoto ni ayika lo jẹ ki oun dide lati maa ṣe imọtoto. Olakunle to jẹ onimọ nipa imọtoto ayika lo wọ aṣọ Spider man lati tun agbegbe rẹ ṣe. Gẹgẹ bi ọrọ Banki Agbaye, awọn idọti ti wọn kojọ ni awọn ilu nla nla le ni biliọnu meji tọọnu. Ninu ọrọ rẹ, Olakunle ni oun ko fẹran bi oun ṣe ma n ri idọti ni ayika oun, oun si korira ayika ti o doti. 'Ọjọ kan ni mo bẹrẹ si ni gba adugbo lẹyin ti mo kuro ni ile, mo bẹrẹ ninu ile, ki agbegbe mi le mọ toto'' Idi ti mo fi n wọ aṣọ Spiderman ni lati jẹ ki awọn eniyan kọ bi ara si mi nitori nigba ti mi o wọ aṣọ Spiderman, awọn eniyan ko tilẹ da mi loun, ti mo ba n gbalẹ. Igbakigba ti mo ba pe wọn, wọn ko ni dahun amọ nigba ti mo wọ aṣọ alaranbara yii ni wọn ma n dami lohun, ti wọn a si tun darapọ mọ mi.'' O ya mi lẹnu pe ti awọn ọmọ Naijiria ba rinrinajo lọ si oke okun, wọn ma n tẹle ofin ati ilana lori imọtoto amọ ni Naijiria, wọn kii kọbi ara si'' Ẹ jẹ ka mu imọtoto ni pataki lati sẹgun aisan - Olakunle Imọtoto lo bori arun gbogbo paapaa awọn aisan to wọpọ ni ilẹ adunlawọ bii aisan onigbameji, aisan iba apọnju, aisan iba Lassa ati bẹẹ bẹẹ lọ. Nitori naa ni Olakunle ṣe rọ gbogbo awọn ọmọ Naijiria, to fi mọ awọn ọdọ lati mu imọtoto ni ọkunkundun fun igbayegbadun awọn eniyan. Iwadii fihan pe, ọpọlọpọ idọti ti o wa ni awọn ilu nlanla ni wọn n parapọ si awọn agbegbe, eleyii ti yoo mu aisan wọpọ ni awọn agbegbe yii.",0,yoruba "Ọdún Ajinde yìí ni àwon ọmọlẹyìn Kristi jakejado àgbáyé máa n ṣe ìrántí ikú ati ajinde Jesu Kristi. Ni ibẹrẹ pẹpẹ ẹṣin Kristẹni, awọn onigbagbọ máa n ya ọjọ náà sọtọ gẹgẹ bíi ọjọ ibanujẹ, ọjọ ọfọ, ọjọ ironupiwada ati ọjọ awẹ. Ọjọ yii si ni wọn maa n pe ni ọjọ Ẹ́ti rere lode oni, koda, ọpọ Kristiẹni kii jẹ ohun abẹmi to jẹ ẹlẹjẹ ni iru ayajọ oni lati sami ati iya nla iku Jesu lori igi agbelebu. Fun ọdun 2021, oni yii, tíì ṣe ọjọ Keji, oṣù Kẹrin ni ọjọ Ẹti rere fun ọdun yii bọ si, ti wọn n pe ni Good Friday. Bó tilẹ jẹ pé ọjọ ọfọ ati ìbànújẹ ni ọjọ náà jẹ ninu itan ẹṣin onígbàgbọ, amọ ọjọ náà ló jẹ òpin ọsẹ to se pataki julọ ninu itan Kristẹni. Ọsẹ yii ni wọn maa n pe ni ọsẹ ikaanu fun ijiya ati iku Jesu Kristi. Ìgbàgbọ àwọn Kristẹni ni pé, ọjọ Ẹtì náà ni Jesu ku lórí igi agbelebu, to sí ko ẹsẹ gbogbo araye lọ, ko to di pe o ji dide pada ni ọjọ kẹta. Ṣugbọn ki lo de ti wọn fi n pé ọjọ náà ni Good Friday, ìyẹn ọjọ Ẹtì rere, dipo ọjọ ibanujẹ ti ọjọ náà jẹ? Àlùfáà Mike Schmitz ni lootọ lo jẹ ọjọ ibanujẹ, ṣugbọn ni ida keji ẹwẹ, ọjọ ayọ ni ọjọ náà nítorí pé ọjọ ọhun gan ni Jésù ko ẹsẹ arayé lọ lori igi agbelebu. O ni awọn onígbàgbọ́ máa n ri ọjọ náà bíi ọjọ ti Ọlọrun ko ẹsẹ arayé lọ, to si dari ẹsẹ jin gbogbo èèyàn labẹ ore ọfẹ Jesu. Àlùfáà náà parí ọrọ rẹ pé, agbelebu nìkan ni idahun sí gbogbo ìbéèrè awọn Kristẹni lórí gbogbo ìṣòro tí wọn bá gbé tọ Ọlọrun wa. Eredi ree ti ọjọ Good Friday yii se jẹ ọjọ ayọ fun onígbàgbọ bo tilẹ jẹ pé ọjọ burúkú ni ọjọ náà nínú ìtàn ẹṣin Kristẹni káàkiri àgbáyé. BBC Yoruba wa n ki awọn ọmọlẹyin Kristi lagbaye ku ọdun ọjọ Ẹti rere, ta si n gbadura pe a se pupọ rẹ nile aye.",0,yoruba "Bí wọ́n bá sì fi òwe yìí ṣ'àdúà fún èèyàn, ó túmọ̀ sí wípé, ẹnítọ̀hún á b'áko á b'ábo, kò ní ya àgàn láyée rẹ̀. #idahun #owe",0,yoruba "Maimouna Alpha Sy , akọ̀wé gbogboògbò fún Ẹgbẹ́ Ọ̀ràn Opó àti Aṣàánù ọmọ - ènìyàn , ti fi ìgbà kan rí jẹ́ aya Ba Baïdy Alassane , tí ó jẹ́ adarí àwọn ẹ̀ṣọ́ ibodè tẹ́lẹ̀ .",0,yoruba "Amọ ati ri wi pe lọpọ igba awọn eniyan fẹran iroyin ofofo tabi ti awọn oṣere ni ilẹ Yoruba. Iroyin ni Ede Gẹẹsi ko bawọn lara mu rara, bẹẹ ni wọn fẹran lati ma a bu eebu ni Comment Box. Oya ẹ wa foju lo n jẹ ninu fidio yiii:",0,yoruba Bolaji Amusan: TAMPAN ń ṣiṣẹ́ lórí 'minimum wage àti insurance' òṣèré báyìí- Mr Latin,0,yoruba Agbani lagba tan! Awi mayehun #Yoruba #OrukoJesu #OmoNaija #OjoIsimi,0,yoruba "Lonii ni Gomina Ṣeyi Makinde ti ipinlẹ Ọyọ yoo ṣide ipolongo ibo fun saa keji. Akanṣe eto naa yoo aye ni gbagede Mapo niluu Ibadan. Nibi ti awon Gomina mẹrin mii ti wọn wa ninu ẹgbẹ kan naa, 'G5' pẹlu Makinde, Nyesom Wike ti ipinlẹ Rivers, Okezie Ikpeazu ipinlẹ Abia, Samuel Ortom ti Benue ati Ifeanyi Ugwuanyi ti ipinlẹ Enugu yoo ti peju pesẹ. Ọkanojọkan aworan awọn Gomina naa lo fọn kaakiri igboro ilu Ibadan saaju abẹwo wọn l'Ọjọru. Awọn Gomina Maraarun naa lo n tako oludije si ipo aarẹ orilẹede yii labe asia PDP, Atiku Abubakar, lori ẹsun wi pe o n gbe lẹyin alaga agbe naa, Iyorcha Ayu ti wọn fẹ ki o kọwe fi ipo silẹ. Titi di asiko yii, awọn Gomina naa ko tii kede ẹni ti wọn fẹ fun ipo aarẹ orilẹede Naijiria. Iroyin to n ja rainrain ni pe o ṣeeṣe ki ikede naa waye nilu Ibadan lonii.",0,yoruba ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba "Eeyan to le ni ẹgbẹrun mẹta lo ma n jọsin ninu ijọ naa ninu isin ọjọ Aiku. Oludasilẹ ijọ naa, Alufaa Isreal Oladele Ogundipe, ni Oluṣọ ijọ naa. Lẹyin rẹ, awọn oludari ati iranṣẹ Ọlọrun mejidinlogoji lo tun wa lẹyin rẹ. Awọn ọkunrin ọlọla Eyi ni ẹgbẹ awọn ọkunrin to n jọsin ninu ijọ CCC Genesis Global. Ohun ti wọn n ṣe ninu ẹgbẹ naa ni lati ma a kọ ara wọn ni ẹkọ lati jẹ ọkunrin gidi, gẹgẹ bi ọkọ, baba, oṣiṣẹ inu ijọ ati adari. Ile ijọsin awọn ọmọde Ibi yii ni awọn ọmọ wẹwẹ ati ọdọ ti ọjọ ori wọn wa labẹ ọdun kan si ọdun mẹtadinlogun ti ma n jọsin. Ẹgbẹ awọn woli ọkunrin ati obinrin Awọn wọnyii ni ariran, agbẹnusọ, iranṣẹ, oluṣọ. Ati aṣoju ninu ijọ naa, to ma n fi adura jagun. O jẹ akojọpọ awọn awọn woli to ma n sọ asọtẹlẹ, awọn to ma n la ala, ariran ati awọn to ma n fi ede oriṣiriṣi sọrọ. Ẹgbẹ awọn ọmọ Sioni Ẹka yii ni ti iṣẹ iranṣẹ awọn obinrin inu ijọ. Ikorajọpọ wọn ni lati ma a kọ awọn obinrin lati dagba ninu ẹmi. Awọn obinrin ti ọjọ ori wọn bẹrẹ lati ọdun mejidinlogun soke lo wa ninu ẹgbẹ naa. Ẹgbẹ awọn aladura Awọn wọnyii lo ma n fi adura jagun fun awọn ọmọ ijọ naa, ati ẹnikẹni to ba fi ẹbẹ adura ranṣẹ sinu ijọ naa. Ẹka igbani nimọran Awọn to wa ninu ẹgbẹ yii lo ma n gba awọn ọmọ ni imọran lori lori ohunkohun ti wọn ba n la kọja. Awọn aṣọna Awọn wọnyii lo ma n duro ni awọn ẹnu ọna to wọ inu ṣọọṣi naa. Lara wọn lo tun ma n tun pẹpẹ ile ijọsin ṣe, ti wọn si tun ma n gba ọrẹ. Yatọ si awọn ti a ka silẹ yii, awọn ẹka oriṣiriṣi lo tun wa ninu ijọ CCC Genesis Global, to ma n ko ipa lasiko isin. Awọn akọrin-Ẹka awọn to n mojuto igbohunsafẹfẹ eto isin ninu ijọ naa. Awọn lo ma n ya aworan ati fidio ti isin ba n lọ lọwọ, ati amojuto iṣẹ iranṣẹ ori amohunmaworan ijọ naa. Ẹgbẹ awọn olukini -Awọn eeyan to ma n ki awọn alajo kaabọ sinu ijọ naa. Ẹgbẹ awọn olufifunni -Awọn to wa ninu ẹgbẹ yii lo ma n ṣoju ijọ lati fun awọn ọmọ ijọ ti ko ni i, ni ounjẹ, owo ati aṣọ. Wọn tun ma n ṣeto fifun awọn alaini awujọ ni iranlọwọ loṣooṣu. Ẹgbẹ eleto ilera - Eyi ni ẹgbẹ awọn onimọ iṣegun oyinbo to ma n tọju awọn alaisan lasiko iṣẹ iranṣẹ ilera ọfẹ, ati ẹnikẹni to ba nilo itọju lasiko ti isin n lọ lọwọ. Awọn eleto aabo - Ojuṣe awọn to wa ni ẹka yii ni lati daabo bo ile ijọin, awọn oṣiṣẹ ati awọn olujọsin ati dukia wọn, lọwọ ole, ati awọn iṣẹlẹ buruku miran. Ikọ awọn alatunṣe - Awọn to wa ninu ikọ yii lo ma n tun inu ati ayika ile ijọsin ṣe lasiko ijọsin ati lẹyin rẹ. Awọn olubẹwo - Awọn eeyan yi lo ma n ṣe amojuto awọn to ba ṣẹṣẹ darapọ mọ ijọ CCC Genesis Global. Wọn si tun ma n bẹ wọn wo lẹyin rẹ. Awọn ajihinrere - Awọn to wa ni ẹka yii lo ma n kede ihinrere kaakiri lati jere ọkan fun Jesu. AbdulQudus Bello ṣàlàyé bí òun ṣe dí aláàbọ̀ ara nítorí pọpọ́ọ̀fù àti ìbínú jàǹdùkù àdúgbò",0,yoruba "jare. Gbogbo àwọn ènìyàn wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìṣẹ́ ọ̀pọ́lọ̀.",0,yoruba ọmọ wè é wò gẹtì rẹ̀,0,yoruba "Ní ìlú kan, Ọmọ ni onidí. ìgbà kan. Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba ojú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba Àwọn ẹ̀kọ́ dídì yìí ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Eyii ni àkóbì ti.,0,yoruba #LetsPauseAndReflect #Yoruba Ronu! Igbeyin lo ma n ye oloku ada,0,yoruba èrò àti àsà tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba Ìlú yorubá lo ni ẹ̀ká àwẹ eyti o gbe lori ọ̀run dídì. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba se fi. A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà.,0,yoruba Àwon obinrin ti ìbàrà ìdí won tóbi a maa je oní ilera tó pé beeni won a maa ni laakaye. #TweetinYoruba @user @user @user https://t.co/g8CPkErs1j,0,yoruba Ó hùn mí kí n bá Ọọ̀ni àti Láí gbàmọ̀ràn pọ̀ nípa ti àṣà àti ọ̀rọ̀ afẹ́. #Yoruba,0,yoruba Diego Maradona: Ohun mẹ́wàá pàtàkì nípa Maradona àti ìbáṣepọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú ẹlẹ́sẹ̀ ayò Diego Costa rèé,0,yoruba beeni ki eleduwa jeki oju gbogbo wa ri ire aseàṣẹ nt èdàmàrè,0,yoruba ìràwọ̀ tó tan iná tó mọ́lẹ̀ jù tí ó sì sún mọ́ òṣùpá ní òfurufú ní alẹ́ àti ní kùtùkùtù òwúrọ̀ ni à ń pè ní ajá òṣùpá,0,yoruba yóò ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọba lo lọ.,0,yoruba "Awọn ayipada ti asiko ajakalẹ arun Covid-19 mu ba ilana isinku fun awọn eniyan Naijiria. Adari ileeṣẹ eleto abani sinku kan, Bolanle Okusanya Feyita kẹnu bọ ọrọ pe iyatọ nla ti de ba ọja fun wọn gẹgẹ bii abanisinku. Gba abẹ́rẹ́ Covid-19 kí o fi ọtí, ""Doughnut"", ẹ̀bùn owó ọ̀fẹ́ ṣararindin Ṣé o mọ àwọn òrìṣà ìṣẹ̀mbáyé méje tó di ilẹ̀ gbogbo àgbáyé mú? Wo àwọn ìlú tó jẹ́ ẹ̀ṣẹ̀ àti èèwọ̀ ni kí ènìyàn kú níbẹ̀ Ohun tí ìyàwó Adeboye ṣe ní ìgbà akọkọ tó fojú hàn lẹ́yìn ikú ọmọ wọn Dare Gẹgẹ bo ṣe koba awọn ile isin igbagbọ bii ṣọọṣi ati mọṣalaṣi, bẹẹ naa lo ṣe koba awọn ileeṣẹ. Eyi to koba awọn abanisinku yii kii ṣe kekere rara. Bolanle jẹ ko di mimọ pe o jẹ́ nkan aa riri tẹlẹ ki awọn idile kan ṣe adura nibi itẹ, ki wọn dẹ sinku lọsẹkẹsẹ. Iru awọn iṣẹ tio wọn maa n ri gba ni ki wọn gbe oku jo lọ si le baba oku ati ile iya oku amọ iru iṣẹ yii ka ẹsẹ ko lasiko covid-19. Paapaa awọn to jẹ pe oku ku si Naijiria amọ mọlẹbi rẹ wa lawọn orilẹede mii kaakiri agbaye, aye ati rinrinajo wa ṣe inawo rẹpẹtẹ ko si bo tilẹ jẹ pe owo wa to n gun wọ lara lati na fẹ na. Ẹwẹ, are kenge mii to tun n waye nileeṣẹ awọn abaniṣayẹyẹ isinku yii ni ki wọn maa dana sun oku di eeru. Ọrọ pọ lẹnu Bolanle Okusanya Feyita to ba BBC Yoruba sọrọ. ""Àwọn okú ọmọ Yoruba mii wa ti a fi eeru wọn ranṣẹ ti awọn ẹbi ṣẹ lọ sun si ilu wọn nigba ti eeyan ṣẹṣẹ n jade nigba ti Covid-29 rọlẹ"".",0,yoruba "mú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọmọ lo ni ìgbà mi owó àkokò, Ìyá lo mú.",0,yoruba "Yatọ si awuyewuye to n waye lori ayelujara, awọn ọmọ bibi ilẹ Yoruba kan ti fi èrò wọn han lori bi orúkọ aarẹ Naijiria nigba kan, Olusegun Obasanjo, ko ṣe sí lara orukọ ti ijọba apapọ kede lọjọ Aje fun awọn ibudokọ oju'rin ni Naijiria. Akọwe ẹgbẹ ọmọ bibi ilẹ Yoruba, Afenifere, Yinka Odumakin, sọ pe ẹ̀tanú lo mu ki ijọba Buhari yọ orukọ Obasanjo sọ ibudokọ oju'rin kankan. O ni nkan to mu ki orukọ Obafemi Awolowo wà nibẹ, naa lo yẹ ko mu ki ti Obasanjo naa pẹlu wọn. ""Nkan ti wọn ṣe yii ko bojumu, ko si le gbe wọn niyi. Ni èrò tiẹ̀, ọmọ igbimọ Agbaagba ilẹ Yoruba, Yoruba Council of Elders, Kunle Olajide sọ pe, o da oun loju pe Aarẹ Muhammadu Buhari n wa nkan nla ti yoo fi sọ ori Oloye Obasanjo ni, kii se pe o mọọmọ ma ṣe e. O fikun ọrọ rẹ pe ""ko si bi a ṣe fẹ ẹ kọ ìtàn orilẹ-ede Naijiria, lai si orukọ Baba Obasanjo"". ""Ẹni ti gbogbo aye n bọ̀wọ̀ fun ni Obasanjo nitori awọn nkan to ṣe nigba to fi jẹ aarẹ ológun, ati alagbada"". Nitori naa, ẹ ma jẹ ki a foya rara"". O fi kun ọrọ rẹ pe nkan ti gbogbo ọmọ Naijiria, ati gbogbo ẹ̀yà yoo kan sara si ni wọn yoo fun Obasanjo, eyi to wúwo lọwọ ju fífi orukọ rẹ sọ ibudokọ oju'rin. Lara awọn ọmọ ilẹ Yoruba to tun sọrọ ni Ọjọgbọn Banji Akintoye. Oun naa sọ fun BBC pe, nkan buruku gba a ni bi ìjọba apapọ ko se fi orukọ Obasanjo si ara awọn eeyan naa. O ni o yẹ ki ijọba fi ọrọ naa lọ awọn ọmọ ilẹ Yoruba ati ẹ̀yà to ku, lati gba akọsilẹ orukọ awọn eeyan to ṣe pataki si ẹ̀yà wọn, lati fun ni iru ọlá bẹ ẹ. Ọrọ ti Minisita tẹlẹ fun irinna ofurufu, Femi Fani-Kayode sọ, ko yatọ si ti Ọjọgbọn Akintoye. Kayode sọ pe orukọ Obasanjo lo yẹ ko siwaju gbogbo orukọ yoku. ""Nkan ti wọn ṣe yẹn ko dara, paapa fun ẹni to ti jẹ aarẹ Naijiria lẹẹmeji. Sugbọn sa, ọrọ naa ko le dun baba, nitori pe ọpọlọpọ ibi, oju ọna, ati agbegbe ni wọn ti fi sọ orúkọ rẹ. Awa ti a jẹ ọmọ Naijiria ni ọrọ naa n dùn."" Fani-Kayode fi kun ọrọ rẹ pe, ko tọ ọ láti maa fi ọrọ oṣelu bo ìtàn mọ́lẹ̀, nitori pe o yẹ ki wọn o bu ọlá fun ẹni to tọ si. Lori pe boya nitori pe Obasanjo ma n bu ẹnu ẹtẹ lu isejọba Aarẹ Buhari, o sọ pe eyi ko yẹ ko ribẹ. ""Nise lo yẹ ki wọn o ma a kan sára si baba yẹn, nitori pe Naijiria i ba dara ka ni bi gbogbo awọn olori orilẹ-ede to ti jẹ tẹlẹ ṣe n ṣe niyẹn"". Oriṣiriṣi awuyewuye lo ti n waye lati igba ti ikede jade pe Aarẹ Muhammadu Buhari ti fi orukọ àwọn ọmọ Naijiria kan sọ ibudokọ oju'rin. Bi awọn kan ṣe n kan saara si, ni awọn kan n bu ẹnu ẹtẹ lu u, paapa lẹyin ti ìwé iroyin Daily Trust, pé akiyesi si awọn orukọ naa ti ko ni orúkọ aarẹ Naijiria nigba kan, Olusegun Obasanjo ninu. Botilẹjẹ pe awọn kan sọ oko eebu si iwe iroyin naa, fun pe o gbe 'iroyin ti ko ni itumọ' jáde, awọn kan sọ pe ko tọ ọ bi orúkọ Obasanjo ko ṣe sí nibẹ. Amọ nigba to n fesi si awuyewuye araalu lori igbesẹ ijọba naa, agbẹnusọ fun aarẹ Muhammadu Buhari , Bashir Ahmad ni ko si ohun to jẹ pataki lori eyi. Gẹgẹ bo ti wi ""Nitori pe orukọ aarẹ tẹlẹ, Olusegun Obasanjo ko si lara orukọ awọn ọmọ Naijiria tijọba fi sọri ibudo reluwe, kii se nnkan pataki. O ni oloye Obasanjo ni wọ̀n ti fi orukọ rẹ sọri ọpọ nnkan tẹlẹ, to fi mọ ọpọ opopona ni Kano."" Ileesẹ ijọba apapọ to n risi igbokegbodo ọkọ ati eto irinna ni Naijiria ti fi atẹjade kan sita. Nínú àtẹ̀jádé yii ni wọn ti kede loni ọjọ Aje, ọjọ kẹtadinlọgbọn, osu keje pe awọn ibudokọ ọkọ oju irin ni Naijiria a gba orukọ tuntun. Awọn ibudokọ ọkọ oju irin to wa ni opopona Eko si Ibadan to fi ya lọ ba ti Lagos Port Complex to wa ni ibudokọ ọkọ oju irin Apapa ni Aare Buhari ni ki wọn fi sọri igbakeji rẹ, Ọjọgbọ Yẹmi Osinbajo. Fun alaye kikun, wo awọn orukọ ti awọn ibudokọ ọkọ oju irin naa n jẹ tẹlẹ ati orukọ tuntun ti ijọba Aarẹ Muhammadu Buhari fun wọn bayii: Ibi ti ibudokọ ọkọ oju irin naa wa Orukọ ti ibudokọ ọkọ oju irin naa n jẹ tẹlẹEni ti Buhari fi orukọ ibudokọ ọkọ oju irin tuntun naa sọri bayiiOrukó tuntun ti a o maa pe ibudokọ ọkọ oju irin naa lati isinyii Opopona Eko si Ibadan Ibudokọ ọkọ oju irin Kajọla Ọjọgbọn Yemi Osinbajo (Igbakeji Aarẹ Buhari) Ibudokọ Yemi Osinbajo Agbegbe Apapa ni ilu Eko Ibudokọ ọkọ oju irin Apapa Oloye Bola Ahmed Tinubu (Agba ẹgbẹ o'selu APC) Ibudokọ Bola Tinubu Agbegbe Ebute Metta Ibudokọ ọkọ oju irin Ebute Metta Ogagun Mobolaji Johnson ( gomina ologun ipinlẹ Eko ri) Ibudokọ Mobolaji Johnson Agbegbe Agbado Ibudokọ ọkọ oju irin Agbado Alhaji Lateef Jakande ( gomina ipinlẹ Eko ri) Ibudokọ Lateef Jakande Agbegbe Agege Ibudokọ ọkọ oju irin Agege Babatunde Raji Fashola (minista isẹ àti iléègbé bayii) Ibudokọ Babatunde Fashola Agbegbe Abeokuta Ibudokọ ọkọ oju irin Abeokuta Ọjọgbọn Wole Soyinka (agba ọjẹ onkọwe) Ibudokọ Wole Soyinka Agbegbe Papa-Lantoro Ibudokọ ọkọ oju irin Papalanto Funmilayo Ransome-Kuti (Oloogbe akinkanju obinrin Égba) Ibudokọ Funmilayo Ransome-Kuti Agbegbe Kila- Olodo Ibudokọ ọkọ oju irin OlodoOloye Olusegun Osoba (to ti jẹ gomina ipinlẹ Ogun ri) Ibudokọ Segun Osoba Agbegbe Omi Adio nitosi IbadaN Ibudokọ ọkọ oju irin Omi-Adio Oloogbe Ladoke Akintola (to ti jẹ Olootu guusu Iwo Oorun Naijiria ri) Ibudokọ Ladoke Akintola Agbegbe Ibadanibudokọ ọkọ oju irin Ibadan Oloogbe Obafemi Awolowo (Baba iran Yoruba ninu oselu) Ibudokọ Obafemi Awolowo Agbegbe aarin gbungbun akoso Ibudokọ akoso Operation Control CentreOloogbe Alex Ekwueme (to jẹ igbakeji aarẹ akọkọ ti a dibo yan ni Naijiria)Alex Ekwueme Operation Control Centre Agbegbe Agbor Ibudokọ ọkọ oju irin Agbor Omowe Goodluck Jonathan (Aarẹ Naijiria tẹlẹ) Ibudokọ Goodluck Ebele Jonathan Agbegbe Itakpe Ibudokọ ọkọ oju irin Itakpe Adamu Attah (Gomina Kwara akọkọ ti wọn dibo yan) Agbegbe Ajaokuta ni ipinlẹ Kogi Ibudokọ ọkọ oju irin Ajaokuta Oloogbe Olusola Saraki (agba oje oloselu ni Kwara) Ibudoko Olusola Saraki Agbegbe Itogbo Ibudokọ ọkọ oju irin Itogbo Augustus Aikhomu (Igbakeji aarẹ labẹ ologun tẹlẹ) Ibudoko Augustus Ahikomu Agbegbe Agenebode Ibudokọ ọkọ oju irin AgenebodeGeorge Innih (to jẹ gomina ologun ipinle Bendel/ Kwara latijọ) Ibudokọ George Innih Agbegbe Uromi Ibudokọ ọkọ oju irin Uromi Oloogbe Anthony Enahoro (Ajijangbara oselu awa ara wa) Ibudokọ Anthony Enahoro Agbegbe Akehen Ibudokọ ọkọ oju irin Ekehen Tom Ikimi (to jẹ minista ọrọ ilẹ okeere tẹlẹ) Ibudokọ Tom Ikimi Agbegbe Igbanke Ibudokọ ọkọ oju irin Igbanke Samuel Ogbemudia (To jẹ gomina ologun ipinlẹ Bendel latijọ) Ibudokọ Samuel Ogbemudia Agbegbe Abraka Ibudokọ ọkọ oju irin Abraka ni ipinlẹ Delta David Ejoor (to jẹ ọga agba adari ologun tẹlẹ) Ibudokọ David Ejoor Agbegbe Opara Ibudokọ ọkọ oju irin OparaMichael Ibru (to je gbajugbaja onisowo) Ibudokọ Michael Ibru Agbegbe Ujevwuibudokọ ọkọ oju irin Ujevwu Oloogbe Alfred Rewane (to je igbakeji aaré lasiko ologun ri) Ibudokọ Alfred Rewane Agbegbe Agboribudokọ ọkọ oju irin ni abule Reluwe ni AgborMike Akhigbe (to ti je agba ologun ri) Ibudokọ Mike Akhigbe Ileeese ijọba apapọ to kede yii salaye pe awọn eeyan wọnyii jk akọni ni Naijiria ti wọn ti gbe ogo ilẹ yii ga daadaa lati ọdun pipẹ sẹyin titi di asiko yii. Lọna ati fi ẹmi imoore han si iṣẹ ribiribi to ṣe lasiko iṣejọba rẹ, aarẹ Muhammadu Buhari ti ni ki wọn fi orukọ ofiisi reluwe to wa ni Agbo, sọrii aarẹ ana, Goodluck Jonathan. Amugbalẹgbẹ aarẹ lori ọrọ ayelujara, Tolu Ogunlesi lo fi ọrọ naa lede loju opo Twitter rẹ. Ogunlesi ni ""Aarẹ Muhammadu Buhari ti fọwọsi pe ki wọn fi ọfiisi reluwe to wa ni Agbo, ni ipinlẹ Delta sọri aarẹ Goodluck Jonathan."" ""Orukọ ti yoo maa jẹ bayii ni Goodluck Jonathan Railway Station & Complex."" Ọfiisi reluwe ọhun ni ojuko ileeṣẹ ọkọ oju irin to so Itakpe ati ilu Warri papọ, oun naa lo tun so oju ọna Benin mọ Onitsha, atawọn ilu miran ni Naijiria. Ọna oju irin naa wa lara ọna reluwe ti ijọba apapọ dawọle, eyii ti yoo so ipinlẹ Eko mọ Calabar atawọn ipinlẹ miran ni iha guusu-ila oorun Naijiria. Iṣẹ ọhun ni wọn gbe fun ileeṣẹ agbaṣẹṣe ilẹ China, CCECC lasiko iṣejọba ọmọwe Goodluck Jonathan. Ọdun 2015 ni aarẹ Buhari fidi Jonathan janlẹ ninu idibo sipo aarẹ to waye, eyii to ṣilẹkun akọsilẹ tuntun oludije sipo aarẹ akọkọ ti yoo gbo ewuro soju aarẹ to wa lori alefa ni Naijiria. Aarẹ Muhammadu Buhari ti ṣapejuwe aarẹ ana, Goodluck Jonathan gẹgẹ bi olori to jẹ olufọkansin bi Ọgbẹni Jonathan ṣe pe ẹni ọdun mejilelọgọta l'Ọjọru. Aarẹ Buhari ni Jonathan jẹ olori ti ifọkansin rẹ yoo maa jẹ iwuri fun ọpọ irandiran to n bọ lorilẹede Naijiria. Ninu atẹjade ti Buhari fi sita lati ọwọ oludamọran rẹ lori ọrọ iroyin, Femi Adeṣina, aarẹ Buhari ni imọran rere ni Jonathan n fun awọn olori Naijiria atawọn olori orilẹ-ede kaakiri ilẹ Afirika, lati igba to ti kuro ni ijọba. Buhari wa gbadura ẹmi gigun ati ilera ninu ọrọ fun Jonathan ki o lee tubọ sin orilẹede Naijiria siwaju si. Aarẹ Buhari sọ pe iwa irẹlẹ ti Jonathan ni jẹ ohun manigbagbe eleyi ti yoo mu ilọsiwaju ati idagbasoke ba awọn iran to n bọ. Buhari tun ki gbogbo idile Jonathan pe ọpọ ọdun ni yoo ṣe loke eepẹ. Aarẹ ana Jonathan gba pe oun fidi rẹmi ninu ibo aarẹ ọdun 2015, ki ajọ eleto idibo INEC to kede Buhari gẹgẹ bi ẹni to jawe olubori ninu ibo ọhun.",0,yoruba "3 • Níná ní í mú owó tán, àìnáwó: f'owó pamọ́ ní í mú owó bùyẹ̀rì. Owó t'á fi pamọ́ ni à ń rí ná bí nǹkan ò sí lọ́wọ́ ẹni lọ́la. #Abameta",0,yoruba "Fun awọn ti wọn ba n gbọ orukọ rẹ fun igba akọkọ nigba ti wọn kede rẹ pe o fidi akẹgbẹ rẹ, Umar Bago janlẹ, anfaani ree lati mọ nipa ẹni ti Fẹmi Gbajabiamila jẹ. Ki a kọkọ bẹrẹ pe oun ni o gba ipo olori ile aṣoju-ṣofin lọwọ Yakubu Dogara gẹgẹ bi olori ile kẹẹdogun lorilẹede Naijiria. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kii ṣe akọkọ ree ti Gbajabiamila yoo du ipo olori ile Lọdun 2015,Femi Gbajabiamila koju Yakubu Dogara fun ipo olori ile amọ Dogara lo jawe olubori. Saaju ki o to di aṣoju nile aṣofin, Femi Gbajabiamila ti a bi ni ọjọ kẹẹdọgbọn oṣu Kẹfa ọdun 1962, bẹrẹ iṣẹ agbẹjọro lọdun 1984 lẹyin to gboye nile Ẹkọ imọ ofin Naijiria. Femi Gbajabiamila Laarin igba naa titi di ọdun 2003 ti o kọkọ di aṣoju fun ẹkun Surulere nilu Eko nile aṣoju-ṣofin Naijiria, Femi Gbajabiamila da ile iṣẹ agbẹjọro tirẹ silẹ, ti o si tun bẹrẹ si ni kopa diẹ diẹ ninu oṣelu. Labẹ asia ẹgbẹ Alliance for Democracy, AD, lo ti bẹrẹ irinajo oṣelu rẹ, ti o si sun lọ si ACN ki o to pada kangun sinu ẹgbẹ oselu APC, nibi to ti wa jẹ olori ile lọjọ Iṣẹgun, ọjọ Kọkanla oṣu Kẹfa ọdun 2019. Kí ló mú kí àyájọ́ June 12 ṣe pàtàkì ní Nàìjíríà Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ki lawọn ipa to ti ko lagbo oṣelu? Laarin awọn akẹgbẹ rẹ nile aṣofin, ọpọ lo ma n fi oju ọlọgbọn wo Gbajabiamila, ti wọn a si ma bọwọ fun, nipa bo ti ṣe ma n se agbekalẹ ọrọ rẹ. Femi Gbajabiamila ati Ahmad Lawan aarẹ ile aṣofin Naijiria ti wọn ṣẹṣẹ yan Femi Gbajabiamila ni aṣofin to da ọrọ ofin pajawiri kan silẹ, eyi to faye gba ki igbakeji aarẹ laṣẹ lati dari ijọba, nigba ti aarẹ ko ba lagbara lati dari ijọba. Abadofin yii ni wọn gbe kalẹ labẹ ilana ''Doctrine of Necessity'' Femi Gabjabiamila ni wọn yan gẹgẹ bi olori ọmọ ẹgbẹ to pọju lọ, ni ile aṣofin kẹjọ ni Naijiria. Amọ ṣa... Toun ti bi Gbajabiamila ti ṣe jẹ ilumọka oloṣelu, o ni awọn iṣẹlẹ kan to ṣe bi ẹni tapo saṣọ ala rẹ. Akọkọ ni iroyin ti awọn alatako rẹ n gbe ka pe, o lọwọ ninu aṣemase kan nigba ti o n ṣiṣẹ gẹgẹ bi agbẹjọro nilẹ Amẹrika. Ninu esi ọrọ yi, Gbajabiamila ni oun ṣẹ labẹ ofin awọn to n ṣe akoso eto amofin ni, ti oun si ti gba ijiya to tọ. Ọrọ yii to tun jẹyọ lasiko to n du ipo olori ile, eleyi ti awọn alatako rẹ fi n sọ pe ko tọ ni ẹni to n di ipo olori ile asofin mu. Isẹlẹ miran ni i ṣe pẹlu bo ti ṣe na owo ribiribi lasiko ayẹyẹ ọjọ ibi iyawo rẹ. Owo ribiribi ti Gbajabiamila fi ra ọkọ ayọkẹlẹ ati aṣọ lasiko ayẹyẹ ọjọ ibi iyawo rẹ bi awọn eeyan ninu Ọrọ yii bi awọn eeyan ninu, ti Gbajabiamila si pada tọrọ aforijin pe oun ko ko iyan awọn ara ilu kere pẹlu rira ẹbun olowo iyebiye fun iyawo oun. Awọn ohun to yan laayo Eto ẹkọ ati ọrọ awọn oṣisẹ wa lara awọn ohun ti Gbajabiamila gbajumọ, to si ma n sọrọ nipa mimu idẹrun ba ara ilu. Gbajabiamila tun nifẹ si mimu idagbasoke ba ere idaraya ni Naijiria.",0,yoruba Àtẹ̀jáde ìtúmọ̀ 30 Agẹmọ 2019 17 : 11 GMT,0,yoruba Eḳọ tí a ní nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa àwọn ènìyàn: ti o nuni ti o.,0,yoruba a yi yi ti o nuni ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba máa dì í sọ́fun kí ó jó ojú yẹn dáadáa,0,yoruba "lọ, Nitori eyi, ara eni lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba ǹjẹ́ àdúrà ti bẹ̀rẹ̀ wọ́n ní àdúrà tí ọmọ nàìjíríà gbà lọ́jọ́ ẹtì tó kọjá ló mú yege bó bá jẹ́ òótọ́ kí àwọn aládùúrà ìjẹ́rin ó tún ṣe bẹ́ẹ̀ kí a borí argentina láṣàálẹ́ yìí àbí báwo,0,yoruba "RT @user: """"""""""""""""Emi ni ma koko jeri s'agbara Oluwa (I'll be the first to testify of God's power)"""""""""""""""". #PastorBiodun #Avalanche",0,yoruba ìṣẹ̀: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Bàbá lo aye àìlẹ̀.,0,yoruba "Jìjìn ọ̀pọ́lọ̀ ni ìbàdandun àtọ́wọ́dá, àwọn oníṣẹ́ ìṣẹ́ ni ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba ọmọ yorùbá oní ìsọkúsọ 😅😂😂👉 Yorùbátv ẸGBẸ ỌMỌ OLÚWA BÍ GBOGBO ÀGBÁYÉ Ojú òpó ìkànsíraẹni 🇳🇬🇹🇬🇧🇯🇧🇷🇨🇴🇨🇺🇬🇭🇨🇮______________________________□ Yoruba TV 🥰😘🔥 #yoruba #yorubatv #yorubaweddings #ebi #asoebi #nigerianwedding… https://t.co/JWD5rxemXW,0,yoruba "Oúnjẹ àràmọ̀ǹdà mọ́kànlá tí wọ́n ń jẹ lágbààyé rèé, ẹ tẹ́wọ́ gbàá",0,yoruba ìyẹ̀ alẹ́. Èyí ni òun tí a ní láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba Ìbàdandun ni ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn. (Item 105),0,yoruba "RT @user: @user Happy birthday to you. Ìgbà ódùn, ójò kàn.",0,yoruba "Ọmọ Àgbàakin jẹ Àgbàakin dípò bàbá rẹ̀. Àwọn olóyè bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ ni wọ́n yọ kúrò lórí oyè. Àwọn ọmọ ogun rọ̀gbà yí ìlú ká. Àwọn tó gbé ọ̀tẹ̀ dìde, dúró lórí kí ọba fi ipò sílẹ̀, tàbí kí ó gba ẹ̀mí ara rẹ̀. Ṣùgbọ́n, Aláàfin Káràán takú, kò jẹ́ mikàn. Kò",0,yoruba "Awọn eero inu ọkọ akẹru lo ku ninu isẹlẹ naa Iroyin sọ wipe awọn eeyan mẹjọ ọhun ku nigba ti ọkọ agbepo kan ati ọkọ akẹru kan kọlu ara wọn, ti ọkọ agbepo naa si gbinna. Alukoro ileesẹ ẹsọ oju popo nipinlẹ Ogun, Babatunde Akinbiyi salaye wipe, ina sẹyọ lara ọkọ agbepo ọhun ni kete ti ọkọ akẹru naa kọlu u. O ni, ""eeyan mẹjọ ni a ti fidi rẹ mulẹ pe wọn ti jalaisi ninu isẹlẹ naa nitori wọn jona guruguru ni. Awọn to fara kaasa iku ninu ijamba naa jẹ awọn ero inu agba ikẹrusi taa mọ si container, to dabi ọkọ akẹru naa.",0,yoruba "wáyé.. Nitori eyi, ara eni lo ni àṣà yorubá eyti o gbe lori ọ̀run dídì.",0,yoruba ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o wulo.,0,yoruba mùmú ni wọ́n ń pè wá,0,yoruba "#iroyin, #yoruba, Ota ilosiwaju nikan ni ko nii ri ohun meremere tijoba Aregbesola ti se l… https://t.co/VAVe69p2RY",0,yoruba "mi owó àkokò, Alàji lo tun se mú.",0,yoruba "ọ̀gbọ́n. Ìyá lo ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba ó wáyé.. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìwà: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ àti ìbi tí wọn wà.,0,yoruba Moro gbà nínú of owó ìwáṣẹ̀ tí àwọn awáṣẹ́ san tí ó ń lọ bíi ẹgbẹẹgbẹ̀rún 675 owóo naira [ $ 1 . 8 USD ] .,0,yoruba Baàlè mú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìwà: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Alàji lo ni ìwájú.,0,yoruba "The Yorùbá word """"""""""""""""Ìpolówó (Advertisement)"""""""""""""""" has 4 syllables and 4 tonal sounds (do-re-mi-mi) 👉Tell us one or more Yorùbá word in the comment section, stating the number of syllable it has. Ẹ kú ìsinmi òní #learnyoruba #tonalsound #yorubatones #syllables #LanguageLearning #Yoruba https://t.co/MQyH0d4YWm",0,yoruba "Ilana yii da lori owo ti ara ilu yoo ma san ti wọn ba fi owo ranṣẹ tabi gba owo ni banki. Ikede yi ti wọn fi sita loju opo Twitter wọn waye lẹyin eleyi ti wn sọ saaju pe iyipada ti de ba iye owo ti banki yoo ma gba lọwọ ẹni to ba gba owo nidi ATM ati loju opo ayelujara. CBN lawọn n kede awọn ilana tuntun yi gẹgẹ bi ọna lati daabo bo awọn onibara ile ifowopamọ Naijiria Àwọn aránṣọ yarí pé gbogbo ẹ̀bi kìí ṣe tàwọn, díẹ̀ wà lọ́wọ́ àwọn oníìbárà náà Bakan naa ni ile ifowopamọ agba naa sọ pe awọn ile ifowopamọ ni lati ṣe akọsilẹ aroye tawọn onibara wọn ba mu wa bi bẹẹkọ wọn yoo fara gba owo itanra miliọnu naira kan. Wọn tun ni aadọta naira ti awọn onibara n san lori rira ọja pẹlu kaadi POS ni ko yẹ ko ri bẹẹ. CBN awọn olokowo ati ileeṣẹ to n gba owo naa lọwọ onibara lo yẹ ki wọn maa san owo naa. Gbogbo awọn igbesẹ yii ni wọn ni yoo mu ki awọn onibara le gbadun idunadura pẹlu ile ifowopamọ wọn. Christmas:Ṣé ẹ ti ra fìlà ọdún? Ko yẹ ki onibara san ₦50 lori pe o san owo pẹlu POS Ẹwẹ, CBN ti ṣalaye pe owo aadọta Naira tawọn ile itaja paapa julọ ile epo n gba lọwọ alabara wọn to ba lo ẹrọ isanwo POS ko tọna. Wọn ni ile ontaja to n ta ọja falabara lo yẹ ki wọn san owo naa. Lori eto kan to waye lori ile iṣẹ amohunmaworan Channels TV ni ẹkunrẹrẹ alaye yi ti waye. Alaye naa ko ṣẹyin ibeere tawọn eeyan n beere latari ikede iyipada awọn owo to yẹ ni sisan fẹni to ba lo ẹrọ ATM. Musa Jimoh to jẹ adari ni ẹka to n mojuto sisan owo ni CBN sọ pe''iwe ta gbe sita nipa pe kawọn oniṣowo ma san owo ko tumọ si pe ki onibara wọn ma san.'' Musa tẹsiwaju pe''ti iye owo ọja ti ẹ ta ba ti kọja ẹgbẹrun kan naira,ẹyin ti ẹ n taja lẹgbọdọ san'' O ni ohun tawọn ṣalaye fawọn ile ifowopamọ ni pe awọn fẹ ki awọn olutaja tẹle aṣẹ yi ṣugbọn pupọ ninu wọn n pọn dandan fawọn onibara lati san owo naa fun wọn.",0,yoruba "Agbẹnusọ fun ẹgbẹ Nigerian Scrabble Federation, Akintunde Akinsemola, to fi idi iṣẹlẹ naa mulẹ fun BBC Yoruba ni, wọn ri oku rẹ ni agbegbe Idoani ni ijọba ibilẹ Ọṣẹ nipinlẹ Ondo. Akinṣemọla ni ọjọru to jẹ Ọjọ Kẹsan, Oṣu Kẹsan, ọdun 2020 ni o yẹ ki Paul Sodje pe ẹni ọdun marundinlọgọta. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Awọn ikọ Nigerian Scrabble Federation naa pejọ pọ lati ranti ọ̀jọ ibi rẹ lori ẹrọ ayelujara ni ọjọ naa. Paul Sodje lo dari ikọ Naijiria lọ si idije Alawọ dudu ilẹ Afrika to waye ni orilẹede Zambia ni ọdun 2012. '' Igba ti wọn ti Paul Sodje lọ san owo ẹmi aburo rẹ ti wọn jigbe ni wọn ko gburo rẹ mọ '' Nigba to n salaye bi iṣẹlẹ naa ṣe bẹrẹ ni bi ọsẹ meji sẹyin, Akinsemola ni lasiko ti wọn fẹ lọ sin mọlẹbi rẹ to ku ni ipinlẹ Delta, ni wahala naa bẹrẹ. Mayowa Omoniyi: Kò sí orin Obey, Sunny Ade abí tàkasúfèé tí ń kò le ta gìtá sí '' Ibi isinku mọlẹbi rẹ, ni wọn wa ti wọn ti gba ipe wi pe Chris, tii se aburo Paul Sodje, wa ni panpẹ awọn ajinigbe, ti wọn si ni ki wọn mu ọgọrun miliọnu wa lati tu silẹ.'' ''Awọn ẹbi ati iyawo Chris Sodje bẹ awọn agbebọn naa lati jọwọ gba miliọnu kan Naira, ti awọn ni agbara lati san.'' ''Alami ẹyẹ Scrabble ni Naijiria naa wa gbera pẹlu ọrẹ rẹ, lati lọ san owo ẹmi ti awọn ajinigbe naa beere fun ni agbegbe ti wọn ti ji gbe.'' Alaga ẹgbẹ Nigerian Scrabble Federation ni, lati igba ti wọn ti lọ san owo ẹmi naa ni wọn ko ti gburo Paul Sodje, Chris Sodje ati ọrẹ rẹ to tẹle Paul, lati lọ san owo fun awọn ajinigbe naa. Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos Akinsemola ni titi di asiko yii, ko si ẹni to le e sọ pato ohun to ṣẹlẹ laarin awọn ajinigbe naa ati awọn ti wọn lọ san owo naa. O fikun pe, ni ọjọ diẹ lẹyin iṣẹlẹ yii ni awọn darandaran naa tun ṣẹ ikọlu si Idoani, nibi ti wọn ti gbe Adari ileewosan ijọba nibẹ pẹlu awọn eniyan miran lagbegbe naa. ''Lasiko ti wọn n wa awọn eniyan ti awọn darandaran naa jigbe lọ si ileewosan to wa ni ilu Ọwọ, ni wọn ri oku Paul Sodje ati ọrẹ rẹ ni ile igbokusi to wa ni Ọwọ.'' Awọn adari ni ilu Idoani ti Otunba Oladele Olapeju ṣe adari fun ni, wọn ri oku Paul Sodje ati ọrẹ rẹ ni ilu Ajagbale, ti ko jina si ilu Ifọn.'' ''Awọn lo gbe e oku rẹ lọ si ileewosan ijọba apapọ to wa ni ilu ọwọ titi di asiko yii.'' Mo ti sa gbogbo ipa mi lati ri ọkọ mi ti wọn jigbe pada - Flora Sodje Nibayii, inu ibanujẹ ni ẹbi ati ara Paul Sodje wa lọwọlọwọ, paapaa iyawo Chris Sodje, Flora, ti ko tilẹ mọ boya ọkọ rẹ wa laye abi o ti ku. Flora, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ ni oun ti sa gbogbo ipa oun lati wa ibi ti ọkọ rẹ wa, ti o si fi to gbogbo awọn ẹsọ alaabo to wa ni Naijiria leti. O ni lati igba ti wọn ti lọ fun awọn ajinigbe naa ni owo, ni awọn darandaran naa ti kọ lati ba awọn sọrọ mọ, ti awọn ko si gburo Chris Sodje to jẹ ẹni ọdun mọkanlelogoji titi di asiko yii. Gbogbo igbiyanju BBC Yoruba lati ba ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo sọrọ lori isẹlẹ yii, si lo ja si pabo.",0,yoruba ewé ìtàkùn èso tí tí kan èpo ẹ̀hìn igi ni ó níṣẹ́ ìwòsàn tí í ṣe láàgọ́ ara wa àtẹ̀pà àpatán ráúráú ni àgbo ń pa àìsàn tòun aàrùn,0,yoruba RT @user: @user @user Boya o ti to asiko lati se apero ni orilede wa Lori Owo idagbasoke ile iwe giga,0,yoruba "kan. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba "jẹ́ ìlú tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Nitori eyi, ara eni lo je ti ibile.",0,yoruba "Ajo Eleto Ilera lagbaye, WHO ti kede pe o ṣeeṣe ki arun Coronavirus tan kale lati inu afẹfẹ. WHO ni o ṣeeṣe ki afẹfẹ gbe arun naa ni ibi ti ero ba pọ si ati ibi ti ko ba si atẹgun, amọ ajọ naa ni iwadii ṣi n lọ lọwọ lati fidiẹ mulẹ daadaa. Wọn ni ti wọn ba fi idi ẹ mulẹ pe lootọ ni arun naa n tankalẹ lati inu afẹfẹ, yoo mu atunṣe si ofin iyansọtọ dani ni inu ile ni ibi ti eniyan ba pọ si. Ohun ti Ajọ Eleto Ilera lagbaye, WHO n sọ tẹlẹ ni pe omi ara eniyan lo n fa itankalẹ arun naa. iyẹn, Ki o to di asiko yii o. Awọn onimọ Sayẹnsi to le ni igba ni ajọ WHO sọ pe wọn kọ lẹta si Ajọ WHO lati ṣe ayẹwo boya arun Coronavirus n tankalẹ lati inu afẹfẹ. Amọ, Ajọ Eleto Ilera, WHO ti ke si awọn onimọ Sayẹnsi naa lati fi aaye silẹ fun iwadii kikun lori boya arun Coronavirus le tankalẹ ninu afẹfẹ. Wọn fikun un pe ti o ba jasi otitọ, ofin ṣiṣe gaaya si ara ẹni yoo yatọ si bi o ṣe wa bayii. Awọn eniyan yoo nilo lati ma a yago fun ara ju tẹlẹ lọ paapaa ni awọn ile igbafẹ, ile ounjẹ ati ọkọ igboro lati dena itankalẹ arun naa.",0,yoruba Gbé àwọn àmì-ìwé wọlé láti:,0,yoruba "#iroyin, #yoruba, PDP ni ko je ki n ri owo osu awon osise san o - Aregbesola: Tolulope… https://t.co/9U2E5Lkqre",0,yoruba "Nínú àtẹ̀jáde tí mo kà ní @user, a ti borí ìjà ọ̀hún ... @user @user @user @user @user #TweetYoruba",0,yoruba @user Ìlú Ọba ni o.,0,yoruba "O ni Alaafin Adeyẹmi tasẹ agẹrẹ ni o. O ni Ọọni ile ifẹ nikan lo laṣẹ labẹ itan Yoruba lati da si ọrọ lọbalọba kaakiri nitori gẹgẹbi ọrọ rẹ, ""Ọọni ni olori ọba lagbaye"" O ni awọn to lee ba gomina Fayẹmi wi bo ba taṣẹ agẹrẹ wa nipinlẹ Ekiti ti ko si si idi fun Alaafin lati maa da si ọrọ laarin wọn. Fatomilọla ní Ọ̀ọ̀ni Ifẹ ní olórí aládé nílẹ̀ Yorùbá, òun ló lẹ́tọ̀ọ́ láti dá sí ọ̀rọ̀ ọba l'Ekiti Ogbontagi olukọ ede ati Aṣa Yoruba, Peter Fatomilọla ti sọ pe, bi Alaafin ilu Ọyọ, Ọba Lamidi Adeyẹmi Kẹta, ṣe dasi ọrọ awọn lọba-lọba ipinlẹ Ekiti ko bojumu to. Fatomilọla, tii se onimọ nipa asa ati ede Yoruba sọ pe, bi igba ti eeyan tasẹ agẹrẹ ni igbesẹ alaafin naa. ""Bi igba ti eniyan lọ sile onile ni. O dabi ki gomina ipinlẹ Oyo lọ si Ekiti, lọ maa da si ọrọ oṣelu wọn, yoo gba eebu ati abuku bọ ni, tori aja kii roro, ko ṣọ ojule meji."" ""To ba jẹ pe Ọọni ile Ifẹ lo gbe iru igbesẹ yii, o dara, nitori pe, oun ni olori ade gbogbo ilẹ Yoruba. Oun nikan lo le dan iru rẹ wo. Igbesẹ ti Alaafin gbe yii, o fẹ tun fi da ogun silẹ laarin awọn lọba-lọba Ekiti ni. Ọdun mẹrindinlogun si ni Oyo fi ba Ekiti jagun."" Nigba ti a beere taa ba wo ọjọ ori, ṣe alaafin ko lẹtọ lati dasi ọrọ naa, Fatomilọla sọ pe, agba ko kan ọrọ yii, kii si se ti ọjọ ori pẹlu. Ti eniyan ba dagba, o yẹ ko mọ nkan to tọ lati se. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: O ni ki Fayemi paapa ma danwo lati rọ awọn ọba loye tori awọn ọba naa lẹtọ lati yari fun gomina to ba gbe ọba ti ko tọna wa fun wọn, bẹẹ si ni kii ṣe gbogbo ọba Ekiti lo wọ igbimọ Pelupelu . ""Awọn ọba to ba tọ si bi i Ẹlẹkọle ti Ikọle, Ajero ti Ijero, Alara ti Ilara, Ewi ti Ado ati awọn miran nikan lo lẹtọ si igbimọ naa lati lọ si ipade. Wọn si tun lẹtọọ lati ba Fayemi wi, ki wọn si tun gba a nimọran to ba tasẹ agẹrẹ."" ""Oṣelu lo ti ba nkan jẹ, oun naa lo si mu ki iru Alaafin Ọyọ maa dasi nkan to n lọ l'Ekiti. Kii ṣe pe gbogbo Ekiti ko ni baba nile, wọn wa n wa baba lọ sode."" A ti sọ fun yin saaju pe ọsẹ to kọja ni Alaafin kọ lẹta kan si Gomina Fayẹmi, lẹyin ti Fayẹmi kede pe, oun yoo rọ awọn ọba kan l'oye l'Ekiti nitori pe wọn n fapajanu lori ẹni to fi jẹ alaga awọn ọba ipinlẹ naa. Coffee Painter: Adebukola ní kò sí ìrànwọ́ lẹ́yìn ẹ̀kọ́ girama lòun ṣe ń ya àwòrán Isẹlẹ yii si lo ti n fa awuye-wuye laarin awọn ọmọ ilẹ Yoruba. Ṣugbọn lọjọ aiku ni Fayẹmi lọ si ọdọ Alaafin lati ni ijiroro pẹlu rẹ, eyi to ṣeeṣe ko jẹ lori ọrọ lẹta naa.",0,yoruba "Bago àti Gbajabiamila Ọ̀pọ̀ àwọn mííràn ò kéde síta nígbà ti àwọn mííràn ni àwọn ń ba àwọn akẹgbẹ́ àwọn sọ̀rọ̀ lábẹ́lẹ̀. Femi Gbajabiamila, olùranlọ́wọ́ pàtàkì fún ààrẹ lọ́rí ọ̀rọ̀ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin Abdulrahman Sumaila, Ahmed Wase Muhammed Monguno àti àwọn míì. Ní báyìí, awọn ẹgbẹ́ amúṣẹyá ẹgbẹ òṣèlú PDP ní àwọn ti fọ́wọ́ sí láti dibò yan Ali Ndume gẹ́gk bii ààrẹ ilé ìgbìmọ aṣòfin nígbà ti wọ́n fọwọ si Umar Mohammed Bago gẹ́gẹ́ agbẹ́nusọ ilé ìgbìmọ aṣojú-ṣòfin. Eyí ní ẹgbẹ́ òṣèlú PDP fí ìdí rẹ̀ múlẹ̀ níní àtẹjáde kan tí wọn fi sita ní ààgo kan àbọ owúrọ oni tí àkọwé àpapọ̀ ẹgbẹ́ sẹnatọ Umar Ibrahim Tsauri sí fọwọ́ sí 'Mo ń ṣa ike jọ láti san owó ilé iwé ọmọ mẹ́ta' Àwọn to ti jẹ Agbẹnusọ láti ọdún 1999 Salisu Buhari 1999-2000 PDP Iwọ-òòrun -Arewa Ghali Umar Na'Abba 2000-2003 Iwọ-òòrun -Arewa Aminu Bello Masari 2003-2007 Ìwọ-òòrun -Arewa Patricai Etteh 2007 Iwọ-òòrun -Guusu Dimeji Bankole 2007-2011 Iwọ-òòrun- Guusu Aminu Waziri Tambuwal 2011-2015 wọ-òòrun -Arewa Yakubu Dogara 2015-2019 Ila-òòrun Arewa Iba Gani Adams: Bẹ́ẹ gbé màláíkà kan lọ sí Aso Rock, kò lè ṣàṣeyọrí Àwọn tó ń dupo agbénusọ ilé ìgbìmọ̀ aṣojú-ṣòfin Ẹgbẹ́ òṣèlú APC tí pín ipò agbẹnusọ sí ìwọ̀-òòrun -Guusu tí wọ́n sì yan asoju ọmọ ilé to pọ jù lọ, Femi Gbajabiamila gẹgẹ́ bi ẹni tí wọ́n fọ́wọ́ sí nígbà ti wọ́n pín ìgbá keji sí gbùngbùn Ariwa. Ṣùgbọ́n o, ìdìde Umar Mohammed Bago láti ìpínlẹ̀ Niger àti John Dyegh láti ìpinlẹ̀ Benue. Mohammed Bago ti dide pe àṣìṣe ńlá ni ẹgbẹ́ APC ṣe láti pín ipò agbẹnusọ sí ìhà iwọ oorun Guusu nítori náà oun kò fara mọ ọ àti pé ìhà gbungbu Arewa kò ti de ipò agbẹnusọ ilé ìgbìmọ aṣoju sofin ri, nítori náà òun náà yóò dije fún ipò Agbẹnusọ Muhammed nínú àtẹjade kan sàlàyé pé iha Ila-òòrun-Gusu àti Gbungbun -Arewa ní ẹgbẹ ń fiya pínpín wọn jẹ jùlọ Ní báyìí, ìdìbò tí yóò wáye ní òní ọjọ kọkanlá oṣù kẹfà ódún 2019 ń pè kí Gbajabiamila kò ni ẹtọ láti lọ nítori ó yẹ ki àwọn àṣojú ẹgbẹ́ ó tún ètò náà ṣe. Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun Ìdìbò ilé ìgbìmọ̀ aṣojú-sòfin fún sáà 2015-2019 Ẹwẹ̀, lòdì si ìpínu ẹgbẹ́ òṣèlú APC ní sáà tó kọja ni àwọn ọmọ ẹgbẹ́ APC kan pàdí àpò pọ pẹlú ẹgbẹ́ alátako láti gbé Bukola Saraki wolé gẹ́gẹ́ bíi ààrẹ ilé ìgbìmọ̀ aṣofin àti Yakubu Dogara wolé gẹ́gẹ́ bi aggbẹ́nusọ ilé aṣojú-ṣòfin. Ní bayìí aṣoju ọmọ ile to kéré jùlọ nígbà kan rí George Akime ti rọ gbogbo ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣofin àgbà àti aṣojú-ṣòfin láti ri dáju pe wọn bọ̀wọ̀ fún ipinu ẹgbẹ́ láti dibò fún Ahmed Lawan gẹ́gẹ́ bi ààrẹ ilé ìgbìmọ aṣòfin àti Femi Gbajabiamila bi agbẹ́nusọ aṣoju-ṣòfin kí ǹkan tó ṣẹlẹ̀ ní ọdún mẹ́rin sẹyìn máà tún wáye.",0,yoruba "àkokò, Baàlè ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé.",0,yoruba Jharkhand ti ṣe àkọsílẹ̀ iye ẹṣẹ̀ àwọn ènìyán ṣẹ̀ tí ó pọ̀ jù lọ tí ó tan mọ́ ìṣọdẹ - àjẹ́ àmọ́ kì í ṣe ìpínlẹ̀ náà nìkan .,0,yoruba eḳọ nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o nuni ti o ní wúlò.,0,yoruba "Arabinrin Damilola Adekoya, tii se adẹrinposonu, ti ọpọ eeyan mọ si Princess, ti ke si gbogbo araalu pe ẹnikẹni ti Baba Ijesha ba ni ajọsepọ aitọ pẹlu ọmọ rẹ, wa fi to oun leti. Princess, lasiko to n salaye bi gbajumọ osere naa se yaju si ọmọ rẹ nidi ajọsepọ laitọ, wa kesi awọn obi tabi alagbatọ to ba mọ pe Baba Ijesha ti ni ibalopọ aitọ pẹlu ọmọ oun ri tabi ti aburo rẹ, ko wa sọ fun oun. Princess, ẹni to salaye pe oun fi inu wenu, oun wa jẹ iwọ, tun gba awọn obi nimọran lati mase jẹri ẹnikẹni lati da ọmọ wọn da. Bakan naa lo tun gba awọn obi to ba ni ẹsun lori Baba Ijesha niyanju lati lọ̀ si agọ ọlọpaa to wa ni Panti, ki wọn lọ fi ẹjọ sun nitori ibẹ ni baba Ijesha wa. Princess tun sisọ loju rẹ fun araye pe ojoojumọ ni oun n yọju si agọ ọlọpaa Panti nilu Eko, nibi ti wọn ti Baba Ijesha mọ, ti ọkunrin naa si maa n rawọ ẹbẹ si oun pe ki oun jọọ, dari jin oun. O ni awọn ọlọ̀paa si n se iwadi rẹ lọwọ, to si ti jẹwọ pe ko si irọ ninu ẹsun ti wọn fi kan. ""Baba Ijesha ni oun ko hu iru iwa yii ri fun ọmọde kanakan ayafi ọmọ mi, amọ bawo ni mo se fẹ mọ pe otitọ lo n sọ. Se iru ohun to yẹ ki Baba Ijesha fi san oore ti mo se fun ree, haa, eeyan ma le o."" Alaye ti n jẹyọ lori ẹsun ifipa ba ọmọde lopọ ti wọn fi kan gbajumọ osere tiata Yoruba kan, Olanrewaju James Omiyinka, ti ọpọ mọ si Baba Ijesha. Obinrin kan to jẹ gbajugbaja adẹrinposonu to jẹ alagbatọ ọmọdebinrin ti wọn fi ẹsun kan Baba Ijesha ba lopọ, ti wa soju opo ayelujara Instagram rẹ, lati sọ fun araye nipa bi isẹlẹ naa se waye. Adẹrinposonu naa to n jẹ Princess Comedian lo n fi omije nla sọ bi isẹlẹ naa se ba a lọkan jẹ to ati bo se waye. Obinrin naa, ẹni to koro oju si bi awọn eeyan kan se n da lẹbi, tun salaye pe kii se gbogbo igba ni Baba Ijesha n wa ba ọmọ naa lopọ fun odidi ọdun meje. O ni ẹẹkan pere lo wa sile oun ni ọdun meje sẹyin, to si se ọmọ naa bi ọsẹ ti n soju. Princess ni lati igba ti isẹlẹ naa ti waye ni ọdun meje sẹyin, ni ara ti n fu oun pe nnkan ti yatọ lara ọmọ naa, to si ti n kuna gidi nipa ẹkọ rẹ. O ni ọpọ ẹbi lo n da oun lẹbi pe oun ni atẹnumọ ju amọ oun mọ pe nnkan ti yipada lara ọmọ naa. Obinrin adẹrinposonu naa ni awọn obi to wa ladugbo oun lo gba ki awọn ọmọ wọn wa maa gbe ni ọdọ oun, ti wọn si fi awọn ọmọ naa se oun laanu. O fikun pe mẹfa ni awọn ọmọ ti oun gba tọ, ọkunrin mẹta ati obinrin mẹta. Princess ni Baba Ijesha lo wa ba oun pe oun ni isoro nipa ẹkọ rẹ, o ni oun n fẹ iranlọwọ lati wọ ileẹkọ fasiti, ti oun si fi si lẹsinni. Obinrin naa tun salaye pe nigba keji ti baba Ijesha wa lẹyin ọdun meje wa se pẹki akoko ti anti oun wa wo oun, ti oun si fẹ sin jade nigba ti onitọun n lọ sile. O ni oun sọkalẹ lati lọ si geeti fun, ti oun ko si lo ju isẹju mẹta si mẹrin lọ nisalẹ, amọ oun ko mọ pe nnkan ti sẹlẹ. ""Baba Ijesha tun pada wa ni ọjọ keji lati mọ boya ọmọ naa ti sọ ohun to sẹlẹ fun gbogbo ile. Ọmọ naa ni Ijesha sọ pe ki oun kalọ sidi mọto oun lati wa gbe eso ti oun ra wọle. Amọ nigba ti wọn de isalẹ lo tun ba ọmọ naa se isekuse lẹẹkeji, lati igba naa ni ko ti wa sile mi mọ amọ nigba to ba nilo iranlọwọ, o maa n pe mi. Lọjọ kan ni mo sọ fun pe ki lo de to se n sa fun mi, o nilo iranlọwọ, o si joko sile, se emi ni ki n wa ko owo fun ọ ninu ile ni. ""Ni ọsẹ keji ti isẹlẹ naa waye, ni awọn alasẹ ileẹkọ ọmọ naa pe mi pe ki n yọju sawọn pe ọmọ naa n joko sori ọkunrin to jẹ ẹgbọn rẹ, to si n rin idi mọ ni itan. Onigbagbọ gidi ni awọn obi ọmọ naa, ti wọn si ro pe ogun ẹmi lo n ja ọmọ ọdun meje naa, koda n ki gba ki wọn wo iwokuwo lori tẹlifisan."" Princess ni ijakulẹ ti ọmọ naa tun n ni ninu ẹkọ rẹ, ko jẹ ki ara oun balẹ nitori wọn fi ọmọ naa rẹ oun lẹkun ni. O ni ọrẹ oun lo ba ọmọ naa sọrọ lati mọ idi ti isesi rẹ se yipada lẹyin ọdun meje ti isẹlẹ naa waye, ti ọmọ naa si jẹwọ oun to wa laarin rẹ ati baba Ijesha, ti otutu si mu oun. Idi ree ti mo se ni ki baba Ijesha yọju si mi, ti emi ati mama mi si ti mura silẹ pe a maa bi nipa ọrọ naa, ko sọ otitọ. ""A wa seto ẹrọ ayaworan CCTV, ta si ni ki gbogbo eeyan to wa ninu ile jade lọ. Nigba to de, o ri awọn to wa se CCTV naa, mo sọ fun pe awọn osisẹ DSTV ni wọn, mo fẹ sin wọn jade. Ni kete ta jade lo bẹrẹ si ni wa inu ile kiri lati ri pe ko si eeyan kankan ninu ile tabi pe a fi kamẹra sinu ile. Ẹ ri bi eeyan se buru to. N ko tiẹ le maa salaye awọn nnkan to se nitori a n wo bo se n se lori foonu wa. O wa mu ọmọ naa lọ sile idana nitori pe o mọ pe ko le si ẹrọ ayaworan nibẹ."" Obinrin naa wa koro oju si awọn eeyan to n sọ oun ti wọn ko mọ lori ọrọ yii lati sọra nipa isẹlẹ naa. Princess ni to ba wu awọn eeyan, ki wọn halẹ mọ oun, ohun to daju ni pe idajọ ododo yoo waye lori ẹsun toun fi kan baba Ijesha. ""To ba wu yin, ẹ lọ dena de mi, idajọ yoo waye. Se nitori pe Baba Ijẹsha jẹ osere tiata Yoruba lẹ se n gbe lẹyin rẹ? Ko si ọmọde to yẹ ki ẹnikẹni fi tipa ba lopọ, ko dara rara.",0,yoruba àjọ taskforce ti bẹ̀rẹ̀ síí ní mú àwọn elétíikún ọlọ́kadà alùpùpù tí ó bá ń gba ojúnà tí ìjọba èkó lòdì sí,0,yoruba "mi owó àkokò, Alàji lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba èdè a máa jọra ṣá àgbákò ìjàmbá ogun ni ewu ní yorùbá ewúrẹ́ ni ewu lédèe,0,yoruba ìdààmú kan ò sí fún wa rárá ohun gbogbo ń lọ ní mẹ̀lọmẹ̀lọ,0,yoruba "How Abiodun Oyebanji won in Ekiti: Fídíò bí Oyebanji ṣe la Oni, Kolawole mọ́lẹ̀ rèé",0,yoruba "Olùwo mú. Nitori eyi, ara eni ni nfàn ojú kakaaki.",0,yoruba "@user: Ìyá n'ìya mí, ẹ̀ seun. #IWD2013 http://t.co/abBuD9vg9e #Yoruba #africa",0,yoruba rere. Ìyá lo ni ìgbà àkerekere lo je ti ibile.,0,yoruba "Ọjọ ti a ba ku laa dere, eniyan o sunwọn laaye. Aye gbọ, ọrun mọ nigba ti gbajugbaja osẹre adẹrinpoṣonu, Babajide Omidina ti ọpọ mọ si Baba Suwe wọ kaa ilẹ sun l'Ọjọbọ ọjọ kẹẹdọgbọn oṣu kọkanla ọdun 2021. Baba Suwe si ti wa lori idubulẹ aisan fun igba pipẹ ki ọlọjọ to de. Ọpọ eeyan si lo gbagbọ pe aisan Baba Suwe bẹrẹ lẹyin igba ti ajọ NDLEA to n gbogun ti gbigbe oogun oloro mu un ti wọn si ju si atimọle. Ko si tun yẹ ka gbagbọ pe Baba Suwe rele ẹjọ fun igba pipẹ lori ọrọ yii eyi tawọn eeyan ni o tun dakun ilera rẹ. Bi irianjo rẹ si ahamọ ajọ to n gbogun ti gbigbe oogun oloro naa si se bẹrẹ ree: Irin ajo Baba Suwe ree pẹlu ajọ NDLEA: Ajọ NDLEA ti Baba Suwe mọle lori ẹsun pe o gbe oogun oloro Loṣu kẹwaa ọdun 2011 ni iroyin jade pe ajọ NDLEA ti mu Baba Suwe ni papakọ ofurufu ilu Eko lori ẹsun pe o gbe oogun oloro. Ajọ NDLEA ni kọmputa lo gbe jade pe egbogi oloro wa nikun Baba Suwe ti o fẹ gbe lọ si ilu Paris lorilẹede France. Bi wọn ṣe fi Baba Suwe si atimọle jẹ iyalẹnu fun ọpọ eeyan tori bi wọn ṣe fẹran rẹ gẹgẹ bi adẹrinpoṣonu. Ajọ naa ni ẹrọ to n se ayẹwo awọn arinrinajo soke okun lo ri egboogi oloro ninu Baba Suwe, ti wọn si se gbogbo ohun to yẹ lati mu ko yagbẹ. Erongba wọn ni pe boya o le su egbogi oloro mọ igbẹ amọ ko yagbẹ, eyi ti ko jẹ ki ẹri wa nilẹ lati mu rele ẹjọ pe lootọ ni Baba Suwe gbe oogun oloro. Idi si ree ti ọpọ eeyan se maa n pe Baba Suwe ni Adimeru o yagbẹ ti. Baba Suwe kuro latimọle NDLEA lẹyin ti wọn mu lori ẹsun gbigbe oogun oloro Ajọ NDLEA tu Baba Suwe silẹ ni ahamọ wọn ninu oṣu kọkanla lẹyin ti wọn ti i mọle lori ẹsun pe o gbe oogun oloro si ikun rẹ. Lẹyin to lo ọsẹ mẹta latimọle NDLEA, wọn fi Baba Suwe silẹ lẹyin ti ko yagbẹ. Awọn ololufẹ rẹ fi ijo ati ilu pade rẹ lẹyin to jade kuro ni ahamọ NDLEA. Owo to le ni ẹgbẹrun mẹta dọla $3,300 ni wọn fi gba beeli Baba Suwe. Bamidele Aturu to jẹ agbẹjọro Baba Suwe sọ fun ile ẹjọ pe oriṣiiriṣii ayẹwo ni ajọ NDLEA ṣe lori rẹ, lati se afihan oogun oloro to gbe amọ ti wọn ko si ri nkan kan. Ile ẹjọ paṣẹ pe ki NDLEA san miliọnu mẹẹdọgbọn (₦25m) owo gba ma binu fun Baba Suwe Lẹyin ọ rẹyin, ile ẹjọ giga ipinlẹ Eko paṣẹ pe ki ajọ NDLEA san miliọnu mẹẹdọgbọn naira fun Baba Suwe gẹgẹ bi owo gba ma binu. Adajọ Yetunde Idowu paṣẹ pe ajọ NDLEA gbọdọ san owo naa fun Baba Suwe laarin ọjọ mọkanlelogun. Ọgọrun miliọnu naira ni agbẹjọro Baba Suwe beere fun un, ki ile ẹjọ to paṣẹ pe ki ajọ NDLEA san miliọnu mẹẹdọgbọn. Adajọ ṣalaye ninu idajọ rẹ pe ajọ NDLEA ko ni ẹri to daju lati fidi rẹ mulẹ pe Baba Suwe gbe oogun oloro sikun. Sugbọn titi ti Baba Suwe fi jade laye lọjọ Aje, ọjọ kejilelogun osu Kọkanla ọdun 2021, adẹrinposonu naa ko ri kọbọ gba lọdọ Ajọ NDLEA. Lori ijagudu yii si ni agbẹjọro Baba Suwe, Bamidele Aturu jade laye, ti ko si si ẹni ti yoo ran alawada naa lọwọ mọ, lati gba ẹtọ rẹ pada lọwọ ijọba. Ni awọn asiko yii, Baba Suwe ti dubulẹ aisan, to si n rele iwosan ni ojoojumọ fun itọju ara rẹ, bakan naa lo nilo owo lati setọju ara rẹ. Akoko kan tiẹ wa, tawọn ẹlẹyinju aanu kede pe oloogbe naa nilo iranwọ owo fun itọju ara rẹ, ti ẹbi ara, ọrẹ atawọn onitiata si n dide lati sugba rẹ. Bakan naa lo lọ si oke okun fun itọju amọ sibẹ aisan yii ko gbọ wiwo titi ti ọlọjọ fi de ba a lẹyin ọdun mẹwa to la ẹsun ajọ NDLEA kọja. Ṣugbọn ohun ti ọpọ eeyan wa n sọ bayii ni pe boya Baba Suwe ko ba ye, ti ko ba si wa laye lonii, to ba jẹ pe o ri miliọnu mẹẹdọgbọn naira owo gba ma binu ti ile ẹjọ ni ki ajọ NDLEA san fun un gba ni. Eyi o wu ka wi, Ọlọrun mọ ju ẹda lọ.",0,yoruba ọsẹ àsa. A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba "ayin. Nitori eyi, ara eni lo ni ìwájú.",0,yoruba Ija ara aiye ati ara orun https://t.co/q1c8AQCHrv,0,yoruba "ènìyàn yì í tún ṣe àwọn iṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.",0,yoruba "Odun oro jẹ dun ti o wọpọ bi awọn ọdun egungun kan nipinlẹ Ogun Nigba to n gbe idajọ kalẹ lori ẹjọ kan ti ẹgbẹ ọmọlẹyin kristi (CAN), ati awujọ awọn musulumi ni ilu Ipokia pe lati tako ọdun oro, onidajọ Sikiru Owodunni sọ fun awọn oloro pe wọn ko ni ẹtọ kankan labẹ ofin lati paṣẹ konileogbele fun awọn olugbe Ipokia, Idi-Iroko, Ihunbo, Ifonyintedo, Ogosa, Koko, Ilaṣhe, Ibatefin, Agosasa, Oniru ati Mede. Ṣaaju ni agbẹjọro fun awọn olupẹjọ, Kayode Samson ati David Folalu ti sọ fun ile ẹjọ wipe awọn ti wọn fi ẹsun kan maa n ṣe ọdun oro wọn ninu igbo laarin oru. Wọn tẹsiwaju ninu ọrọ wọn pe niṣe ni awọn ọlọdun oro yii nawọ ayẹyẹ wọn de aarin gbungbun awọn ilu yii, ti wọn si n ti itori bẹ paṣẹ konileogbele lọsan gangan fun awọn ara ilu. Bakanna ni wọn ni igbesẹ yii nṣe idiwọ fun okoowo, ileewe, ile ijọsin, to fi mọ ileeṣẹ ijọba. Lakotan igbẹjọ naa, Owodunni pa laṣẹ pe aarin oru titi di aago mẹẹrin idaji ni wọn gbọdọ maa ṣe ọdun oro tabi gbe ẹbọ kankan, iyẹn ti awọn alaṣẹ toyẹ ba buwọlu. Ẹwẹ, ile ẹjọ naa tun ni, wọn yoo ni ki awọn olukopa ninu eto naa fi ọwọ si iwe pe alaafia yoo jọba lasiko ti wọn ba n ṣe ọdun wọn. Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹ si:",0,yoruba Grammy winners 2022: Wo àwọn tó jáwé olúborí ní Grammy Awards 2022,0,yoruba ọmọ yorùbá o,0,yoruba "àkokò, Ọba ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa aráyé: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde sí ara ilẹ̀.",0,yoruba Ìjẹ̀. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba àwọn èrò àti àsà tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba "Ọpọ ẹmi lo ti ba isẹlẹ ipaniyan Zamfara lọ Nínú ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò pẹlú akoroyin BBC, Garba Shehu ní iye agbofinro tó yẹ ni ìjọba fi ranṣẹ, lẹyìn tí wọn ṣe àyẹwò ìṣẹlẹ tó n wáyé lagbegbe náà. ""Ìjọba ìbílẹ̀ kan perei ọrọ yí kan, ti a bá sì wò dáadáa a ri wí pé àwọn ọmọ ogun wá kunju oṣuwọn, láti lèe dẹkùn awọn agbebon wọn yí'' Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Shomolu gbajúmọ̀ fún ìwé títẹ̀ Kin ni ero awọn ọmọ Naijiria lori igbesẹ yii ? Ṣùgbọ́n awọn ọmọ Naijirià kan ko le ro wí pé iye àwọn agbofinro yi tó lati dẹkun ipaniyan ni ipinlẹ Zamfara. Lójú òpó Twitter àwọn kan n ṣé àfiwé iye agbofinro ti wọn ran lo sí Zamfara, pẹlú ìyè agbofinro tó lò sí ipinle Ekiti nigba ìdìbò Gómìnà ibẹ. Onimọ eto aabo ni ‘wọn n ti-wọn n ti kọ leyin’... Onímọ̀ nípa ètò ààbò kàn lorileede Naijiria, Tony Ofoyetan nínu ero tirẹ ni, iye ọmọ ogun tí wón rán lo sí Zamfara, paapa ti pọju. ''O dami lójú wí pé, áwọn agbegbon wọnyi ko lee to ẹgbẹrun kan ti awn ọlọpaa yii jẹ́, ẹja wọn to si n daamu ibu ko to nkan. Nitori nà, egberun kan agbofinro tó fún iṣẹ tó wà nílé yí.'' Àarẹ Muhamadu Buhari ti se àbẹ̀wò sí ágbèègbè náà laipe yii Tony so wi pe, bi àwọn agbofinro naa bá ṣe iṣẹ wọn bí o ti yẹ, ''kò yẹ ki o gbawọn lásìkò láti kojú awọn jaguda wọn yi'' ''Ti wọn ba gbajumo isẹ otẹlẹmuye daada, ti ko si si ija laarin awọn agbofinro ti wọn ran lọ si Zamfara, o ye ki wahala yii dopin laipe.'' A gbo wi pe o to eeyan àádọ́jọ to padanu ẹmi wọn ninu ikolu yi laarin ọsẹ meji Ninu ikọlu to waye laipe yi, awọn janduku agbebon yà lù awọn abúlé kan ni ìpínlẹ̀ Zamfara, ti wọn sì pa èèyàn mejilelogoji nigba tí wọn kọlù abúlé méjìdínlógún láwọn ìjọba ìbílẹ̀ kan nipinlẹ naa. N se ni aworan awọn ara ilu ti wọn sa asala fun ẹmi wọn latari ikọlu naa gba ori ẹrọ ayelujara kan. O ti to ọdun mẹjo ti awọn ara ilu Zamfara ti n koju ipenija ikọlu awọn agbebon Lara wọn la ti ri eleyi ti awọn ara ilu to di eru wọn mọri, ti wọn si n rin pẹlu. Lọdun yi nikan, ọgọ̀ọ̀rọ̀ ènìyàn ni wọn ti fara káásà ninu ìkọlù aimoye to n waye nipinlẹ Zamfara.",0,yoruba "Idije yii ni yoo jẹ idanwo akọkọ fun olukọni tuntun fun ikọ Chelsea, Maurizio Sarr, lẹyin ti awọn alaṣẹ ikọ Chelsea le olukọni wọn tẹlẹ lọ Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Manchester City n kopa ninu idije naa gẹgẹ bii ẹgbẹ agbabọọlu to gba liigi saa to kọja nigba ti Chelsea n kopa gẹgẹ bii ikọ to gba ife ẹyẹ FA nilẹ Gẹẹsi. Idije ife ẹyẹ Community shield yii ni ifẹsẹwọnsẹ to maa n ṣe atọna fun saa liigi tuntun lorilẹede Gẹẹsi Idije ife ẹyẹ Community Shield yii ni ifẹsẹwọnsẹ to maa n ṣe atọna fun saa liigi tuntun nilẹ Gẹẹsi. Idije ife ẹyẹ Community shield yii ni ifẹsẹwọnsẹ to maa n ṣe atọna fun saa liigi tuntun ti ilẹ Gẹẹsi Ni agogo mẹta ọjọ Isinmi ni o ń waye. Idije yii ni yoo jẹ idanwo akọkọ fun olukọni tuntun fun ikọ Chelsea, Maurizio Sarri, lẹyin ti awọn alaṣẹ ikọ Chelsea le olukọni wọn tẹlẹ, Antonio Conte lọ ni ọjọ kẹtala, oṣu keje, ọdun yii. Ni agogo mẹta ọjọ isinmi ni yoo si maa waye 'Ẹni mọ iyì wúrà ni à ń ta awòrán fún' Ṣé ẹ rántí orin - Má ṣe jẹ́jẹ́ ma wà mi lọ?",0,yoruba "fẹ. Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "Àjàó wà lórí àkéte àìsàn nílée rẹ̀, kò s'ẹ́ni tí yóò ṣe ìtọ́júu rẹ̀. #Alo #Ajao #Yoruba",0,yoruba RT @user: @user Ilu oyinbo ni e ti le to onje repete bi eleyi. Ni Naijiria awon olowo ni kan lo le to ounje si ori tabili.,0,yoruba "Elebuibon salaye awọn ọrọ yii lasiko to n ba BBC sọrọ nipa bi awọn ẹgbẹ awo Osugbo se lọ fi tipa gbe oku ọba to waja. Saaju la ti mu iroyin wa fun yin nipa bi ẹgbẹ awo Osugbo se fi tipa gbe oku ọba kan pamọ nilẹ Ijebu. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Iroyin naa ni awọn mọlẹbi ọba naa ni ko fẹ ki wọn sin baba wọn nilana ẹsin ibilẹ eyi to mu ki wọn gba ile ẹjọ lọ. Ta lo lẹtọ lati sin oku ọba, mọlẹbi ni tabi awọn awo? Nigba to n dahun ibeere lori ẹni to lẹtọ lati sin oku ọba to ba waja, Elebuibon ni kii se mọlẹbi lo lẹtọ lati sin oku ọba rara. O ni niwọn igba ti ọba kan ba ti gori itẹ, o ti di ti gbogbo aye, oku rẹ si ti di ti araalu ati gbogbo eeyan. ""Oku ọba to ba waja kii se ti mọlẹbi mọ, awọn to lẹtọ lati sin oku rẹ naa lo lọ gbe oku naa pamọ. Boya ọba ko wa sọ fawọn mọlẹbi rẹ tẹlẹ ni pe oun ti se oro, lo mu ki wọn pe awọn Osugbo lẹjọ."" Araba Awo ilu Osogbo fikun pe ọba kọba to ba jẹ kii se ti mọlẹbi rẹ mọ, wọn ko si lẹtọ mọ lati pasẹ lori isinku rẹ. Wakili tẹẹ rí yẹn kìí ṣe ẹran rírọ̀, ó ń díbọ́n ní o - Iba Gani Adams Se ọba ni anfaani lati sọ asọtẹlẹ pe ki wọn sin oun nilana ẹsin Islam tabi ti Kritiẹni? Ọpọ igba ni isẹlẹ ti waye saaju nipa awuyewuye to maa n waye nidi ilana sinsin oku ọba to ba waja. Bakan naa nirufẹ isẹlẹ yii waye saaju nilu Abeokuta nigba ti mọlẹbi Alake tilẹ Ẹgba tẹlẹ, ọba Lipede waja faake kọri fawọn ọmọ ẹgbẹ Ogboni. Wọn ni Kabiyesi naa ti sọ asọtẹlẹ saaju pe ilana Kristiẹni ni ki wọn fi sin oun, nitori oun ti di ọmọlẹyin Kristi tootọ, ki oun to tẹri gbasọ. Nigba to n sọrọ lori asa ki awọn ọba kan maa sọ asọtẹlẹ fawọn mọlẹbi wọn lori ọna ti wọn fẹ ki wọn gba sin wọn, Elebuibon ni eyi ko tọna. ""Yoo dara ki ẹni to ba fẹ ki wọn sin oun nilana ẹsin igbalode Kristiẹni abi Musulumi ma kuku wulẹ jọba rara. Ki wọn to fi ọba jẹ, o ni oro ti wọn yoo se, ti ọba ba si tun ku, o ni oro ti wọn yoo se pẹlu. Ẹni to ba wa jẹ Kristiẹni abi Musulumi, ẹ ma wulẹ jọba. Ẹ fun ẹni to setan lati se isẹse laaye lati jọba, ka le yago fun awuyewuye ti ko tọna."" Wo obìnrin kanṣoso láàrin àwọ́n ọkunrin agunẹṣin gbafẹ́ nílùú Ilorin àmọ́ tọ́kàn rẹ̀ yii Ewu wo lo wa ninu ka sin ọba to se oro nilana ẹsin Igbalode? Araba Awo, lasiko to n salaye awọn ewu to rọ mọ ilana sinsin ọba ni ilana ẹsin igbalode salaye pe ewu n bẹ loko longẹ fun oku ọba to ba waja naa. ""Oku ọba ti wọn ko ba fi etutu tabi isẹse sin yoo ni idiwọ nla lẹnu irinajo rẹ. Awọn ara ilẹ to yẹ ko ba pade ni yoo nira fun lati ri, eyi to lewu pupọ. Bakan naa, iru ọba to waja yii ko pese ọna to tọ silẹ fun ẹlomiran to fẹ jẹ ọba lẹyin rẹ, eyi naa si lee mu idiwọ nla lọwọ. O yẹ ki wọn se bi wọn se n se lati igba iwasẹ, ko le ri bo se yẹ ko ri, bi bẹẹ kọ, o lewu."" Bone setting: Adimula Kehinde Akinfenwa ṣàlàyé nípa irúfẹ́ ẹranko tí wọ́n fi ń to eegun èy Jerusalem tabi Arab kọ ni wọn ti bi wa, alawọ dudu ni wa Oloye Ifayemi Elebuibon wa rọ ile ẹjọ lati bọwọ fun asa ati isẹse agbegbe kọọkan nilẹ Airika ati ba se n gbe igbe aye wa. ""Ilẹ alawọ dudu Afirika la wa, adajọ gbọdọ bojuwo eyi. Bi eeyan kan ba ni oun n se Musulumi, kii sa se ilẹ Arab ni wọn ti bi. Bakan naa, ẹni to ba ni oun n se Kristiẹni, kii se ilẹ Jerusalem ni wọn ti bi, bi wọn ti n se ni ilẹ Jerusalem ati Arab yatọ si tilẹ Afirika."" Ẹgbẹ́ Òṣùgbó fi tipá gbé òkú Ọba ní Ijebu, mọ̀lẹ́bí fárígá Ta lo ni ẹtọ lati sin oku ọba alaye to ba waja, ẹgbẹ awo to n dari ilu lo gbọdọ sin ọba ni ilana ibilẹ ni abi mọlẹbi ọba? Bakan naa, ilana isinku wo lo yẹ ki wọn fi sin oku ọba, se ilana ẹsin ti ọba ba n sin ni abi ilana isẹse to gba jọba ninu ilu? Ohun aburu wo lo le sẹlẹ ti wọn ko ba sin ọba nilana ẹsin ibilẹ, ti wọn si sin nilana ẹsin Kristiẹni abi ti Musulumi? Awọn ibeere yii ati ọpọ miran lo n tawọ tasẹ ninu awọn ọmọ Yoruba to gbọ nipa isẹlẹ kan to waye nilu Aba Ayepe. Gẹgẹ bi iwe iroyin Daily Trust ti jabọ rẹ, awọn ọmọ ẹgbẹ awo Osugbo lo fi tipa gbe oku Alaye-Aba tilu Aba Ayepe kuro nibi ti awọn mọlẹbi tọju oku ọba naa pamọ si. Ọjọ Kejilelogunosu Kinni ọdun 2021 ni Ọba Rauf Adebayo Raji-Suleimon, Alaye-Aba tilu Aba Ayepe, dara pọ mọ awọn baba nla rẹ, tawọn mọlẹbi rẹ ko si fẹ sin nilana ẹsin ibilẹ. Ọna lati daaabo bo isẹse lo mu kawọn ọmọ ẹgbẹ awo Osugbo ya wọ ibi ti oku naa wa, ti wsn si lọ gbe pamọ nilana ẹsin ibilẹ, eyi to bi awọn mọlẹbi ori ade to di oloogbe naa ninu. Ki lo ṣẹlẹ nigba ti ẹgbẹ awo Osugbo fi tipa gbe oku ọba? Ọrọ di isu ata yanan-yanan, tawọn mọlẹbi ọba si wọ ẹgbẹ Osugbo lọ sile ẹjọ pe wọn tako ẹtọ tawọn ni lati fun baba awọn ni ẹyẹ ikẹyin nilana ẹsin Musulumi. Awọn mọlẹbi ọba naa ni Mususlumi ododo ni ọba naa ko to waja, o si yẹ ki wọn sin ori ade naa nilana ẹsin Islam ni. Ẹjọ naa si lo pe awọn eeyan mẹẹdogun wa sile ẹjọ lati jẹjọ, awọn si lo jẹ ọmọ ẹgbẹ awo Osugbo nilẹ Ijebu nigbati igbimọ afọbajẹ tilẹ Ijebu lapapọ jẹ Olujẹjọ kẹrindinlogun. Mọlẹbi ọba naa wa n beere miliọnu lọna aadọta naira gẹgẹ bii owo gba ma binu fun bi ẹgbẹ awo Osugbo se tẹ ẹtọ wọn mọlẹ ati ti ọba to waja pẹlu. Farmers Herders Crisis: Rẹ́rẹ́ rún, ẹ̀mí àti dúkìá ṣòfò lágbègbè Ariwa Yewa Awọn ọmọ ẹgbẹ awo Osugbo wọ asọ iṣẹṣe lọ sile ẹjọ Amọ nigba ti awọn ọmọ ẹgbẹ Osugbo ọhun n yọju sile ẹjọ to n gbọ ẹjọ naa nilu Abeokuta lati wa jẹjọ, se ni awọn ẹgbẹ awo naa wọnu gbọngan ile ẹjọ pẹlu asọ awo. Bakan naa ni wọn n kọ orin isẹse to jọ mọ ẹgbẹ awo wọn, eyi ti wọn fi n tako ẹjọ naa ti idile ọba to waja pe wọn. Adajọ ti wa sun igbẹjọ siwaju di ọjọ Kẹrindinlsgbọn osu Kẹrin ọdun 2021.",0,yoruba "Àwọn agbófinró tì wà ní ibi ìjókòó náà láti rí pé nǹkan lọ geere, àbò sì wà fún àwọn akópa. #NationalConference #ConfabNG",0,yoruba "Tí ẹ bá ṣàkíyèsí ẹ̀, ẹ̀ ó rí i pé ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn orúkọ ẹranko ní èdè Gẹ̀ẹ́sì kìí ṣe èdè Gẹ̀ẹ́sì rárá. #eranko",0,yoruba "Bi igbe aye ọkunrin kan Mike Sonko se ri ree, ẹni to nifẹ wura puọ, ọpọ ohun alumọni rẹ si lo jẹ kikida goolu pọnbele. Sonko, ti inagijẹ rẹ n jẹ Sonkoree, jẹ ọdọmọde olowo lati orilẹede Kenya, bakan naa lo si tun jẹ oloselu to gbajumọ bii isana ẹlẹta. Ẹni ọdun marundinlaadọta ni Sonko, to si jẹ gomina keji ti yoo dari ilu Nairobi amọ ile asofin agba ilk naa yọ nipo gomina lori ẹsun iwa ọdaran ati asemase. Bi o tilẹ jẹ pe ọkunrin yii lo ni owo rẹ amọ ọpọ eeyan ni ẹnu maa n ya nipa awọn dukia to jẹ kikida goolu olowo iyebiye to maa n ra. Wọn ni isẹ, osi ati aini gogo nilẹ Afirika ati ni orilẹede rẹ pẹlu amọ ifẹ wura lo gba ookan aya rẹ. Awọn dukia olowo iyebiye to jẹ ti Sonko ree: Mike Sonko nifẹ wura, koda ọkọ ayọkẹlẹ rẹ gan ko gbẹyin Gbogbo inu ọọfisi Sonko gan, kikida goolu ni Olowo ni yoo ku re, wura dara , o rẹwa ni ọọfisi Sonko Ta lo le sọ pe wura ko rẹwa Kii se obinrin nikan ni ọṣọ wura dara lara wọn, o dara lara ọkunrin pẹlu, Sonko lo fidi eyi mulẹ pẹlu ẹṣọ wura to rẹwa Bi Ọba Oke ba ti fi ọkan ẹda balẹ, ẹrin ni yoo gba ẹnu rẹ Ọpa to gbe asia orilẹede soke ni ọọfice Sonko gan, wura pọnbele ni Ibi a ba jaye de ree o, eyi tun kasiara, Waini Sono, kiki wura ni igo rẹ Awọn ẹsọ ẹsin ti Sondo fi se ẹsọ ninu ọọfisi rẹ gan, goolu ni",0,yoruba Tottenham sọ ọjọ́ ìsinmi olóyin di ''Black Sunday'' mọ́ Arsenal lọ́wọ́ pẹ̀lú ìgbájú-ìgbámú,0,yoruba ìlú. ti Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba "ìwájú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Nitori eyi, ara eni yi.",0,yoruba àtẹ odù ọdún tuntun wọ̀nyí ni ìlànà àtọ̀yè tí ẹ̀dá ní láti tọ̀ kí ọdún ó ba ya abo fún un,0,yoruba àwọn àgbà ní bí kò bá nídìí obìrin kì í jẹ́ kúmólú ẹṣin ọ̀rọ̀ mìíràn ló tún ní ẹ̀ṣẹ́ kì í dédé ṣẹ́ ò kàn déédéé wáyé,0,yoruba Kò lè ṣẹ̀dá atọ́nà '%s': %s,0,yoruba "Ṣenatọ Surajudeen Ajibola Basiru, tí gbogbo ènìyàn mọ si SRJ, tíì se agbẹnusọ fun ilé igbimọ asofin àgbà ilẹ̀ wa ti ṣàlàyé pé, kò seese kí ilé asofin fi òfin de ẹnikẹ́ni, pàápàá àwọn aṣáájú wá, láti lọ gba itọju lókè òkun. Agbenuso fún ilé asofin àgbà ní bakan naa ni ọmọ sórí làwọn orile-ede míràn lagbaye, àmọ́ ó wà daba pé, ó yẹ kí ilẹ wa ṣe ìpèsè eto ìlera tó mọyàn lórí ni. Ajibola ni ""Kii se àwọn aṣáájú nìkan ló ń lọ sókè òkun, àwọn onísẹ adani, oniroyin àti àwọn èèyàn tó lowo lati lọ sókè òkun lo ń lọ gba itọju sugbọn a gbọ́dọ̀ kọ́kọ́ tọju ilé na, ká tó lọ síta ni."" Nígbà tó ń sọ̀rọ̀ lórí owoya bilionu lọ́nà ẹgbẹ̀rin àti àbọ̀ náírà tí ìjọba Nàìjíríà ṣẹ̀ṣẹ̀ yá, Ajibola ni irọ tó jinna sooto ni èyí. O ni"" ṣáájú ni ile asofin tí buwolu pé kí ìjọba lọ ya owó náà lókè òkun kí àrùn Covid-19 tó dé, àmọ́ nígbà tí àrùn náà dé, ní ìjọba tún padà wá síwájú ilé pé, kí ilé fontẹ lu u pé kí ìjọba lọ yà owó náà ni abẹle dípò òkè òkun. Lórí iyansipo rẹ bíi agbenuso fún ilé, Ajibola ni yiyan tí wọn yàn òun, tòun ṣẹ̀ṣẹ̀ wá sílè asofin àgbà fún ìgbà àkọ́kọ́, lo ṣe àfihàn ìgbẹ́kẹ̀lé tí àwọn asofin náà ni nínú òun ni. O ni òun ń ṣe iṣẹ́ tí wọn kọ́kọ́ fun òun takuntakun, ní wón tún ṣe fún òun ní isẹ akọni mìíràn, tíì ṣe agbenuso fún ilé. Nígbà tó ń sọ̀rọ̀ lórí bí ìjọba ṣe de òkun lórí àṣẹ konile ó gbélé, ó ní igbese ìjọba náà lo fihan pe, ijọba tó ń gbọ igbe aráàlú lo wà nita, eyi tó fún wọn láǹfààní láti jáde síta lọ wà jíjẹ àti mímú. ""Àmọ́ mo wà ń rọ àwọn ènìyàn wá láti tẹle asẹ ìjọba tó nii ṣe pelu òfin ìtakété síra ẹni, fifi aṣọ bo imú, ki wọn maa fi ọ̀sẹ̀ fọ ọwọ, bẹ́ẹ̀ ni kí wọn jìnnà sí ibi tí èrò bá pọ si. "" Nígbà tó ń sọ bóyá ijoba ati àwọn ọmọ Nàìjíríà tí kẹ́kọ̀ọ́ lórí àrùn Coronavirus, sẹnatọ Ajibola ni a ti kẹ́kọ̀ọ́ tó pọ̀, pàápàá julọ nípa ṣíṣe isẹ ni ile ati ṣíṣe àtúnṣe òfin ajakalẹ àrùn tó wáyé gbẹyin lọ́dún 1926, fifi ìwé ipejọ lè èèyàn lọwọ láti ipasẹ ifiweransẹ Email pẹ̀lú sise ìpàdé àti eto ìdájọ́ lójú òpó ayélujára bíi Skype, Zoom àti bẹẹ bẹẹ lọ. ""Bí ile asofin àgbà, a yà idà mẹwa ọ̀rọ̀ aje wá ṣílẹ̀ fún idagbasoke eto ìlera, ìdènà ajakalẹ àrùn àti ìmọ̀ ẹ̀rọ, tá sì tún ń ṣe agbeyẹwo àwọn òfin wá ti ọjọ́ tí lọ lórí wọn."" Aarẹ Muhammadu Buhari tun ti yan eeyan kan to ti ku si ipo bayii eleyi to ti n ṣe ọpọlọpọ eeyan ni haahin. Aarẹ fi orukọ Oloogbe Tobias Chukwuemeka Okwuru gẹgẹ bii ọkan lara awọn ọmọ igbimọ alakoso fun ajọ ijọba apapọ kan lẹyin oṣu meji to ti jade laye. Aarẹ Buhari fi iwe kan ṣọwọ si ileegbimọ aṣofin agbalorilẹede Naijiria ni ọjọ Iṣẹgun ninu eyi to kọ orukọ awọn eeyan mẹtadinlogoji to fẹ yan si ipo lai mọ pe Ọgbẹni Okwuru ti jade laye loṣu keji ọdun 2020. Bi ẹ ko ba gbagbe bi ọdun mẹta sẹyin ni iroyin lu igboro pa pe Aarẹ yan ọpọ awọn eeyan to ti jalaisi sipo akoso loniran-an-ran. Ninu ọrọ rẹ, ọkan lara awọn amugbalẹgbẹ fun aarẹ, Lauretta Onocjie ṣalaye penigba ti aarẹ kọ yan Okuru, ko tii ku nigba naa koda, 'o funra rẹ mu iwe ẹri rẹ wa ni imurasilẹ fun ifọrọwanilẹnuwo ti yoo waye ni ileegbimọ aṣofin agba.' Ní ọjọ́ Isẹgun nílé asofin àpapọ̀ ilẹ̀ wa fi ontẹ lu ọgbọn biliọnu dọla ($30bn) owo tí ijọba àpapọ̀ ilẹ̀ wá fẹ gba lọdọ àjọ ayanilowo lagbaye IMF. Láti ìgbà tí ìjọba àpapọ̀ si ti tẹ pẹpẹ owoya náà síwájú àwọn asofin àgbà, làwọn ọmọ orílẹ̀ èdè yìí tí ń béèrè pé ṣe ilẹ̀ wá tún nílò owoya kankan lásìkò tí ọrọ aje agbaye ti dagun yìí? Wọn ní ṣe akọtun ìbéèrè fún owoya yìí, èyí tí yóò mú kí gbèsè tí ilẹ wa jẹ́ láwùjọ agbaye fò fẹrẹ sì biliọnu mẹtadinlọgọrun dọla ($97bn), kò ní ṣe àkóbá ńlá fún igbaye-gbadun àti ọjọ́ ọ̀la àwọn ọmọ orílẹ̀ èdè yìí? Àmọ́ ṣe ẹni tó béèrè ọrọ, lo fẹ́ ìdí rẹ gbọ, nínú ìwádìí ikọ ìròyìn BBC Yoruba, ìjọba àpapọ̀ ti ṣàlàyé pe, oun fẹ́ gba owó náà lati fi mú kí ọrọ aje Nàìjíríà gbéra lásìkò ajakalẹ àrùn Covid-19 yìí, tí epo rọbi kò ta mọ ni ọjà àgbáyé, ti ọ̀rọ̀ aje àgbáyé si dẹnu kọlẹ. Ìjọba ni owo naa ni òun fẹ́ fi ṣe àwọn àkànṣe isẹ tó yà kalẹ ninu eto isuna ọdún 2020. Ìjọba àpapọ̀ ni àkànṣe isẹ mọkandinlọgọrun tó wà káàkiri àwọn ẹkùn idibo tí ń bẹ lorilẹede èdè yìí, làwọn yóò fi owóya náà gbọ bukata rẹ. Ìjọba sàlàyé pé, lọ́dún tó kọjá àkànṣe isẹ mẹ́rin péré nínú àwọn àkànṣe iṣẹ́ náà, ni ile asofin àgbà tó kogba wọlé fi àṣẹ si láti gbọ bukata rẹ lọ́dún 2016, nígbà tí àwọn àkànṣe isẹ yoku tí wọn kò buwọlu sì ṣe koko fún idagbasoke Naijiria. Lára àwọn àkànṣe isẹ ti ijọba si lo ṣe koko náà, tí wọn fẹ gbọ bùkátà wọn nínú owóya ọhun, lo wa ni ẹka eto ìpèsè ohun amusagbara, iwakusa, eto ọgbin, eto ìlera, ìpèsè omi tó ṣeé mú àti eto ẹ̀kọ́. Ìjọba wá rọ àwọn ọmọ Nàìjíríà láti nigbagbọ nínú ìjọba, nítorí owoya náà ní wọn yóò lo fún àwọn àkànṣe isẹ tó yẹ fún. Ewu n bẹ loko lọngẹ, longẹ gan an ewu! Aarẹ ẹgbẹ awọn dokita lorilẹede Naijiria(NMA), Dokita Francis Faduyile sọ pe oṣeeṣe kawọn agboku atawọn to wa leti iboji lasiko isinku olori awọn oṣiṣẹ Aarẹ Muhammadu Buhari, Abba Kyari ko aarun coronavirus lati bẹ. Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Dokita Faduyile ni bawọn eeyan ti pejọ leti iboji ati bawọn agboku naa ṣe gbe oku Abba Kyari tako ilana ijina sira ẹni ti ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun, NDCD la kalẹ. Aarẹ ẹgbẹ awọn dokita ni Naijiria fikun ọrọ rẹ pe ko yẹ ki ipejọpọ nibi kibi ju ogun eeyan tabi eeyan mẹẹdọgbọn lọ lasiko ti coronavirus wa lode yii. ''Aisan yii le ti ara oku ti wọn sin bọ si ara awọn eeyan to gbe posi tabi awọn eeyan to wa leti iboji,'' Dokita Faduyile lo woye bẹẹ. O ni bi awọn eeyan ti sun mọ ara wọn nibi isinku Abba Kyari le ṣakoba fun awọn ọmọ Naijiria. Dokita Faduyille sọ pe o yẹ ki gbogbo eeyan to wa nibi isinku naa yara wọn sọtọ ninu igbele fun ọjọ mẹrinla ki wọn si ṣe ayẹwo lati mọ boya wọn ko ni aarun naa. Bakan naa lo bu ẹnu atẹ bi awọn oṣiṣẹ eleto ilera ṣe bọ aṣọ idaabo bo ara ẹni lọwọ aarun nibi isinku naa. Ẹwẹ, lẹyin ọpọlọpọ ọjọ ti ile ẹjọ di da a lẹbi pe o tapa si ofin konile o gbele nipinlẹ Eko, gbaju-gbaja oṣerebinrin, Funke Akindele-Bello ti sọrọ lori iṣẹlẹ naa. Ninu fidio kan to fi sita lọjọ Aiku, Akindele dupẹ lọwọ awọn ololufẹ rẹ fun atilẹyin ati aduroti wọn lasiko to fi la 'ewu' kọja. Lẹyin to dupẹ lo ba awọn eniyan sọrọ pe otitọ ni pe aarun coronavirus wa lode. Funkẹ sọ pe ""asiko ẹkọ kikọ ni ọsẹ bi i melo sẹyin jẹ fun oun, ṣugbọn ko gbọdọ da itẹsiwaju duro."" ""Ẹyin ọrẹ mi, lootọ ni aarun coronavirus wa. Gbogbo wa lati si gbọdọ tẹsiwaju lati ṣiṣẹ pọ pẹlu ijọba ipinlẹ Eko ati ijọba apapọ nipa diuro nile, fifọwọ loorekoore ati sise iyagosiraẹni. Ijina sira ẹni yoo ṣe iranlọwọ lati kapa aarun coronavirus. O ba awọn ti eeyan wọn toi ku sọwọ coroanvirus. O ki awọn eleto ilera. Àṣìṣe ló ṣẹlẹ̀ níbi ètò ìsìnkú Abba Kyari- FCTA Awa naa gba pe aṣiṣe lo waye nibi eto isinku ati lẹyin isinku olori oṣiṣẹ fun Aarẹ Buhari, Abba Kyari- FCTA Ileesẹ ijọba apapọ to n mojuto ọrọ Abujato jẹ olu ilu Naijiria ti sọrọ lori ohun to ṣẹlẹ nibi eto isinku Abba Kyari ni iboji Gudu nilu Abuja ni ana. Wọn dupẹ lọwọ awọn ọmọ Naijiria to ya fọnran naa ati awọn to pin in titi ti ọwọ ijọba fi tẹẹ. Wọn ni iwa bi arakunrin naa ṣe bọ aṣọ idaabobo to wọ lasiko to n gbe oku Abba Kyari sọnu silẹ naa ku diẹ kaato. Eyi lo si ti jẹ ki ijọba Abuja gbe igbesẹ to yẹ pe: Ijọba ni wọn rii pe awọn ohun eelo aabo ara ẹni lọwọ ajakalẹ aarun coronavirus naa wa kaakiri iboju oku naa Ṣugbọn bayii, wọn ti lọ palẹmọ gbogbo ohun to wa nilẹ kaakiri itẹ oku ni Gudu nilu Abuja. Bakan naa ni ijọba FCTA ti lọ fin kokoro apako ati apa kokoro aifojuri kaakiri itẹ oku to wa ni agbegbe Gudu nilu Abuja lati dẹkun itankalẹ arun coronavirus. Ni Afikun, wọn ti n ko awọn eeyan ti ọrọ kan bi awọn oṣiṣẹ ni iboji oku naa si igbele fun ọjọ mẹrinla, lẹyin ti wọn yoo ṣe ayẹwo to yẹ fun wọn. Ni afikun, FCTA tun fi atẹjade sita pe awọn ti da gbogbo awọn ti ọrọ kan mọ, awọn si ti fi ara balẹ wo iṣẹ ti wọn ṣe nibẹ ati ọna abayọ siṣoro to wa bayi FCTA ṣeleri pe lẹyin isinku Abba Kyari yii, awọn lawọn yoo maa ṣeto oku ẹnikẹni ti coronavirus ba tun pa ni Abuja. Wọn fi awọn ara Abuja lọkan balẹ pe ko nii si ewuitankalẹ ajakalẹ arun corona ni Abuja ati agbegbe rẹ. Awuyewuye lórí nǹkan márùn ún tí ó níí ṣe pẹ̀lú Abba Kyari nígbà ayé rẹ̀ rèé Abba Kyari: Awuyewuye lórí nǹkan márùn ún tí ó níí ṣe pẹ̀lú olórí òṣìṣẹ́ ààrẹ Buhari tó kú rèé Bí àwọn ọmọ Nàìjíríà kan ṣe ń daro ikú Abba Kyari pé ẹni re lọ, ní àwọn míràn ń ju oko ọ̀rọ̀ lu àwọn oloselu lori ikú rẹ. Olori awọn oṣiṣẹ ni ileeṣẹ Aarẹ lorilẹede Naijiria, Abba Kyari ju awa silẹ, o dagbere faye lalẹ ọjọ Ẹti lẹyin to ba arun COVID-19 wọ iyaaja ṣugbọn ti ko lee bori. Ọpọ lo n foju wo Abba Kyari nigba aye rẹ gẹgẹ bii ẹni to lagbara julọ ni iṣejọba aarẹ Buhari. Ni ọdun 2015 ni aarẹ Buhari yan Abba Kyari gẹgẹ bii olori awọn oṣiṣẹ ni ọfiisi aarẹ; ipo yii lo si wa di ọdun ọjọ kẹtadinlogun oṣu kẹrin, ọdun 2020. Nigba aye rẹ oniruuru awuyewuye lo wọ tọọ lẹyin: Ẹsun pe Abba Kyari gba abẹtẹlẹ lọwọ ileeṣẹ ibanisọrọ MTN Lọdun 2016 lẹyin ti ajọ to n ṣakoso ẹka ibanisọrs lorilẹede Naijiria, NCC paṣẹ ki ileeṣẹ ibanisọrọ MTN o san owo itanran fun bi o ṣe kuna lati ys gbogbo nọmba ibanisọrọ awọn eeyan ti ko ṣeto iforukọsilẹ awọn nọmba ibanisọrọ wọn gẹgẹ bi ofin ṣe laa kalẹ. Wọn fi ẹsun kan oloogbe Abba Kyari nigba naa pe o gba owo ẹyin to to ẹẹdẹgbẹta miliọnu naira lọwọ ileeṣẹ naa lati lee din iye owo itanran ti wọn ni ki ileeṣẹ naa san nigba naa. Ko sẹni to fi idi eyi mulẹ nigba naa nitori Abba Kyari funra rẹ gan ke sawọn oṣiṣẹ agbofinro DSS lati wadii oun. Ẹsun pe Abba Kyari ni olori awọn igbimọ apaṣẹ wa (Cabal) ni ileeṣẹ aarẹ. Lati igba ti aarẹ Buhari ti de ori oye ni ariwo pe awọn alagbara kan wa to n paṣẹ ni ijọba rẹ ti bẹrẹ. Awọn alagbara yii ni wọn ni wọn n fi ọla jiyọ ti wọn si ti sọ aarẹ Buhari di aarẹ gbẹwudani. Ọrọ yii di ọrọ ajọsọ kaakiri orilẹede Naijiria paapaa julọ lasiko ti ara aarẹ Buhari ko fi ya to fi lọ gba itọju ni ilu Lọndọn. Gẹgẹ bi iroyin nigba naa,ko si ẹnikẹni to lee ṣe ohunkohun nigba naa bi awọn igbimọ alagbara yii ko ba fọwọ sii. Aawọ laarin Abba Kyari ati aya aarẹ, Aisha Buhari Iyawo aarẹ Buhari, Aisha Buhari ni a lee sọ pe o jẹ eeyan akọkọ lara awọn to sun mọ aarẹ Buhari to kọkọ pariwo sita pe lootọ ni awọn igbimọ alagbara yii wa. Aisha Buhari pariwo sita nigba naa pe pe awọn eeyan kan n ko aarẹ Buhari ni papa mọra ti wọn si sọ ara wọn di apaṣẹ waa ni ileeṣẹ aarẹ. Kyari ko iyan ipo igbakeji aarẹ, Oṣinbajo kere. Bakan naa ni iroyin lọ kaakiri nigba kan naa lorilẹede Naijiria to fẹsun kan Abba Kyari nigba naa pe o n lo anfani bi o ṣe sunmọ aarẹ Muhammadu Buhari lati maa fi jẹ gaba le igbakeji aarẹ, Yẹmi Oṣinbajo lori. Ọpọ awọn iwe iroyin abẹle lorilẹede Naijiria nigba naa ni wọn royin bi Abba Kyari ṣe n lo agbara aarẹ Buhari lati ti awọn ohun ti Oṣinbajo ba beere fun inawo si ẹgbẹ kan Awuyewuye pe Abba Kyari n toju bọ ọrọ to nii ṣe pẹlu abo orilẹede Naijiria. Laipẹ yii ni awọn iwe iroyin abẹle kan gbee pe iwe ijsba kan wa ti adari eto abo lorilẹede Naijiria, Babagana Monguno ti n fi ẹsun kan Abba Kyari pe o ṣe ayọjuran lọna to lewu si ọrọ eto abo orilẹede Naijiria. Bakan naa ni Monguna ti fẹsun kan Abba Kyari pe o n paṣẹ fun awọn olori ileeṣẹ alaabo gbogbo lorilẹede Naijiria, eleyi ti aarẹ funrarẹ kii mọ si lọpọ igba. Ẹ wo àwọn ẹ̀kọ́ tí ikú Abba Kyari kọ olóṣèlú Nàìjíríà - Aráàlú ṣàlàyé Yoruba ni bàa kú laa dere, èèyàn kò sunwọn ni aaye àmọ́ èyí kò rí bẹ́ẹ̀ pẹ̀lú ikú olórí òṣìṣẹ́ nílé isẹ Ààrẹ, Abba Kyari tó dara ilẹ̀.Lójú opo ikan sira ẹni Twitter àti Facebook, onírúurú ọ̀nà ni awọn ọmọ Nàìjíríà ń gba daro olóògbé náà, bí àwọn kan se kárí bọnu pé ẹni re lọ, ní àwọn miran lọ ikú rẹ láti sọ oko ọ̀rọ̀ sáwọn oloselu Nàìjíríà. Bẹẹ si ni ọ̀pọ̀ àwọn akẹẹgbẹ rẹ nínú oselu, pàápàá àwọn igun alátakò lo ń ṣe ìdárò rẹ fún ipa tó ko fún ìlọsíwájú orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Femi Fani-Kayode @realFFK daro pé òun ti pàdánù ọrẹ ogójì ọdún táwọn di jọ lọ sílè ẹ̀kọ́ fasiti Cambridge. O ṣe àpèjúwe olóògbé náà bíi èèyàn rere àti ẹni apọnle bí ó tilè jẹ́ pé èrò àwọn nínú òṣèlú ṣe ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀. Daddy Freeze @DaddyFRZ lójú òpó tiẹ̀ ni, ẹkọ mẹta ni ikú Abba Kyari kọ àwa ọmọ Nàìjíríà àtàwọn oloselu. Èkíní ni pé, ikú Kyari fìdí rẹ múlẹ̀ pé, lóòótọ́ ni àrùn Coronavirus wá, to sì ń pá èèyàn.Ẹ̀kọ́ kejì ni pé a nílò abẹrẹ ajẹsara ni kíákíá lórílẹ̀-èdè yìí tí ẹkọ kẹta si n ke si wa pé àwọn ilé ìwòsàn wá nílò àtúnṣe lọgan. Awọn mii n beere ibeere nla pé bawo la ṣe fẹ mọ pe Abba Kyari ganhan lo ku lasiko yii pé Ta lo le sọ nipato pe Kyari ni wọn n sin pe o ku? @CallMeBiola sọ ń tiẹ̀ pé, bóyá Abba Kyari lo kú àbí ẹlòmíràn, inú òun kò dùn rárá pé àrùn Covid-19 ń pá ọmọ Nàìjíríà. Bákan náà ni àwọn miran ń kesi àwọn aláṣẹ Nàìjíríà pé, kí wọn kọ ẹ̀kọ́ ńlá nípa ohun tí àwọn ọmọ Nàìjíríà ń sọ lẹ́yìn ikú Abba Kyari Wọn ni ki wọn sì máa rò ohun tí aráyé yóò sọ nípa tiwọn náà, tí wọn ba papoda. Awọn bii: @akeula_trendy Jù gbogbo rẹ lọ, àwọn oloselu Naijiria ni wọn ń kesi julọ lórí ikú olórí òṣìṣẹ́ fún Ààrẹ Buhari, láti fi ikú rẹ ṣe arikọgbọn. Ọpọ ni bí onirese wọn kò bá fín igba mọ, èyí tí wọn fín silẹ, kò leè parun láéláé ati pe ariṣe larika; arika ni baba iregun, ohunkohun ti oloṣelu kọọkan ba ṣe laraye a royin lọjọ iku rẹ. Ìfẹ́ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ló sọkùnfà ikú Kyari - Lai Mohammed Abba Kyari: Lai Mohammed sọ pé aájò kí Nàìjíríà le dára ló sọkùnfà ikú Kyari Minisita fun eto iroyin ati aṣa ni Naijiria, Lai Mohammed ti sọ pe aajo Naijiria lo pa Abba Kyari. Aarun Covid-19 ti ṣekúpa olórí àwọn òṣìṣẹ́ ní ilé ìjọba ní Abuja tó tún jẹ amúgbálẹgbẹ fún Ààrẹ Muhammadu Buhari. Lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, Lai sọ pe eniyan to fi ara ṣiṣẹ fun Naijiria, to si nifẹ orilẹ-ede naa ni Kyari jẹ nigba aye rẹ, tako bi ọpọlọpọ ṣe maa n bu ẹnu atẹ lu u. Lai ṣapejuwe Kyari gẹgẹ bi ọkan pataki ninu iṣejọba Aarẹ Muhammadu Buhari, ""nitori pe ko si nkankan ti aarẹ fẹ ẹ ṣe ti ko ni i fi to o l'eti. Oun ni alamọran aarẹ."" Gẹgẹ bi Lai ṣe sọ, ọpọlọpọ eniyan ko mọ nipa oloogbe pe o fi tọkantọkan ṣiṣẹ fun ilu wa lati ri pe iṣẹ agbẹ lọ soke, ni pataki julọ, ọrọ irẹsi gbingbin, ati ajilẹ (fertilizer) wa lara awọn nkan to mu lọkunkun dun."" Lai tẹsiwaju lati sọ pe ọrọ Kyari dabi olootọ ti kii lẹni. ""Germany to lọ to ti kagbako coronavirus, ko lọ fun igbadun ara rẹ. O lọ nitori ilu ni. Ọrọ ina mọna-mọna Naijiria lo ba lọ sibẹ. ""Aarẹ ni iku rẹ maa fi pupọ nitori pe o jẹ ẹnikan ti aarẹ gbarale pupọ fun imọran."" Wọn ti gbe oku olori awọn oṣiṣẹ fun Aarẹ Buhari, Abba Kyari de ilu Abuja fun isinku. Oluranlọwọ fun Buhari lori ọrọ ayelujara, Bashir Ahmad lo fi ikede naa sita. Èyí ni àwọn nkan tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa Abba Kyari tí coronavirus pa Abba Kyari ti iku wọlede mu lọ lẹyin ikọlu ajakalẹ arun coronavirus to n gbẹbọ lọwọ gbogbo agbaye yii jẹ odu ti kii ṣe aimọ fun oloko. Ẹya Kanuri lati ipinlẹ Borno ni olori oṣiṣẹ fun Aarẹ Muhammadu Buhari, Abba Kyari, ti aarun Covid-19 pa. Ni ọdun 1980, o gba oye imọ ijinlẹ akọkọ ninu imọ nipa ibagbepọ ẹda, Sociology, ni fasiti Warwick. Bakan naa lo gba oye imọ ijinlẹ akọkọ ninu imọ ofin ni Fasiti ilu Cambridge. Ọdun 1983 ni wọn gba a wọle si iṣẹ aṣofin ni Naijiria, lẹyin to lọ si ileewe imọ ofin Naijiria, Nigeria Law School. Yatọ si eyi, Kyari tun kẹkọọ lori idagbasoke amojuto ileeṣẹ, ni ileewe eto okoowo, Harvard Business School lọdun 1992 ati 1994. O fẹ iyawo kan, o si bi ọmọ mẹrin. Nigba aye rẹ, Kyari ṣiṣẹ amofin pẹlu gbaju-gbaja oloṣelu, oloogbe Fani-Kayode. O ṣiṣẹ gẹgẹ bi olootu iroyin nileeṣẹ New Africa Holdings Limited nilu Kaduna. Laarin ọdun 1990 si 1995, Kyari jẹ oye akọwe fun igbimọ oludari African International Bank Limited. Bakan naa lo jẹ oludari agba fun ẹka awọn alamojuto ni ile ifowopamọ United Bank for Africa, UBA, ko to di pe o di ọga patapata. Lọdun 2002, wọn yan-an gẹgẹ bi oludari igbimọ alakoso fun ileeṣẹ aladani Unilever Nigeria, ko tun to o darapọ mọ igbimọ alakoso ileeṣẹ eporọbi Exxon Mobile Nigeria. Kyari lo ṣaaju awọn aṣoju ẹkun ariwa Naijiria lọdun 1994 nibi apero National Constitutional Conference ki wọn to yan an gẹgẹ bii alaga igbimọ to n mojuto ọrọ eto aabo. Abba ti ṣiṣẹ gẹgẹ bii ọkan lara awọn ọmọ igbimọ adari ile ifowopamọ First Bank, Merchant Bank of Commerce ati ile iṣẹ Adojutofo Standard Alliance Insurance ri. Ọdun 2015 ni wọn yan Kyari gẹgẹ bi Olori awọn oṣiṣẹ fun Aarẹ Muhammadu Buhari. Kyari jẹ eniyan pataki ninu eto iṣakoso Buhari, debi pe awọn iroyin kan sọ pe oun gan-an ni onílù tó n lu ìlù fún ìròmi Aarẹ Buhari. Aarun coronavirus ti pa olori awọn oṣiṣẹ lọfiisi Aarẹ Muhammadu Buhari, Abba Kyari. Agbẹnusọ fun aarẹ Buhari, Femi Adesina lo kede iku rẹ lojo opo twitter ni oru ọjọ Abamẹta. Gẹgẹ bi Adesina ṣe sọ, ọjọ Ẹti, ọjọ kẹtadinlogun, oṣu Kẹrin ni Kyari ku. Ọjọ kẹrinlelogun, oṣu Kẹta, ọdun 2020, ni ajọ to n mojuto itankalẹ aarun ni Naijiria, NCDC, kede pe Kyari ni Covid-19. Ọjọ diẹ ṣaaju ọjọ naa ni Kyari pada si orilẹ-ede Naijiria nibi to ti lọ duna-dura okoowo kan pẹlu ileeṣẹ Siemens AG. Ilu Abuja ni wọn ti kọkọ n tọju Kyari, ko to o di pe iroyin sọ pe wọn ti gbe e wa si ilu Eko ni ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu Kta, lati maa gba itọju fun aarun naa. Ọpọlọpọ ọmọ Naijria lo si bu ẹnu atẹ lu igbesẹ naa, pẹlu alaye pe ilu ti ẹni to ni Covid-19 ba n gbe naa ni ki wọn o ti ma a tọju wọn. Iroyin sọ pe Abba Kyari ni aisan otutu aya, Pneumonia, ati awọn aisan miran ninu agọ ara rẹ, ko to di pe o ko aarun coronavirus. Awọn onimọ nipa eto ilera si ti sọ pe awọn to ba ni iru awọn aisan bẹ ẹ lara tẹlẹ ni coronavirus yara lati pa. Kyari ni olori ijọba to kọkọ ni Covid-19 ni Naijiria.",0,yoruba ilera ṣẹlẹ ni Lagos ti gbogbo eniyan sọ o dara. (2001),0,yoruba Ṣàfikún Àtòjọ-ètò Fún Ìbẹ̀rẹ̀,0,yoruba Ó sì ti ṣe amúgbálẹ́gbẹ̀ẹ́ ààrẹ Ilé ìfowópamọ́ Àgbáyé ẹ̀ka ti Ilẹ̀ Adúláwọ̀ ìgbà kan láti oṣù Igbe ọdún 2007 sí oṣù Igbe ọdún 2012 .,0,yoruba #HeritageCorner #Yoruba #FujiGospel 🎵 Tinu e ba dun ferefe k'aleluya ferefe. Haleh! Tinu e ba dun daada... https://t.co/B6mJtZEIi7,0,yoruba "mi owó àkokò, Ọba lo ni ìgbà mi owó àkokò, Baàlè ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..",0,yoruba pa Alàji lo ni ẹ̀ká àwẹ eyti o gbe lori iwa rere.,0,yoruba "Amosun Laipẹ yii ni ẹgbẹ oṣelu APC paṣẹ lọ rọọkun nile fun Gomina Ibikunle Amosun ti ipinlẹ Ogun latari pe ẹgbẹ ni o ṣe lodi si ofin ẹgbẹ nipa atilẹyin rẹ oludije gomina lab asia ẹgbẹ oṣelu mii, Abdulkabir Akinlade. Igbimọ amuṣẹya ẹgbẹ naa lo daba yii lẹyin ipade wọn ti o waye nilu Abuja. Ẹwẹ, onimọ nipa ofin kan, Jiti Ogunye nigba to ba BBC Yoruba sọrọ ṣalaye pe pupọ ninu igbesẹ awọn ẹgbẹ oṣelu lorilẹede Naijiria mọ ohun ti wọn n ṣe. Lotitọ igbesẹ gomina Amosun yoo jẹ ki awọn ẹgb mọ pe ṣekuṣẹyẹ ni iwa to wu to si lodi si ofin ẹgbẹ wọn. O jẹ ko di mimọ wi pe olori ọrọ inu rẹ ni wi pe ohun ti ẹgbẹ ba ṣe naa lawọn araalu yoo gba. ""Niwọn igba to jẹ pe ẹgbẹ APC naa lo fun un ni aaye lati dije fun ipo Sẹnetọ, ki lo de to jẹ pe igba ti wọn dibo tan ni wọn to mọ pe awọn ko fara mọ ohun ti Amosun ṣe?"" Ibikunle Amosun: Owo adani ni'ṣẹ ẹran dida, ko kan ijọba O ni agabagebe ni ẹgbẹ oṣelu APC ṣe ti wọn fi ni ki gomina Amosun lọ rọọkun nile. Amoṣa, Amofin Jiti jẹ ko di mimọ pe niwọn ti ko jẹ tuntun pe awọn oloṣelu n ṣi kuro lati ẹgbẹ kan lọ si omiran, ""ti a ba ba akata wi pe o lọ jẹ laatan, o yẹ ki a ba adiyẹ naa wi"". Nitorinaa, o ni ohun ti Amosun naa ṣe ku diẹ kaato nitori ipo lawn oloṣelu n wa kaakiri. Ohun ti Amosun ṣe, awọn gomina mii naa ti ṣe e nipinlẹ mii. Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun O ran awọn araalu leti wi pe o le da bii wi pe awọn oloṣelu n ja loju araalu ṣugbọn bo ba di ọla, wọn di ọrẹ ti wọn a maa rẹrin kaa kaa. Latari ohun ti yoo bi ni saa Amosun gẹgẹ bii Sẹnetọ labẹ asia APC, Jiti ni ọrọ oloṣelu ko ṣee da si taara nigba mii nitori bi idibo ti gomina yii ba ti pari ti wọn bura wọle fun un gẹgẹ bii sẹnetọ, fun apẹẹrẹ bi oludije aayo rẹ ko ba pegede, o le tun pinu lati pada si APC ti ẹgbẹ APC naa a si tun fọwọ paa lori.",0,yoruba "Gbolohun eemọ re lo n jade lati ẹnu awọn ọmọ orilẹ-ede Kenya lori bi ọmọ ilẹ China kan ti ṣe to ẹgba sidi ọmọọṣẹ rẹ kan to jẹ ọmọ orilẹ-ede Kenya tori pe o pẹ de ibiiṣẹ. Ni ile ounjẹ kan ti o jẹ t'awọn ọmọ ilẹ China ọhun, iyẹn Chez Wou Restaurant to ni agbegbe Kileleshwa l'olu ilu Kenya, Nairobi ni iṣẹlẹ naa ti waye. Niṣe ni oju opo ayelujara gbana lẹyin ti ilẹeṣẹ amohunmaworan kan K24 TV fi fọnran fidio han nibi ti ọkunrin, ọmọ China kan ti n na ọmọ Kenya kan lẹgba. End of Twitter post, 1 Lẹyin awuyewuye ti fidio yi mu wa, ileeṣẹ ọlọpaa ni Kenya fi ọrọ sita pe awọn ti mu awọn ọmọ ilẹ China mẹrin ti wọn n ṣiṣẹ ni ile ọunjẹ naa. Gẹgẹ bi ohun ti wọn fi sita,eniyan kan pere ninu wọn lo ni iwe aṣẹ to gba laaye lati ma ṣiṣẹ ni Kenya. Bakan naa ni wọn sọ pe awọn ọmọ Kenya mẹjọ to n ṣiṣẹ nibẹ l'awọn n wadi ọrọ lẹnu wọn. Wayi o,ileeṣẹ orileede China ni Kenya ti ni digbi lawọn wa lẹyin awọn alaṣẹ nipa wiwadi ẹni to ba tasẹ agẹrẹ sofin. Ẹ gbe lọ si Wuhan ni! Orisirisi ọrọ lawọn ọmọ Kenya ti n sọ nipa iṣẹlẹ yi, ti wọn si ni ko da ki eeyan jẹ ẹru ni ilẹ baba rẹ. @KiplangatLedama ni ti ẹ sọ pe ki wọn mu ẹni to hu iru iwa yi lọ si ilu Wuhan ti Coronavirus ti n ba awọn eeyan finra.",0,yoruba "RT @user: Alakowe yoruba...a ji daadaa oo. Iba f'Edumare """"""""""""""""""""""""""""""""@user: Ẹkú ojúmọ́ o. A à jí bí?""""""""""""""""""""""""""""""""",0,yoruba "@user: @user Mú owo wá 😎😏😊😉 Alaúfìyá"""""""" mú owó wá 😎😏😊😉 àlááfíà",0,yoruba "RT @user: Oga ju! Jimoh Oloyin de...RT""""""""""""""""..@user: Ibú fàájì la wà. Òpin-ọ̀sẹ̀ la pè é. Àwa ò lè wá kú. #Igbadun #Kelele""""""""""""""""",0,yoruba ìbàdandun ìlú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "Fásitì OAU ní ààbò àṣírí wà fún akẹ́kọ̀ọ́ yóówù tó bá ta àwọn aláṣẹ fásitì náà lólobó ìwà ìbàjẹ́ Ariwo ta lórí ìtàkùn ayélujára ní ọjọ́ ajé, nípa ọ̀jọ̀gbọ́n Richard Akindele, ti ẹ̀ka ìmọ̀ nípa ìṣirò owó tí wọ́n ní, o ń bèèrè fún ìbálòpọ̀ ìgbà máàrún ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lọ́wọ́ ọ̀kan lára àwọn akẹ́kọ́bìnrin tó fìdírẹmi nínú ìmọ̀ ẹ̀kọ́ kan tí ọ̀jọ̀gbọ́n náà ń kọ́. Ohùn àkásílẹ̀ nípa àjọsọ ọ̀rọ̀ láàárín akẹ́kọ́bìnrin ọ̀hún àti ọ̀jọ̀gbọ́n Richard Akindele lórí ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ ti wọ́n ká sílẹ̀ sórí ìkànnì ayélujára, ló tí ń jà ràìn-ràìn káàkiri báyìí. Alukoro fásitì Ọbafẹ́mi Awólọ́wọ̀ ní Ìlú Ilé ifẹ̀, OAU, Ọ̀gbẹ́ni Abíọ́dún Ọláńrewájú n,i fásitì náà ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí rẹ̀ tí wọ́n sì ti gbé ìgbìmọ̀ kan kalẹ̀ láti tú'ṣu dé ìsàlẹ̀ ìkòkò ọ̀rọ̀ náà. Fasiti OAU: À wádìí olùkọ́ tó fẹ́ bá akẹ́kọ̀ọ́ lò fún máákì Nínú ìfòròwánilẹ́nuwò rẹ̀ pẹ̀lù BBC Yorùbá, alukoro fásitì OAU ni àwọn aláṣẹ fásitì náà yóò ṣe ohun gbogbo tó bá tọ́ lórí ọ̀rọ̀ náà. OAU kò fààyè gba kí olùkọ́ fi tipá bá akẹ́kọ̀ọ́ lòpọ̀ ""A fẹ́ gbé ìgbìmọ̀ kan kalẹ̀ láti wòó bóyá nǹkan tí a gbọ́ lórí ìkànnì ayélujára jẹ́ òòtọ́ tàbí irọ́. Tó bá wá jẹ́ òòtọ́, a óò gbé ìgbésẹ tí òfin ilé ìwé yìí là kalẹ̀.""Ọ̀gbẹ́ni Abíọ́dún Ọláńrewájú ní fásitì OAU Ife kò fààye gba fífi tìpá tìkúùkù fẹ́ tàbí bá ọmọbinrin láṣepọ̀, ""yálà látọ̀dọ̀ olùkọ́ sí akẹ́kọ̀ọ́ tàbí akẹ́kọ̀ọ́ sí akẹ́kọ̀ọ́.""Ilé ìwé gíga fásitì OAU ní ààbò àṣírí wà fún akẹ́kọ̀ọ́ yóówù tó bá ta àwọn aláṣẹ fásitì náà lólobó ìwà ìbàjẹ́ lọ́gbà fásitì náà. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:",0,yoruba yorubá tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìwà: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún gbogbo.,0,yoruba "Ahmed Musa, Odion Ighalo, Kelechi Iheanacho wà lára àwọn agbábọ́ọ̀lù mẹ́ẹ̀dọ́gbọ̀n lo tí balẹ̀ sí ibùdó ìgbáradì ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Super Eagles ni ìgbáradì fún ìdíje ife ẹ̀yẹ Africa Cup of Nations (AFCON). Àwọn agbábọ́ọ̀lù mẹ́ẹ̀dọ́gbọ̀n lo tí balẹ̀ sí ibùdó ìgbáradì ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Super Eagles ni ìgbáradì fún ìdíje ife ẹ̀yẹ Africa Cup of Nations (AFCON). Ìdíje AFCON yóò wáyé fun oṣù bẹ̀rẹ̀ ní ọjọ́ Àìkú, ọjọ́ kẹsàn-án, oṣù Ṣẹẹrẹ títí di ọjọ́ kẹfà, oṣù Èrélé, ọdún 2022 ní orílẹ̀ èdè Cameroon. Ìròyìn fi yé wa pé àwọn agbábọ́ọ̀lù mẹ́ẹ̀dọ́gbọ̀n lo tí balẹ̀ sí ibùdó ìgbáradì nínú àwọn méjìdínlọ́gbọ̀n tí akọ́nimọ̀ọ́gbá fìdíẹ́ fún ikọ̀ Super Eagles, Augustine Eguavoen ráńṣẹ́ sí láti kópa nínú ìdíje náà. Ní ọjọ́ Ọjọ́rú tó ń bọ̀ yìí ni ikọ̀ Super Eagles yóò fi orílẹ̀ èdè Nàíjíríà sílẹ̀ lọ sí orílẹ̀ èdè Cameroon. Ẹwẹ̀, ọ̀pọ̀ àwọn agbábọ́ọ̀lù ikọ̀ Super Eagles láti ilẹ̀ òkèerè ló ṣì ń wọ ibùdó ìgbáradì lásìkò tí à ń kó ìròyìn yìí jọ. Èyí ló ń wáyé lẹ́yìn oṣù kan tí àjọ NFF ti fi orúkọ àwọn agbábọ́ọ̀lù tí wọ́n ráńṣẹ́ sí léde. Bákan náà, àwọn agbábọ́ọ̀lù mìíràn ń fi ibùdó ìgbáradì sílẹ̀ látaàrí ìfarapa àti àìsàn. Gẹ́gẹ́ bí àlàyé àjọ Confederation of African Football (CAF), rẹfirí mẹ́rìnlélógún àti igbákejì rẹfirí mọ́kànlélọ́gbọ̀n láti orílẹ̀ èdè mẹ́rìndínlógójì ni yóò kópa nínú ìdíje náà. Orílẹ̀ èdè Nàíjíríà, Egypt , Sudan àti Guinea Bissau tó ń ṣẹ̀ṣẹ̀ fún ìgbà àkọ́kọ́ ló wà nínú gúrùupù kan náà. Awon ti wọn pee ree ati orukọ ẹgbẹ agbabọọlu ti wọn n gba bọọlu fun ki Naijiria to ranṣẹ si wọn: Adilemu: Francis Uzoho (AC Omonia, Cyprus) John Noble (Enyimba FC) Daniel Akpeyi (Kaizer Chiefs, South Africa) Maduka Okoye (Sparta Rotterdam, The Netherlands) Atamatase: Ahmed Musa (Fatih Karagumruk, Turkey) Henry Onyekuru (Olympiacos FC, Greece) Moses Simon (FC Nantes, France) Sadiq Umar (UD Almeria, Spain) Taiwo Awoniyi (Union Berlin, Germany) Alex Iwobi (Everton FC, England) Peter Olayinka (SK Slavia Praha, Czech Republic) Kelechi Iheanacho (Leicester City, England) Awọn Agbbọọlu laarin lori Papa Frank Onyeka (Brentford FC, England) Wilfred Ndidi (Leicester City, England) Chidera Ejuke (CSKA Moscow, Russia) Kelechi Nwakali (SD Huesca, Spain) Awọn Agbabọọlu to n di ẹyin ile mu: Chidozie Awaziem (Alanyaspor FC, Turkey) Kenneth Omeruo (CD Leganes, Spain) Oluwasemilogo Ajayi (West Bromwich Albion, England) William Ekong (Watford FC, England) Olaoluwa Aina (Torino FC, Italy) Zaidu Sanusi (FC Porto, Portugal) Olisa Ndah (Orlando Pirates, South Africa) Awon miran ti wọn tun pe ni: Jamilu Collins (SC Padeborn 07, Germany) Tyrone Ebuehi (Venezia FC, Italy) Joseph Ayodele-Aribo (Glasgow Rangers, Scotland) Samuel Chukwueze (Villarreal FC, Spain) Odion Jude Ighalo (Al-Shabab Riyadh, Saudi Arabia)",0,yoruba "For Home based and Diaspora folks. Ṣé Àlàáfíà Lẹ Wà? Learn basic Yorùbá Language with @user. Greetings, Salutations and more. #YorubaLanguage #EkoEdeYoruba #YorubaDiaspora #DiasporaYoruba #PreserveAfrika #Orisa #Ifa #YorubaCulture #Yoruba #EdaDuduTV #PreserveAfrika https://t.co/MeTPbdZDqq",0,yoruba Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó ṣe pàtàkì. (Item 25),0,yoruba "Nígbà tó kún jú, àwọn ènìyàn ni ó pa Bàbá lo tun se fi.",0,yoruba iṣẹ́ ni nkan pataki lojiji. Alàji lo tun se joko. Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba ah ẹṣeun o ẹ̀yí ganan ni ìpanu gidi,0,yoruba lojiji. Ọba lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba Àlàyé rèé lórí ìdí tí MC Oluomo ṣe sún ìwóde ‘’5 milion March’’ fún Tinubu síwájú,0,yoruba @user @user Ètò àt'èrò àwọn kan ni láti jẹ owóo-gbà-máà-bínú tí ó jẹ́ ẹ̀tọ́ wa mọ́lẹ̀ bíi ejò tó gbówó mì lọ́jọ́ òní. #PapakoOfuurufu @user,0,yoruba "Orí ní í gbe ni t'áà á dádé owó, orí ní í gbe ni t'áà á tẹ̀pá ìlẹ̀kẹ̀, orí Ọlájùmọ̀kẹ́ Òrìṣàgunà tìí débi ire. Orí mi gbé èmi náà débi ire.",0,yoruba àti àsà tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba Emir of Kano: Ganduje fún Aminu Ado Bayero ní ìwé ìyannisípò gẹ́gẹ́ bí Emir ìlú Kano,0,yoruba "Ǹjẹ́ ìwọ mọ̀ wípé ní ọdún-un 1884, àwọn ogúnlémdé 50, 000 – 60, 000 tí í ṣe ọmọ Ìbàdàn/Ọ̀yọ́ ló ń gbé ní Modákẹ́kẹ́? #IfeModakeke. #Yoruba",0,yoruba "@user Ajá tó rí ìkokò tí ngbó, Ẹ̀ṣù ò ṣè ìkokò, ajá nii ṣe! :))",0,yoruba "Igba mi owó àkokò, Ìyá lo se. Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "gbé fi yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "Idi ree ti Iba Oluyole, tii se baale ile agboole naa, Alhaji Nureni Aknbi fi tẹwọgba ọmọbinrin kan, Vivian Umeh, tii gbe ilẹ Igbo dagba. Gẹgẹ ba se mu iroyin naa wa fun yin saaju, ẹya Igbo ni iya orekelẹwa obinrin naa, to si gbe salọ silu wọn lati kekere, amọ baba Vivian, tii se sọja ti kọ ni ila agboole wọn. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Alhaji Akanbi ni Vivian ko gbọ ede Yoruba rara amọ o le sọ ede Igbo loju oorun, ọpẹ ila ti wọn kọ si loju nikan lo fi han pe Yoruba ni. O ni Vivian salaye pe kekere ni oun wa, ti iya oun ti ku, ti wọn ko si jẹ ki oun wo digi rara nitori wọn ni oun yoo ku ti oun ba wo digi. ""Vivian ni amọ nigba ti oun pe ọmọ ọdun mẹjọ ni oun dọgbọn wo oju ara oun ninu digi ni kọrọ, ti oun si wa ri ila ti wọn kọ si oun ni ẹẹkẹ, eyi ti ko sẹni to kọ iru rẹ laarin awọn to sun mọ oun."" Akanbi ni ọmọbinrin naa dunkooko lati pa ara rẹ ni ọjọ to kẹyin osu kejila ọdun to kọja, tii se ọjọ ibi rẹ, o ni ayafi ti oun ba mọ awọn ẹbi oun nikan ni oun ko fi ni se bẹẹ. Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó ""Idi ree ti mo se ni mo ti gbaa bii ọmọ bibi inu mi nitori n ko fẹ ko pa ara rẹ. Ila wa loju rẹ, to si ni Ibadan ni wọn bi oun si, ọmọ ilu Ibadan naa si ni baba oun. Mo ti pe awọn ẹbi mi, mo si sọ fun wọn pe mo ti tẹwọgba ọmọ naa bii ọmọ, to si ti fara mọ pẹlu, oun naa si tẹwọ gba mi bii baba rẹ. Koda, o ti n jẹ orukọ mi, mo si n pe ni Fatimo gẹgẹ bi orukọ ti baba rẹ sọ, mo si ra irẹsi ati adiẹ fun pẹlu owo nla lati lọ fi se ọjọ ibi rẹ, ko si lọ se ajọyọ pe oun ti ni baba ati ẹbi tuntun."" Alhaji Nureni Akanbi tẹsiwaju pe ọmọbinrin naa ni ninu iwadi oun ni wọn ti sọ fun oun pe Balogun ni orukọ baba oun, amọ wọn ko ri akọsilẹ mọ nipa agboole to ti wa abi aworan rẹ. Oluwo Jogbodo Series: Ìmẹ́lẹ́ jẹ́ orísun àìnílárí, Ifá ṣe ìkìlọ̀ rẹ̀ fáwọn ará Ibadan kí O fikun pe oun ti lọ kede Vivian fun awọn akọroyin ko le rọrun lati tete ri baba rẹ. Iba Oluyole ni ọpọ awọn eeyan to jẹ abọde sọja ti wọn bimọ silẹ Igbo atawọn ẹbi wọn lo ti n wa, to fi mọ awọn ẹbi to n jẹ Balogun, gbogbo wọn ni fọto Vivian ti wọn ri ko jọ ọmọ ti wọn n wa. Amọ o ni iyalẹnu lo jẹ pe Vivian gan ti faake kọri pe oun ko wa baba kankan kiri mọ nitori oun ti mọ oun ni baba, oun si ti lọ gbadura si, ẹnikẹni ko si le gba oun lọwọ Alhaji Akanbi. Enugu ni mo ti wa, mò ń wá bàbá mí n'Ibadan, mà á pa ara mi tí ń kò bá ri- Vivian Omeh Adúgbò Ọjà‘ba nílùú Ibadan gba àlejò tí wọn kò gbà rí rí lọ́jọ́ kọkànlọ́dínlọ́gbọ̀n oṣù kejìlá ọdún 2021 nígbà ti kẹ̀kẹ̀ márúwá gbé ọmọbìnrin kan dé síbẹ̀. Ọmọbìnrin náà púpa, ó sì gà, ó jẹ́ obinrin to jẹ ojú ní gbèsè nitori arẹwa ni. Sùgbọ́n ó, kí ni kan ló ba àjàó jẹ́, apá rẹ̀ gun ju itan lọ, Bí ọmọnìnrin yìí ṣe rẹwà tó, kò rí ọkùnrin kankan fi ṣe adé-orí. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, ọmọbìnrin náà tó pé ara rẹ̀ ni Vivian Omeh ni ọ̀rọ̀ yìí gán ló fa a, tí òun fi bá ẹsẹ̀ òun sọ̀rọ̀ láti ìlú Enugu wa si ìlú Ibadan, lati mọ bàbà tó bi òun lọ́mọ. Kíni ìdí tó fi ṣẹ̀ṣẹ̀ fẹ́ mọ bàbá rẹ̀ lásìkò yìí? Gẹ́gẹ́ bi Vivian ṣe sọ, ó pẹ́ kí òun tó mọ pé, ilà tí ó wa ni ẹ̀kẹ́ òun le dá wàhálà sí òun lágbada lọ́ja iwájú. Ó ní nígbà tí àsìkò tó láti ni ọkọ, gbogbo àwọn tó n kẹnu ifẹ́ sí òun ń bèrè pé, ṣe Yoruba ni òun ni àbí Igbo. Gẹ́gẹ́ bí ó ṣe sọ, ìyá òun gbé òun sálọ sí ìlú Enugu nígbà ti òun wà ní kékere, kí bàbá òun má báa rí òun mọ́, sùgbọn wọ́n ti kọ ilà Oyo fún òun. O ní títí ìyá òun oun fi kú, ǹkan tí ó kan sọ ni pé, ológun ni bàbá òun àti pé Balogun lo n jẹ́. Ó ni nígbà tí àwọn ọmọ Igbo bẹ̀rẹ̀ si ni bèrè ìbéèrè pé, ṣe Igbo ni òun ni tàbi Yoruba, ní òun tún ni bóya kí òun máa fẹ́ Yoruba. ""Orí kọ̀ ọ̀ náà ní, àwọn ọmọ Yorùbá náà tún ni, dandan ní òun gbọ̀dọ̀ mọ ẹyẹ tó sun òun ni ìpínlẹ̀ Oyo, nítori àwọn kò lè fẹ́ obinrin to see se ko jẹ ẹbí àwọn. Eyi ló mu mi gbéra lọ sí àgbàlá Iba Olúyọlé lati lọ mọ orísún bàbá mi."" Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, àrole Iba Oluyọle Alhaji Nureni Akanbi ní nígbà ti òun gbọ́ ọ̀rọ̀ yìí, ó ká òun lára nítorí ọ̀rọ̀ ti obinrin naa sọ. ""O ní tí òun kò bá mọ bàbá òun, òun yóò pa ara òun ki ọdún tó parí, ìyẹn ọjọ́ kọkanlélọ́gbọ̀n oṣù kejìlá, tó tún jẹ́ ọjọ́ ìbí rẹ̀. Iba Oluyole ni òun ṣetan láti gba a gẹ́gẹ́ bi ọmọ, títí di ìgbà tí bàbá rẹ̀ rẹ yoo fi di mimọ. ""Mo fẹ́ gba ọ gẹ́gẹ́ bi ọmọ mí títí di ìgbà ti wọ́n yóò fi ri bàbá rẹ̀, mo ti kan sí agbẹjọ́rò mí, gbogbo ẹni to ba si fẹ́ gbà á, kí wọ́n kan sí mi"" Iwadii si n lọ lọwọ lori agboole ti baba Vivian ti wa ati boya o wa laye abi o ti jẹ Ọlọrun nipe ni. Bi gbogbo ọrọ ba si se ri, BBC Yoruba yoo maa mu wa fun yin.",0,yoruba "Adajọ Sikiru Oyinloye tun paṣẹ fun Kolade Emmanuel Balogun pe ki o san ẹgbẹrun un lọna aadọta naira gẹgẹ bi owo itanran lẹyin to jẹbi ẹsun ti ajọ EFCC fi kan an. Lati ọjọ kẹtadinlogun oṣu kẹjọ ọdun 2020 yii ni ileẹjọ so pe ki Balogun bẹrẹ si ni dari igboke-gbodo ọkọ lẹyin ileeṣẹ ijọba to n ri kikọ ile si ilu. L'Ọjọbọ, ọjọ kẹtala, oṣu kẹjọ ni EFCC fi ẹsun onikoko kan ọmọkunrin naa pe purọ pe ara rẹ ni Ọgbẹni William Davis ti inagijẹ rẹ n jẹ Behemooth lati tan obinrin alawọfunfun kan jẹ lori ẹrọ ayelujara. Agbẹjọro fun ajọ EFCC, Aliyu Adebayo ileẹjọ lati fiya to tọ jẹ Balogun nitori ohun to ṣe tako ofin orilẹede Naijiria. Amọ agbẹjọro ọmọkunrin naa, Rotimi Oyagbola rawọ ẹbọ si ileẹjọ lati fi oju aanu wo ọdọkunrin naa nirori igba akọkọ ree ti yoo ṣe iru nnkan bẹẹ. Ṣugbọn, Adajọ ni ko si awawi kan fun Balogun nitori ẹri to daju wa wi pe o jẹbi ẹsun ti wọn fi ka an. Mr Macaroni sọ nípa eré tí Fraky freaky, Sugar Daddy, You are doing well, freaky spicy fẹ́ Adajọ Oyinloye tun paṣẹ pe ki wọn gba ẹrọ ibanisọrọ ati ẹrọ kọmputa ti ọmọkunrin naa n lo lati lu awọn eeyan ni jibiti lori ayelujara, ki wọn si ko fun ijọba apapọ. jkkkkk",0,yoruba "RT @user: @user too,ti e bati wo ile oluyole,e le kan simi,mole dari yin si ibe.e ku gbigbe ede yooba laruge.",0,yoruba "Emir Ìlọrin, Shitta (ọmọ Alimi), fi ìpè ráńṣẹ́ sí Aláàfin Olúẹ̀wù ní Ọ̀yọ́, láti yọjú sí Ìlọrin, fún ìkíni ní ìbẹ̀rẹ̀ 1830. Èrò ọkàn Shitta ni láti sọ Aláàfin di Mùsùlùmí nítorí, ọba Mùsùlùmí ma ṣe àǹfààní àti ìgbéga fún Islam ní Ọ̀yọ́ Ilé",0,yoruba "kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.",0,yoruba "Ijọba ipinlẹ Eko ti buwọlu eto isinku adari ijọ Synagogue Church of All Nations (SCOAN), Woli TB Joshua to jade laye. Eyi ko ṣẹyin bii ijọ naa ṣe n reti ọpọlọpọ eniyan kaakiri agbaye ti wọn yoo ma awa si ibi isinku naa lati oni lọ. Kọmiṣọnna fun eto ilẹra nipinlẹ Eko, Ọjọgbọn Akin Abayomi to saaju awọn to ṣe abẹwọ sibẹ ni idi ti awọn fi lọ sibẹ ni lati ri pe wọn tẹlẹ ilana to de arun Coronavirus. Abayomi ni awọn n gbiyanju lati ri pe ọwọja ikẹta aarun Coronavirus to n kaakiri awọn orilẹede paapaa India, ko ja de Naijiria. O ni awọn ko fẹ ki arun Coronavirus to ti n rele ni Naijiria tun ru gẹgẹ si oke si nitori iye awọn eniyan to n bọ lati okeere wa si Naijiria. ''A tun fi asiko yii ba ẹbi ati ara oloogbe TB Joshua kẹdun ipapoda ẹni ire to lọ, paapaa ni asiko yii.'' ''Ohun ti a mọ ni pe orisirisi ọwọja aarun Coronavirus lo n ja kaakiri ni agbaye bayii, amọ a ko fẹ ko wọ ilu Eko.'' ''Lẹyin iku T.B Joshua ni gomina ipinlẹ Eko ti paṣẹ pe ki a ṣe abẹwo to yẹ si ile ijọsin naa nitori eniyan nla lo kọja lọ, ti ọpọlọpọ eniyan yoo si pejọ sibẹ.'' ''Nibayii, gbogbo ẹni to ba n bọ gbọdọ wa ni ipamọ fun ọjọ meje, lẹyin naa ni wọn to le darapọ mọ ayẹyẹ kankan.'' Bakan naa ni kọmisọnna ohun ni gbogbo eto lo ti wa lati ri pe ẹnu ibode Naijiria gbogbo lo wa ni ilana idẹkun arun Coronavirus. Gẹgẹ bi eto isinku gbajugbaja Wolii agbaye ni ati ati oludari ijọ Synagogue Church of All Nations, Temitope Joshua yoo ṣe bẹrẹ lọsẹ yii, ijọ naa ti kéde ohun to yẹ ni ṣiṣe fun awọn ti yoo wa nibi eto isinku naa. Wọn ni bo tilẹ jẹ pe isin akọkọ ti yoo waye, kii ṣe gbogbo eniyan ni yoo lanfani lati wa nibẹ tori wọn ko ṣe aye silẹ fun gbogbogbo amọ awn ti ko ba si nibẹ lee ba awọn pe lori ayelujara tabi lorii tẹlifisan wọn. Ninu fidio ti wọn fi sita lori ayelujara ijọ SCOAN lowurọ oni yii kan naa ni wọn ti ki awọn eniyan nilọ pe ki wọn ṣọra fun awọn ọdaran to n dibọn bii ileeṣẹ tẹlifisan Emmanuel tabi ijọ SCOAN lati maa beere owo lọwọ wọn fun eto isin ikẹyin Woli TB Joshua. ""Ole paraku ni iru awọn bẹẹ! Ẹ ma jẹ ki ẹnikẹni tan yin jẹ, Ọlọ run mọ bo ṣe n sọrọ si ọkan awọn eeyan lati na ọwọ si ohun ti a nilo. A o ran ẹnikẹni, a ko si ni ran ẹnikẹni lai lai"". Ileeṣẹ naa ni awọn ni ọna ti awọn fi n kan si awọn onigbọwọ awọn nipasẹ Emmanuel TV to jẹ agbẹnusọ awọn. Lẹyin eyi ni wọn kede ilana bi eto isinku ti yoo bẹrẹ lọla yoo ṣe lọ laarin ọla ọjọ karun titi di ọjọ kọkanla oṣu keje eyi ti wọn n pe akori rẹ ni ""kii ṣe temi, bikoṣe ifẹ Ọlọrun"". Bí ìlànà ìsìnkú TB Joshua yóò ṣe lọ rèé - Mọ̀lẹ́bí kéde Mo rí òkú TB Joshua tó yọ sí mi lẹ́yìn ikú rẹ̀ - Jaiye Kuti Mo rí Áńgẹ́lì mẹ́fà tó wá gbé Wòlíì TB Joshua lọ sọ́run - Àlúfáà kan kéde Wo ohun tí Dele Momodu sọ nípa TB Joshua lẹ́yìn ikú rẹ̀ Ìtàn ayé TB Joshua tó lo ọdún kan àti oṣù mẹ́ta nínú ìyà rẹ̀ Ninu ikede naa ni wọn ti ni eto idagbere nipa titan abẹla yoo waye ni ọjọ Aje ọjọ karun oṣu keje. Wọn kede pe ki awọn to n bọ ma gbagbe ati mu abẹla wọn dani. Koda wọn ni ""gbogbo ẹni ti ko ba le wa sibi eto naa, o lee tan abẹla ninu ile rẹ gẹgẹ bi ami didarapọ mọ wa lati inu ile lati bu iyi fun iranṣẹ Ọlọrun oloogbe TB Joshua"". Lọjọ keji eyi ni wọn isin orin idagbere lataarọ yoo waye ninu ijọ SCOAN to wa ni Eko ninu eyi ti ẹ o ti lanfani lati jẹri nipa ohun rere ti Ọlọrun ti lo Wolii naa lati ṣe ninu aye yin. Isin ti wọn ni aaye rẹ wa ni ṣiṣi fun gbogbo awọn eeyan amọ pẹlu aaye ijoko to lonka ni eyi ti yoo waye l'Ọjọbọ ati ọjọ Ẹti. Bi ko ba gbagbe, laip ti ikede iku Wolii Temitope jade ni Ọba ilu ibi rẹ, Arigidi-Akoko ti sọ fun ẹbi pe awọn n f ki wọn wa bu iyi fun ilu awọn nipa sinsin oku rẹ si Arigidi amọ ij pada kede ninu ijọ wn to wa ni Eko ni yoo ti waye. Nibayii, ijọ Synagogue Church of All Nations ti kede iyawo oloogbe gẹgẹ bi adari tuntun. Sunday Igboho kọ̀wé sí ìjọba àpapọ̀, o ní dandan kí wọn sàn owó gbà má bínú ₦500m ''Ṣọ́ọ̀bù ìyá rẹ̀ ní Jumoke wá tí ìbọn ọlọ́pàá ti pa lásìkò ìwọ́de Yoruba Nation ní Ojota'' Kò jọ́ọ́! Àṣìṣe kọ́, Ọlọ́pàá mọ̀ọ́mọ̀ pa ọmọ ọdún mẹ́rínlà lásìkò ìwọ́de Yoruba Nation ní Ojota - Femi Falana Gbogbo ìpilẹ̀sẹ̀ ìṣoro Nàìjíríà ni àtúnyẹ̀wò òfin ta ń ṣe yìí yóò mójútó - Gbajabiamila Ọkọ̀ òfurufú ọmọ ogun já lulẹ̀, èèyàn 92 ló wà nínú rẹ̀ Wo ohun tó yẹ kí o ṣe sí ojú abẹ́ rẹ, ''vagina'' lẹ́yìn ìbálòpọ̀",0,yoruba "@user Ẹ̀ṣọ́ jẹ́ 'ẹni tó ń ṣọ́ nǹkan, òde tàbí ìlú'. Jagunjagun ìlú Ìkòyí Ọ̀yọ́-Ilé ni Ìkòyí Ẹ̀ṣọ́.",0,yoruba "Ọjọ́ 1-4-2015, ọ̀gágun Muhammadu Buhari t'ó ti fìgbà kan rí jẹ́ ààrẹ ilẹ̀ #Nigeria ní ọdún 1983 ni ó jáwé olúborí ìbò ààrẹ. #NigeriaTitun",0,yoruba èmi ni ìkòròdú ọmọ ọ̀gà ọmọ ẹ̀lúkú mẹdẹ́n mẹdẹ́n ọmọ ẹ̀lúkú mẹdẹ̀n mẹdẹ̀n ọmọ afínjú jẹ̀bú rè fọmọrẹ̀ japènà ̀bá,0,yoruba "àìlẹ̀, Olùwo ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Nitori eyi, ara eni lo ni àṣà yorubá eyti o gbe lori àìmọ́ kọ.",0,yoruba "ADP ni adisokan lati fi aaye gba ọdọ ati obinrin ninu eto oselu Ikede to se atọna igbese rẹ yii jẹyọ loju opo Twitter rẹ . Ninu ọrọ to fi sita, o sọ wipe oun ''darapọ mọ awọn obinrin ati ọdọ ninu ẹgbẹ oselu ADP nibi ifilọlẹ awọn ọmọ igbimọ alasẹ ẹgbẹ́ naa ni ijọba ibilẹ ariwa Abeokuta'' Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Josh Posh: Inú mi máa ń dùn láti kọrin fún àbúrò mi ní kékeré Ninu alaye to se nipa igbese toun gbe yii, Rinsola so pe fifun awọn obinrin ati ọdọ lanfaani lati kopa ninu oselu jẹ nnkan gbogi ti oun yan ladi-sọkan. ''ipinnu mi lati yan ADP ko sin lẹyin pe wọn ni ifarajin fun ọrọ obinrin ati ọdọ'' Bakanna lo tẹsiwaju ninu alaye rẹ pe, iye owo ti ẹgbẹ oselu ADP n gba fun fọọmu fifi erongba han lati dije fun ipo oselu, ko gunpa rara. ''Fun awọn to n dije ipo ile asofin nipinlẹ, ₦330,000.00 ni wọn n san, nigba ti awọn to n du ipo ile asoju sofin si n san N1,100,000'' O ni awọn oludije obinrin laanfani pe wọn ko ni san owo fọọmu. Bi APC ṣe pàdánù ọmọ MKO Abiọla Ọmọ ẹgbẹ oselu APC ni Rinsola jẹ tẹlẹ ti o si n ba olori ile asoju sofin agba labuja, Yakubu Dogara, sisẹ gẹgẹ bi oluranlọwọ pataki. Nigba ti afẹfẹ iyiẹgbẹ pada n fẹ loun naa kede pẹ oun ko se ẹgbẹ APC mọ. Ninu lẹta kan to kọ ranṣẹ si alaga wọọdu idibo rẹ, eyi to tẹ fi sọwọn si oju opo Twitter rẹ ni Rinsọla ti salaye pe igbesẹ ohun lati fi ẹgbẹ APC silẹ ko ṣẹyin ofin tuntun ti awọn oludari ẹgbẹ All Progressives Congress, APC, fi sita. O ni irinajo ọdun maarun pẹlu ẹgbẹ osẹlu naa jẹ eyi to kun fun ẹ̀ka ti ko ṣe e gbagbe. Bi o tilẹ jẹ wipe awọn kan n sọ lori ayelujara Twitter pe ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party, PDP, ni Rinsọla darapọ mọ, arabinrin naa ni oun ko ti darapọ mọ ẹgbẹ́ oṣelu kankan. Ati pe awọn nkan bi fifi aaye gba awọn obinrin ati ọ̀dọ́, to fi mọ iṣejọba awa-arawa l'abẹle, ni yoo sọ ẹgbẹ oṣelu ti oun yoo pada darapọ mọ. O ni ki awọn alaṣẹ ẹgbẹ oṣelu PDP ṣi fi ara balẹ naa. Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹ si: Ọdalẹ ni Babangida ati Abacha - Ọmọ Abiola 'IBB da Abiola lẹ́yìn tó búra pẹ̀lú Quran'",0,yoruba "Ìsimi àpàpàndodo là ńgbà, kàkà kí a parí lọ́dún nìí, ó tún di ọdún tó'mbọ̀. Háà! Ó mà ṣe o ☹ #ASUU #IfNotForAsuu #Nigeria",0,yoruba lòdì Ìjẹ̀. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba ìbàdandun ìlú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "Fayose gọ̀, ó fẹnu họra, Ọlọ́run á gbẹ̀san lára rẹ̀, àdàbí...- Bode George Igbe gbajare yi n gbẹnu Oshokomolẹ latari iṣẹlẹ to waye ni asekagba ipolongo idibo ẹgbẹ PDP ni Ondo t'awọn kan ti si fila lori rẹ. Gomina tẹlẹ rí ni ipinlẹ Ekiti to si tun jẹ agbaọjẹ ninu ẹgbẹ alatako ni Naijiria fi ọrọ yi sita loju opo Facebook. Agbẹnusọ rẹ Lere Olayinka lo buwọlu atejade yi to si ni Fayose ko ni yẹ ko ni gbo lati maa sọ ododo nigbakugba. Fayose sọrọ lori lẹta oloye Ọbasanjọ. Ko fi mọ ọ bẹẹ, Fayose tun naka abuku si agba oloselu PDP nii, Bode George, ati gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde pe awọn ni wọn de janduku to si fila lori oun nibi eto ipolongo idibo PDP l'Akure. Ninu alaye ti Fayose sọ nínú atejade rẹ,o ni igba toun n rin lọ si ori aaye t'awọn alejo wa ni janduku kan sadede sun mọ oun to si ṣi fila ori oun. ""Bí wọn ṣe yọ fila lori Bola Ige bi yẹn ni Ile Ife. Gbogbo wa la mọ ohun to t'ẹyin rẹ bo"" ""Nitori naa mi o ni fi ọwọ yẹpẹrẹ mu ọrọ yi"" Fayose salaye pe oun ti fi ọrọ naa to awọn agbofinro leti ati pe wọn gbọdọ wadii awọn to wa lẹyin oro ti o fi n ke. Lẹnu ọjọ mẹta yi, Gomina ipinlẹ Oyo Seyi Makinde ati Ayodele Fayose jijọ n tahun sí ara wọn lori didari ẹgbẹ oṣelu PDP. Ondo Elections 2020: Ọgọ́rùn-ún ọdún tí a máa lò lórí oyè l'Ondo, ẹ ó rí àrà - Ojon YPP Kí ló wà nídìí ìsọ̀rọ̀ǹgbèsì láàrin Makinde ati Fayose? Ẹ̀wọ̀n ni wàá gbẹ̀yìn sí, kò sí bóo ṣe dọ́gbọ́n tó - Seyi Makinde wa ègúná ọ̀rọ̀ lé Fayose Aawọ oṣelu to n ṣẹlẹ laarin awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party ni iha Guusu-Iwọ Oorun Naijiria eyi to jẹ awọn ilu Yoruba da bii pe o tun ti n gbona bii ogun bayii gẹgẹ bi itahunsira ni gbangba ṣe bẹ silẹ laarin gomina Oyo, Seyi Makinde ati gomina ipinlẹ Ekiti tẹlẹ, Ayodele Fayose. Eyi to tun ṣẹṣẹ jẹ tuntun laarin wọn ni igba ti gomina Makinde n fesi si abajade ẹsun ti ajọ to n ri si iwa jẹgudujẹra, EFCC fi kan Ayo Fayose ti Makinde ni ko si ohunkohun ti Fayose i baa ṣe lori ẹjọ yii, ẹwọn ni yoo lọ gbẹyin. Ẹsun mọkanla ni ajọ EFCC fi kan Fayose lati ọjọ kejilelogun oṣu kẹwa ọdun 2018 toun tu ile iṣẹ kan to n jẹ Spotless Investment Ltd. Fayose ni oun o jẹbi ẹsun naa ti wọn si ni beeli rẹ ni aadọta miliọnu naira pẹlu oniduro kan. Latẹnu ọkan lara awọn oluranlọwọ Seyi Makinde, Dare Adeleke ni o ti fesi lori ayelujara si ohun ti Lere Olayinka, agbẹnusọ Fayose sọ pe ""ati iwọ ati ọga rẹ to n sanwo fun ẹ, ẹwọn ni ipin yin, ko si bi ẹ ṣe fẹ yi idajọ naa to, ẹ o lọ sẹwọn"". Bi ẹ ba ranti, ọrọ laarin gomina Makinde ati awọn eekan PDP bii Fayose, Hon. Ladi Adebutu, Sẹnetọ Ademola Adeleke ati alaga ẹgbẹ PDP ni Eko, amojuẹrọ Deji Doherty ti n di fa ki n fa a tipẹ lorii tani yoo ṣakoso idari ẹgbẹ PDP nilẹ Yoruba. Awọn kan korajọ sẹyin Ayodele Fayose paapaa julọ awọn to wa ni Ekiti, Osun, Ogun ati Eko ti awọn ti Oyo ati Ondo gba sẹyin Seyi Makinde 'N500 dé fún gbogbo ọmọ tuntun lóṣooṣù bí mo bá di gómìnà Ondo - Adeleye AAC Àìgbọ́n àti àìmọ̀kanmọ̀kàn ló ń da Fayose láàmù, kò gba ẹnu rẹ̀ láti sọ̀rọ̀ sí mi - Bode George Oloye Olabode George, tii se asaaju kan ninu ẹgbẹ oselu PDP nipinlẹ Eko, ti fesi si oko ọrọ ti gomina ana nipinlẹ Ekiti, Ayodele Fayose sọ si. Saaju la ti kọkọ mu iroyin wa fun yin pe Ayodele Fayose ti sọ fun ẹgbẹ oselu PDP nipinlẹ Eko pe ayafi ti oloye Bode George ba yẹba ninu ẹgbẹ oselu naa, ni egbẹ PDP to le moke nipinlẹ Eko. Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ lati fesi si ohun ti Fayose sọ naa, Bode George ni aigbọn ati aimọ lo n se Fayose nitori ko yẹ ko jẹ oun lo yẹ ki Fayose ri fin. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Asaaju ẹgbẹ oselu PDP naa ni oun seranwọ fun Fayose lati moke ni igba meji gẹgẹ bii gomina ipinlẹ Ekiti, o si ya oun lẹnu pe o le pada ri oun fin. ""Se bi ti ẹgbẹ ni o, abi o muti yo, abi o mugbo yo, o ti pẹ ti Fayose ti maa n fi ẹnu rẹ yẹn sọ isọkusọ bii ọmọ ti wọn ko bii re, ti kii si se ọmọluabi. Ki lo kan Fayose gan pẹlu ipinlẹ Eko, Ekiti to ti wa gan, wahala to da silẹ nibẹ, a sẹsẹ n yanju rẹ ni."" Bode George ni Fayose ko bọwọ fun agba, ewu to si wa lori oun, kii se pe oun fi owo ra a, bẹẹ ni ko lọgbọn ori, Ọlọrun yoo si gba ẹsan lara Fayose, ayafi ti ko ba wa dọbalẹ ni ọọfisi mi lai mọye igba lati beere fun iranlọwọ. Bakan naa lo fikun pe, Fayose ko le wọ aarin ero ni Eko bi, sebi se lo gbe oku baba rẹ pamọ fun ọdun kan, eyi to fihan pe kii se ọmọ gidi. ""Wọn ko nile iwosan ti wọn ti n wo were, amọ awa ni nilu Eko nibi, a si mu Fayose lọ sibẹ pe ki wọn lọ yẹ ọpọlọ rẹ wo, ologun si ni emi, emi kii gba igba kugba, mo si kọja ẹni ti ọmọ kan maa yọ ẹnu si tabi fi tayin."" Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife ""Ti Fayose ba to bẹẹ, ko bọ si aarin wa nilu Eko, ko maa bọ, yoo ri ẹẹkẹ rẹ lai gbe digi, ọmọ ọdun melo lo wa nigba temi se gomina lọdọ wọn, awa maa tun kọ ni Eko, tori Fayose gọ, o si fi ẹnu họra, wọn ko si bi re."" Ẹgbẹ́ òṣèlú PDP, ẹ̀ka ìpínlẹ̀ Eko fún Fayose lọ́jọ́ méje láti bẹ àwọn adarí ẹgbẹ́ Ẹgbẹ́ òṣelú People's Democratic Party (PDP) ni ìpińlẹ Eko ti fún gómìnà àná ní ìpínlẹ̀ Ekiti Ayodele Fayose ni gbédéke ọjọ méje láti rawọ́ ẹ̀bẹ̀ sí àwọn àgbà ẹgbẹ́ PDP. Èyí wáye lẹ́yìn tí wọn ni Fayose sọ̀rọ̀ tó lé dá ẹgbẹ́ rú tó sì lè dá wàhalà sílẹ̀ láàrin àwọn ọmọ kéèkèé àti àgbà ẹgbẹ́. Agbẹnusọ ẹgbẹ́ PDP ni ìpínlẹ̀ Eko Taofik Gani sọ nínú àtẹjáde kan to fisíta pé Fayose sọ ọ̀rọ̀ àbùkù lásìkò ti Fayose ni òun n gba àwọn ọdọ ẹgbẹ́ níyànjú tó le mú kí àwọn ọdọ ẹgbẹ́ kọjú ìjà sí àwọn àgbà ẹgbẹ́ ní ìpínlẹ̀ Eko. Ojú àwọn èèyàn Ondo ti là pé ìnira ni ẹgbẹ́ APC mú wá - Jegede PDP Lásìkò ìfilọ́lẹ̀ ìgbìmọ̀ ìpolongo fún àtúndi ìbò sẹnatọ ni ẹkun ìlàoorùn ìpínlẹ̀ Eko to wáye ni ọjọ ìṣẹ́gun tó kọjá, níbi tó tí gba àwọn ọdọ́ nímọ̀ràn pé kí wọ̀n fún igbákejì alága ẹgbẹ́ nígbàkan rí olóyè Bode George ní ìsìnmi kúrò nínú ètò òṣèlú. Gẹ́gẹ́ bi àtẹ̀jáde tí akọ̀wé Fayose Lere Olayinka fi síta, to pe àkọlé rẹ ni "" PDP gbọdọ̀ sọ pé kí ìgbákejì alága ẹgbẹ́ PDP nígbàkan ri olóyè Bode George lọ fẹ̀yìntì kí ẹgbẹ́ báa le ní ìlọsíwájú kí wọ́n sì jáwé olúborí nínú ìdìbò tó n bọ ní ìpińlẹ̀ Eko"". Wo Adigun ọmọ ọdún mẹ́rin tí òwe Yorùbá àti ìtúmọ̀ gbó lẹ́nu rẹ̀ ju tìrẹ̀ lọ Agbẹnusọ ẹgbẹ́ òṣèlú PDP rọ Fayose láti ma jẹ́ àwòkọ́ṣe òdì fún àwọn ọdọ́ nínú ẹgbẹ́. Láti ọja ajé, ọjọ́ kejila, oṣù kẹwàá, ọdún 2020, Fayose kò ni láànfàni láti kópa nínú ètò kankan nínú ẹgbẹ́ PDP, àyàfi tó bá wá túbá lórí gbogbo àwọn ọ̀rọ̀ tó sọ. Bákan náà ni Gani rọ Fayose láti dẹkun àwọn ọrọ to le dá wàhálà sílẹ̀ láàrin àwọn àgbà ẹgbẹ́, tàbí èyíkéyìí tó lo dènà ìlọsíwájú ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ni ìhà Iwọ̀oorù-Gúúsù Naìjíríà.",0,yoruba "RT @user: Tí ìyà ńlá bá gbé'ni ṣán'lẹ̀, kéékèèké á máa gun orí ẹni. / When tripped by a major setback, one easily becomes vulne…",0,yoruba "Iku ọmọ Alagba Rueben Fasoranti ti da ọpọlọpọ awuyewuye Kí ló mú àwọn adarí Nàìjíríà tako ra wọn lórí ikú ọmọ alága ẹgbẹ́ Afenifere?silẹ paapaa julọ lori awọn wo gan an lo ṣiṣẹ laabi naa. Bi ọlọpaa ti n lọgun pe awọn agbebọn ni, wọn kii ṣe darandaran Fulani, lawọn apa kan araalu naa n pariwo pe rara oOoni Ile ife, Ààrẹ Gani Adams fárígá lórí ikú ọmọ Fasoranti, awọn Fulani lo ṣiṣẹ laabi yiiǸjẹ́ ẹ mọ ohun tí igbákejì ààrẹ Yemi Osinbajo sọ nílé bàbá Fasoranti . Amọṣa, dẹrẹba to wa ọkọ arabinrin naa lọjọ buruku eṣu gbomimu yii ba BBC News Yoruba sọrọ lori bi ọrọ ṣe ṣẹlẹ gan an.",0,yoruba mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa òkè: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba aláìì a yi da ti o nuni ti o pẹ jú nìlọ̀ ni ọ̀nà tí ẹ̀ọ́ kan máa ń gbé ìyẹ̀ alẹ́.,0,yoruba gbogbo àgbà yoòbá mojúbà ọmọdé mojúbà o ẹ jẹ́ kó yẹmí o,0,yoruba a ní nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba "Ọba lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba ojú òní. ti Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Bàbá lo tun se fi.,0,yoruba ijoba apapo fg ngbero isuna ntn fun,0,yoruba olùparapọ̀ ri pe nilo ayẹwo wey ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò.,0,yoruba "jíjí tí a jí lónìí, Ọlọ́run ọba ni. Nítorípé ojúmọ́ kan kìí mọ́ àyàfí àṣẹ Olódùmarè. #ekaaro",0,yoruba yíyẹ ní í yẹyẹlé rírọ̀ ní í rọ àdàbà lọ́rùn pẹ̀tẹ́pùtù ní í ṣadìẹ àba yíyẹ ni yóò máa yẹ mí rírọ̀ ni yóò máa rọ̀ mí lọ́rùn ọgbọ́n kò ní pin mọ́ mi nínú iyèè mi yóò máa là wàà ọ̀nààn mi kò ní nà mí iléè mi ò ní lé mi ilẹ̀ ọ̀gẹ́rẹ́ yóò máa rú fún mi tẹ̀,0,yoruba oruko mi ni adekunle folarin omo afolabi laati aagbole alaagba ni gbagura ilu abeokuta ile lisabi,0,yoruba "Yewájobí ṣe bí àwọn awo ti wí, ó sì bẹ̀rẹ̀ sí í bímọ, ó bẹ̀rẹ̀ sí ní gbé ọmọ ṣeré, ó finú ṣoyún, ó fẹ̀yìn gbọ́mọ pọ̀n. #Gelede #Yoruba",0,yoruba Nípa ojú ìdarí kọmpútà GNOME,0,yoruba Àyájọ́ Ọjọ́ Òmìnira ní Trinidad àti Tobago — àmọ́ ǹjẹ́ orílẹ̀ - èdè náà ní òmìnira bí ?,0,yoruba ọ̀gbẹni sodiq lawal jẹ́ ọkan nínú àwọn márùnún to yege jùlọ nínú ìdíje ẹ̀bùn ìwé kíkọ ẹgbẹ́ àtẹ́lẹwọ́ fún iṣẹ́ wọn tí àkọ́le rẹ̀ ń jẹ́ koowéè ń ké,0,yoruba ẹkọ́: ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba àsà tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba "Ìjọba àpapọ́ ní ẹgbẹ́ òsìsẹ́ tún bèrè fún àfikún owó osù fún àwọn tó ń gba owó osù tó ju 30,000 Naira tí wọn béré fún lọ. Alága àjọ tí ń rí sí owó oṣù, àti ipòwòwọlé, Olóyè Richard Egbule, lo sọ ọrọ yìí ni Abuja nígbà tí ó ń fi ọ̀rọ̀ j'omi toro oro pelu àwọn akọ ròyìn lọ́jọ́ ajé. Egbule ni Ìjọba àpapọ́ ní ẹgbẹ́ òsìsẹ́ tún bèrè fún àfikún owó osù fún àwọn tó ń gba owó osù tó ju 30,000 Naira tí wọn béré fún lọ. Kílò fa èdè àìyedè láàrin ìjọba àti àwọn ọmọ lẹ́yìn El-Zakzaky? ìjọba àpapò wa fikun wi pe ti awọn ba fikun owo bi ẹgbẹ osisẹ se beere rẹ, iye owo ti ijọba a ma a san fun owo osu.",0,yoruba "A ti ṣe ìtúmọ̀ àwọn ohun tí ó ní ṣe pẹ̀lú ààbò lórí ayélujára sí èdè Yorùbá, ẹ yẹ̀ ẹ́ wò lórí Ibùdó-ìtàkùn-àgbáyé ~>>> https://t.co/3aAtPUK3jL #EFF @user #l10n #Yoruba",0,yoruba "Baba Mimo Iwo Olorun Gbogbo Aye, Baba wa gbowa k'ale ma feran ara wa. Baba Mimo Ateriba si'iwo ju ite re, bo'ju wa ko saanu fun wa oo! Olorun! Olorun Agbayee!! Oluwa wa o, Eleda Gbogbo Eniyan!! 🎶🎧 by Beautiful Nubia #Music #Renaissance #Yoruba",0,yoruba RT @user: @user mo modupe O! Oosa oke oni gbagbe eyin naa ooo..Ase Ire O!,0,yoruba "lọ. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba àlùfáà ni iwa rere lojiji. Alàji lo tun se joko. Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "Awọn dokita lati ilẹ Amẹrika naa fikun wipe o seese ki igbẹ ọmọde jẹ ọna abayọ si gbogbo aarun ti n pa awọn eniyan lai to ọjọ. Iwadii ti awọn dokita onimọ lati ilẹ Amẹrika fi sita ninu akojọpọ iwe Scientific Reports fihan wipe kokoro aifojuri kan wa ninu igbẹ awọn ọmọde ti o le pese eroja ara kan ti wọn n pe ni 'probiotic' ti wọn nilo lati koju aisan sisanra ju ati arun jẹjẹrẹ. Ti eroja asaraloore probiotics ti wọn n fi si inu awọn ounjẹ ipapanu bii yogọọti gẹgẹbi eroja asaraloore ba wa ni ara eniyan, yoo seese fun ounjẹ lati da ni inu eniyan fun sise ara loore. 'Ògidì ọmọ Yorùbá ni mí, kò sí ọ̀rọ̀ tí n kò lè túmọ̀' Awọn dokita lati ilẹ Amẹrika naa fikun wipe o seese ki igbẹ ọmọde jẹ ọna abayọ si gbogbo aarun ti n pa awọn eniyan lai to ọjọ. 'Fífún ọkọ àti ọmọ l'ọ́yàn ń dènà jẹjẹrẹ ọyàn' O ti pẹ ti ariyanjiyan ti wa lori ẹni to ni ọyan aya obinrin laarin ọkọ rẹ ati ọmọ wọn. Diẹ lara awọn ọkunrin to ba BBC Yoruba sọrọ ninu fidio isalẹ yii ni ọkọ lo ni ọyan aya obinrin, pe ọmọ ti wọn bi kan ya a lo fun igba diẹ ni. Àwọn ọkùnrin sọ èrò wọn lórí àríyànjiyàn ẹni tó ni ọyàn obìnrin láàrin bàbá àti ọmọ. Ọjọ kinni, oṣu Kẹjọ si ọjọ keje ni wọn ya sọtọ lati polongo pe ki awọn obinrin maa fun awọn ọmọ wọn lọyan, o kere tan, oṣu mẹfa. Lẹyin eyi ni wọn to le fun iru ọmọ bẹẹ ni awọn ounjẹ aṣaraloore miran. Ajọ to n mojuto eto ilera l'agbaye, WHO, to fi mọ UNICEF, ni omi ọyan ni awọn eroja aṣaraloore fun awọn ọmọde. Onimọ nipa eto ilera, Abilekọ Grace Oluwatoye, sọ fun BBC Yoruba pe 'o yẹ ki obinrin fun ọmọ ni ọyan fun oṣu mẹfa akọkọ ti wọn ba bi'. Omi ọyan to kọkọ jade lara ọyan fun ọjọ mẹta akọkọ lẹyin ti iya ba bi mọ tan dara pupọ, nitori pe awọn eroja to wa ninu rẹ dara fun ilera ọmọ tuntun.' Àwọn obìnrin kan tilẹ̀ máà n ta omi ọyàn wọn fún àwọn ìyálọ́mọ́ tí kò le fún àwọn ọmọ wọn ní ọyàn O ni eyi yoo ṣe iranlọwọ fun idagbasoke ati ọjọ iwaju awọn ọmọ naa, ati pe fi fun ọmọ lọyan maa n mu ki ifẹ ati isopọ wa laarin iya ati ọmọ. Bakan naa lo rọ ijọba ati awọn agbanisiṣẹ lati ṣe awọn alakalẹ eto ninu eto isejọba ti yoo fun awọn obinrin ni anfaani lati fun awọn ọmọ wọn ni ọyan nikan ṣoṣo fun oṣu mẹfa akọkọ lai ni abula. Kin ni awọn onímọ̀ sọ lórí ki ọkunrin maa mu ọyan iyalọmọ? Abilekọ Oluwatoye ni ko si oun to buru ninu ki ọkọ mu ọyan aya iyawo rẹ lasiko to ba n t'ọmọ lọwọ, nitori ko si ewu kankan fun ọkunrin bẹẹ. O fi kun un pe eyi yoo tun mu ki ifẹ to wa laarin ọkọ ati aya l'agbara sii. Ati pe iwadi fihan pe aisan jẹjẹrẹ yoo jina si obinrin to ba n fun ọmọ ati ọkọ rẹ l'ọyan. O ni koda, omi ọyan obinrin dara ju ti ẹranko lọ. Sunday Ayẹni: Damilọla, aya ọmọ mi fìgbónára sọ mi sókùnkùn alẹ́",0,yoruba "lé Ìgbìmọ̀ Asòfin sọ pé àwọn ti gbé ìgbésẹ̀ lórí ikú àgùnbánirọ̀ tó yẹ kó gba ìwé ẹ̀rí ní ọjọ́bọ Sẹnatọ Atai Aidoko to gbe ọrọ naa kalẹ ni iwaju ile sọ wi pe arabinrin naa n lọ ile pẹlu awọn ọrẹ rẹ nigbati wọn yin ibọn lu u ni ilu Abuja, ti awọn ile iwosan si kọ lati tọju rẹ nitori ko si iwe lati ọdọ awọn ọlọpaa. Aarẹ Ile Asofin, Bukola Saraki ninu ọrọ rẹ sọ wi pe ""ẹmi ẹni kọọkan lo se pataki, paapaa awọn ọdọ ti wọn sẹẹsẹ n bẹrẹ igbe aye wọn. Ìjà ọlọ́pàá àti alápatà ni Bodija gbẹ̀mí Sulia aláìṣẹ̀ ni UCH Lẹyin naa ni ile igbimọ wa pasẹ fun igbimọ ile to n risi ọrọ ọdọ ati ere idaraya lati se iwadi kikun lori iku agunbanirọ naa, ki igbimo ile to n risi ọrọ̀ọ ilera lati se iwadi lori idi ti ile iwosan se kọ lati fun u ni itọju.",0,yoruba ènìyàn a yi yi ti o ní wúlò fún gbogbo.,0,yoruba "Ko din ni eeyan mẹjọ to kú, lasiko wọ́lù-kọlù to waye ni papa isere Olembe ti idije Afcon ti n waye ni Cameroon lọjọ Aje. Ọpọ eeyan lo tun farapa. Fidio kan safihan bi àwọn ololufẹ bọọlu ṣe n tiraka lati wọ papa isere ọhun to wa ni olu ilu Cameroon, Yaoundé. Gomina ẹkùn aarin gbungbun Cameroon, Naseri Paul Biya sọ fun ileeṣẹ iroyin AP News pe, o ṣe e ṣe ki oku pọ si i. Iroyin miran tun sọ pe awọn ọmọde kan dákú nitori wọ́lù-kọlù naa. Iwadii BBC salaye pe ẹgbẹrun lọna ọgọta eeyan ni papa isere naa le gba, sugbọn wọn din ku si ìdá ọgọrin nitori COVID-19. Ṣugbọn àwọn alamojuto ifẹsẹwọnsẹ to ba oniroyin sọ̀rọ̀, sọ pe eeyan bi ẹgbẹrun lọna aadọta lo n gbiyanju lati wọle sibi ifẹsẹwọnsẹ laarin Ileeṣẹ iroyin orile-ede Cameroon, sọ pe eeyan mejila lo ku, ti ogunlọgọ si ku. Àjọ bọọlu ni Afrika, CAF, sọ ninu atẹjade pe awọn ti n ṣe iwadii iṣẹlẹ naa. Bakan naa ni CAF sọ pe Ààrẹ àjọ naa, Ọmọwe Patrice Motsepe ti ran Akọwe Agba, Veron Mosengo-Omba, lọ si ileewosan lati lọ ṣe ibẹwo si awọn to farapa. Nick Cavell, olootu eto fun BBC Africa, to wa nibi ifẹsẹwọnsẹ ọhun sọ pe iroyin wọ́lù-kọlù naa ko de eti awọn to ti wa ninu papa naa, titi di asiko ti iroyin naa jade si ori ayelujara. Cavell sọ pe ni ṣe ni bata ati awọn nkan miran kún ẹnu ọna papa isere. Olutọju alaisan kan, Olinga Prudence sọ fun ileeṣẹ iroyin AP pe, awọn kan wa ni bebe ikú lara awọn to farapa. Iṣẹlẹ yii waye lẹyin ọjọ́ kan pere ti eeyan mẹrindinlogun kú nile igbafẹ LIVS Night club ni agbegbe Bastos nilu Yaoundé. Botilẹ jẹ pe wọ́lù-kọlù waye, ko da ifẹsẹwọnsẹ to n lọ laarin Cameroon ati Comoros duro. Ami ayo meji si odo ni Cameroon fun Comoros.",0,yoruba Gbogbo ọmọ Naija ẹ ti ṣorí ire o! Ẹ kí ààrẹ yín tí ń bọ̀ lọ́nà! Alákọ̀wé lorúkọ rẹ̀ ń jẹ́. Ẹ kú ojú lọ́nà!! #Alakowe2015,0,yoruba "Nígbà tí mo débẹ̀ , ó òkùnkùn ṣú bolẹ̀ , a sì fi alífábẹ́ẹ̀tì náà hàn mí ní àpẹẹrẹ ìmọ́lẹ̀ .",0,yoruba "Eeyan nikan ni a mọ pe arun naa n mu, a ko tii gbọ pe o mu ẹranko. Ṣugbọn ohun to jẹ kayeefi ni pe iroyin kan lati orilẹede China sọ pe ''ice cream'' fun lila ti lugbadi coronavirus. Iroyin naa sọ pe ayẹwo ti wọn ṣe nigba mẹta fihan pe ''ice cream'' naa ni arun covid-19 lara. Ajọ Tianjin to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede China ti bẹrẹ si ni wa awọn eeyan to ti fọwọ kan ''ice cream'' naa ti ileeṣẹ ounjẹ Tianjin Daqiaodao ṣe. Gbogbo ounjẹ ti ileeṣẹ naa ṣe jade ni ijọba ti fi ote le bayii lati igba ti iroyin ''ice cream'' to lugbadi covid-19 ti jade. Itaniji: Oluwo sọ ìtàn bí Orunmila ṣe jìyà nílùú Iwo àti ayọ̀ tó gbẹ̀yìn rẹ̀ torí sùúrù Dokita Stephen Griffin to jẹ onimọ nipa awọn kokoro arun ni fasiti Leeds sọ fawọn akọroyin pe ko si ifoya lori bo ya covid-19 le maa gba ibẹ ran kaakiri. Dokita Griffin ṣalaye pe o ṣeeṣe ko jẹ wi pe ara eeyan kan ni arun ọhun ti ran mọ ''ice cream.'' Ado Ekiti Blind Couple: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú Onimọ nipa kokoro arun naa sọ pe bo ya nitori ibi to tutu ti wọn ko ''ice cream'' naa si lo jẹ ki kokoro coronavirus si wa laaye di igba ti wọn ṣe ayẹwo. Amọ, o sọ pe ko si ewu lọri iṣẹlẹ naa, ati pe iti ọgẹdẹ lọrọ naa, ko too yọ ada si. Akomolede ati Aṣa: Mọ̀ síi nípa ìró afárànma àti agbárànmọ́ fáwẹ́ẹ̀lì Yorùbá Ni bayii, 1,662 awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ to ṣe ''ice cream'' naa sita ti wa ni iyasọtọ. Ijọba China ṣalaye pe 4,836 ''ice cream'' naa ni ileeṣẹ ọhun ṣe sita, amọ 2,089 ninu rẹ ni wọn ti so pa bayii.",0,yoruba "tí Bàbá fè joko, Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba "Aarẹ ẹgbẹ Yoruba kan to n ri si igbe alafia (Yoruba Welfare Group) ti funpe si gbogbo awọn tọrọ kan nilẹ Yoruba bayii. Wọn ni pe ki wọn wọn ma gbabọde dida wahala silẹ bo ṣe ti n ṣẹlẹ ni iha Ila-Oorun Ariwa ati Guusu-Iwọ Oorun Naijiria. Iṣoro aisi aabo ti n peleke sii lorilẹede Naijiria to si ti n fa oniruuru gburu sita lawujọ eyi ti awọn ọdọ si n kara bọ gidi gan. Ẹwẹ, aarẹ ẹgbẹ YWG, Comerade AbdulHakeem Adegoke Alawuje sọ fun awọn akọroyin ninu atẹjade kan. Wọn ni pe awọn gbọ iroyin pe iṣẹlẹ ipaniyan ati iwa idaluru to n lọ lọwọ lapaa Guusu - Ila Oorun paapaa julọ bi gbogbo oju ṣe n ri i ti eti n gbọ ọ nipa ipinlẹ Imo fẹ wọ ilẹ Yoruba. Eyi lo mu ki wọn funpe si ijjọba, awọn gomina apaa Guusu - Iwọ Oorun, awọn lọbalọba ati onikaluku araalu lati fọwọsowọpọ bẹgi dina iṣẹlẹ yii. Adegoke to jẹ ajagunfẹhinti ki awọn ọdọ nilọ pe ki wọ́n ma fi aaye gba ki agbara ọdọ gun wọn de ibi pe wọn o maa ""jo ile baba wọn"" labẹ didbọn pe awọn n jijagbara lodi si aidaa ofin. ""Sí awọn ọmọ wa ti ko ni imọ nipa ogun, o n gun wọn lati ni iriri ọkan ṣugbọn awa kan ti a ti foju ri ogun la ni iṣẹ lati fi oye ye wọn bo ti le wu ko le to. Oba Gbolahan Timson Shomolu Bariga ní 'Restructuring'ti bọ́ aṣọ kò bá Omọyẹ mọ́! O ni o daju pe awọn Yoruba ko gbaradi de ogun ""a ko si gbudọ gba ọkan laaye. Mo le ma mọ pupọ nipa awọn ẹya miran ṣugbọn mo mọ ti awọn lọbalọba ilẹ Yoruba"". O ni ni ọpọ igba ni a o bọwọ fun wọn ""bẹrẹ latori awọn agberaga ọmọkunrin ati obinrin wa. ""Bi a ba ri olori ilu fin, dandan ni ki ilana aṣa ilu naa wo lulẹ bẹẹ si ni gbogbo aṣa adayeba wa ko ni ni apọnle mọ loju ara ita. O ni ori ni awọn oriade jẹ si awọn oloṣelu gan. Amọ wọn o tẹle ilana to tọ mọ pẹlu bi wọn ṣe n pe awọn ajagun ibilẹ lai gba aṣẹ lọwọ awọn Oba ilu to yan wọn si iṣẹ. O ni pe nitori eyi awọn ajagun ibilẹ gan ti wa bẹrẹ si ni ṣe bii pe awọn kọja ofin nipa riri awọn ọba fin tori awọn oloṣelu ti la wọn loju si owo nla nla biliọnu latẹyinwa. 'Èmi ọmọ Ikorodu ọ̀ga, ọmọ aṣalẹ̀ jẹ́jẹ! Wo bí àwọn ọmọdé tó ""tuush"" yìí ṣe ń fi oríkì Yorùbá dábíra Adegoke wa kilọ pe ẹgbẹ Yoruba Welfare Group o ni kawọ gbera maa woran ki wọn si jẹ ki awọn ti ko mọ nkankan dana sun ile toripe ina ko tilẹ da ẹni to da a jo mọ. O ni apẹrẹ ni Nnamdi Kani to ni ""kii ṣe olugbe Naijiria amọ ti oun atawọn ẹgbẹ rẹ ti dana sun gbogbo iha Guusu - Ila Oorun tan yanyan"" o ni amọ wan o le ba odidi orilẹede jẹ, ẹkun tiwọn nikan naa ni wọn le ba jẹ"". Adebayo Murital David: Gbogbo iṣẹ́ tó ń múni là láyé wá láti ọpọlọ ni kìí ṣe agbára Alawuje wa rawọ ẹbẹ si awọn ọdọ Yoruba lati ṣọra pẹlu ibinu ki wọn parapọ lati dena irufẹ nkan to n ṣẹlẹ nilẹ Ibo bayii ko ma baa waye nilẹ Yoruba, ""ki wọn ma gba ki ilẹ wọn di ilẹ ija ogun"". Bakan naa, o gba awọn agbagba naa to n ti awọn ọda lẹyin lati maa da igboro ru ki wọn jawọ nibẹ wipe ilẹ Yoruba kii ṣe ibudo karakata fun ẹgbẹ tabi ọlọdani kankan. ""Ololufẹ alafia ni Yoruba a ko si gbudọ jẹ ki ipenija to wa lode lọwọlọwọ yii yi ọrọ daadaa naa pada"". Simple tricks to identify designer shoes: Ṣe ìwọ lè wọ bàtà #2 mílíọ̀nú",0,yoruba "Baba Adebanjọ ni iṣekupani ojojumọ ti pọju lorilẹede Naijiria, ni awọn ọdọ ṣe n dide lati gba ara wọn la. O ni awọn ọdọ ni ijọba n koju pẹlu aikaato eto akoso rẹ, nitori naa, wọn ko le e da wọn duro. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ''Ọjọ ti pẹ ta ti n pariwo ki ijọba ṣe atunto orilẹede Naijiria, amọ wọn kọ eti ikun si ọrọ wa. O yẹ ko ye ijọba pe o n fi ina si ibinu awọn ọdọ ni Naijiria nitori pe o kọ lati ṣe atunto orilẹede Naijiria. Kò sí ìgbà kankan tí Yorùbá jókòó pé ki Igboho lọ kéde ìyapa kúrò ní Nàíjíríà Ijọba yẹ ko fun awọn ẹkun to wa ni Naijiria laaye lati ṣakoso ohun ini wọn funra wọn ni'' Ẹya Igbo naa figbe ta pe awọn ko fẹ jiya lọwọ ọdaran darandaran mọ Bakan naa ni ẹgbẹ awọn ẹya igbo, Nigeria Patriotic Youth Against Corruption and transparency, ni awọn ko ni gba fun awọn Fulani darandaran lati wa si ilẹ awọn, ki wọn si ma a jẹ awọn eniyan wọn ni iya. Adari ẹgbẹ naa, Oloye Emmanuel Iwuayanwu ni awọn adari ni ilẹ igbo yoo dide lati gbogun ti ipaniyan awọn ẹbi ati ara awọn ni ilẹ Igbo, paapaa ni ipinlẹ Ebonyi. ''Nkan buburu lo n ṣẹlẹ ni Naijiria, o buru jai ki awon Fulani darandaran ma a pa eniyan kaakiri lai si pe wọn ti ọwọ ọmọ wọn bọ aṣọ.'' Cattle Ranching: Ẹ wo Fulani darandaran to tako àṣà dída màálù kiri lójú pópó ''Nibayii awọn ọdọ lati ipinlẹ mẹtadinlogun lorilẹede Naijiria ti kesi awọn darandaran to n paniyan, ki wọn kuro ni agbegbe naa ni kiakia lai wọ ẹyin.'' Bakan naa ni wọn kilọ fun ijọba lati jawọ igbeṣẹ fifi panpẹ mu awọn ọdọ to n ja fun ẹya wọn bii Alhaji Asari Dokubo, Sunday Igboho ati Nnamdi Kanu. Ọpọlọpọ awọn eniyan lo sọrọ tako iṣekupani to n waye ni Guusu orilẹede Naijiria lati ọwọ awọn afurasi Fulani darandaran. Afúrasí darandaran tó pa ènìyàn 15, jó ọ̀pọ̀ dúkìá ni Ebonyi ti bọ́ sí àhámọ́ ọlọ́pàá Gomina ipinlẹ Ebonyi, David Umahi ọwọ awọn ti tẹ awọn afurasi darandaran to ṣekọlu awọn ijọba ibilẹ bii mẹrin ni ipinlẹ naa. Gomina Umahi lo sọ ọrọ yii lasiko to ṣe abẹwọ si ibi ti iṣẹlẹ naa ti waye ni ijọba ibilẹ Nkalaha, Obegu, Umuhuali ati Amaezu. Umahi ni awọn marundinlogun lo ku ninu ikọlu naa. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ''A ti ri awọn to sekọlu si awọn eniyan ijọba ipinlẹ yii, ti a si ti ri awọn to ran wọn ni iṣẹ'' ''Mo si ti bẹrẹ si ni ba awn eniyan sọrọ ti iṣẹlẹ naa ṣe ijamba fun, ati ki awọn eniyan ma gbe ija ara wọn ja.'' ''Ibanujẹ ọkan lo jẹfun mi pẹlu iṣẹlẹ to waye ni Ebọnyi ati bi awọn darandaran to wa nmi agbegbe naa ṣe sa asala fun ẹmi wọn, ki awọn eniyan ma ba a pa wọn''. Gomina ipinlẹ Ebonyi ni ti iṣẹlẹ ikọlu awọn Fulani darandaran yii ba tẹsiwaju kaakiri orilẹede Naijiria, o le da ogun abẹle. Ẹni ti iṣẹlẹ naa ṣoju rẹ ni awọn agbegbọn naa kọlu pẹlu ikọ ati ada ti wọn si fi ọbẹ le awọn eniyan kuro nibẹ. O tun fikun wi pe wọn pa alfa ijọ Methodist to wa nibẹ, ti wọn si ko ọpọlọpọ dukia awọn eniyan lọ nibẹ. Amọ, ijọba bu ẹnu atẹ lu bi awọn eniyan ṣe fiyajẹ awọn afurasi ti wọn ri lagbagbe naa, jungle justice lai fi idi rẹ mulẹ pe awọn gan an lo ṣiṣẹ ibi ọhun. Gomina ipinlẹ Ebonyi, David Umahi ni iwadii ṣin tẹsiwaju lori iṣẹlẹ naa. Akwa Ibom state Attack: Àwọn agbébọn pa ọ̀pọ̀ ọlọ́pàá, ṣọ́jà, wọ́n tún jó ọ̀pọ̀ ọkọ̀ ní Akwa Ibom Nnkan ko fi gbogbo ara rọgbọ ni ijọba ibilẹ Essien Udim ni ipinlẹ Akwa Ibom, lẹyin ti awọn agbebọn kan lọ kọlu awọn ọkọ ọlọpaa atawọn ologun to n mojuto eto abo nibẹ. Awọn agbebọn naa ti wọn to aadọta ni iye ni wọn ni wọn n tako alaga ijọba ibilẹ naa, ti wọn si tipa bẹẹ kọlu awọn ọlọpaa ati ọmọ ogun ti wọn ko lọ si ibẹ lati pẹtu si awọ. Gẹgẹ bi iroyin ṣe sọ, ọga ọlọpaa kan ti orukọ rẹ n jẹ Benedict Okoh Ajide atawọn ọlọpaa miran ni awọn agbebọn naa pa ni owurọ ọjọ Iṣẹgun ọgbọn ọjọ oṣu kẹta ọdun 2021. Ohun ti BBC News gbọ nibẹ ni pe, awọn agbebọn naa jo ile ọga ọlọpaa, CSP Ajide, koda ọta ibọn ba eeyan kan to n kọja ls ni tirẹ to si gba ibẹ ku. Bakan naa ni wọn tun da ina sun awọn ọkọ Hilux kan, wọnṣe awọn ọlọpaa miran leṣe bi o tilẹ jẹ pe a ko lee sọ iye wọn. Bawo lo ṣe ṣẹlẹ ati pe ki lo fa sababi? Ni nnkan bii ọsẹ mẹrin sẹyin, awọn agbebọn kan kọlu agọ ọlọpaa kan ti wọn si da ina sun apakan agọ ọlọpaa naa titi kan awọn aloku ọkọ kan ti wọn wa kalẹ si ọgba agọ ọlọpaa naa. Ikọlu yii lo mu ki ijọba ipinlẹ Akwa Ibom fofin de lilo alupupu ọkada tabi kẹkẹ marwa nibẹ lọjọ kẹrindinlọgbọn oṣu kẹta ọdun 2021. Ijọba ibilẹ Essien Udim atawọn ijọba ibilẹ meji miran ni aṣẹ naa kan, laarin agogo mẹfa irọlẹ si meje aarọ lati dẹkun iwa ọdaran nibẹ. Ni bi a ṣe n sọrọ yii, ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Akwa Ibom ko tii sọ ohunkohun lori iṣẹlẹ naa.",0,yoruba agba ri pe nilo ayẹwo wey ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìwà: ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba ìran gíga tí wọ́n gé kúrú ìran ológo tí a pa ògo rẹ̀,0,yoruba kò lè fi àṣẹ lọ́lẹ̀ '%s',0,yoruba ẹ kú ojúmọ́ ire o ìsinmi ayọ̀ la ó máa ṣe o,0,yoruba "Ṣaaju ni iroyin kan ti kọkọ sọ pe Tinubu bẹ ipinlẹ naa wo laarọ Ọjọru, nibi to ti parọwa si awọn oniṣowo naa lati maṣe ba ọkan jẹ lori iṣẹlẹ ọhun. Ọpọ ọja lo jona ninu iṣẹlẹ naa, eyii to mu ki ijọba ipinlẹ ọhun gbe iwadii dide lati mọ ohun to ṣokunfa ina naa. Ẹwẹ, ọọfisi Aarẹ Naijiria ti sọ pe ko si ija kankan laarin Aarẹ Muhammadu Buhari ati adari gbogbogbo fun ẹgbẹ oṣelu APC, Aṣiwaju Bola Ahmed Tinubu. Ninu atẹjade kan ti agbẹnusọ fun Aarẹ Buhari, Garba Shehu fi lede, o ni irọ lasan ni awọn iroyin kan to sọ pe ija wa laarin Buhari ati Tinubu. Atẹjade naa ni ""ọọfisi Aarẹ fẹ fi da awọn eeyan loju pe ko si ija kankan laarin Bola Tinubu ati Aarẹ."" 'Pẹ̀lú gbogbo ìrìnàjò Dubai mi, ẹ̀sẹ̀ gígún ní Nàìjíríà láti pàdé èèyàn ńlá ńlá tó lè ra àwòrán wa ṣe pàtàkì' ""Alafo diẹ to wa laarin awọn mejeji ko ṣeyin pe Tinubu kii ṣe ọkan lara awọn alabaṣiṣẹ Aarẹ."" Gẹgẹ bo ṣe sọ, ahesọ ọrọ naa bẹrẹ lẹyin ti Tinubu ko ṣabẹwo si Aarẹ fun saa kan ṣugbọn eyii ko tumọ si pe ija wa laarin wọn. O ni Aarẹ Buhari ati ẹgbẹ APC n ṣiṣẹ takuntakun ki alaafia ati idagbasoke le wa ni Naijiria. O tẹsiwaju pe akitiyan Aarẹ Buhari lati gbogun ti iwa ajẹbanu yoo tẹsiwaju lai fi ti ahẹsọ ọrọ ti awọn madaru kan n gbe kiri ṣe. Shehu ni Aarẹ Buhari ati Bola Tinubu jẹ ọkan gboogi lara awọn oloṣelu ti awọn eeyan bu iyi fun ju ni Naijiria. O ni Tinubu jẹ òpó kan pataki to jẹ ki ẹgbẹ oṣelu APC di igi araba nla ni Naijiria, nitori naa, mimi kan ko le mi ibasẹpọ rẹ pẹlu Aarẹ. O pari rẹ pe bo tilẹ jẹ pe Tinubu kii ṣabẹwo si Aarẹ loorekoore, ibaṣepọ awọn mejeji dan mọran. Àwọn ọ̀rọ̀ Yorùbá kan wà tí ẹ kò lè lò pọ̀ mọ́ ara wọn, àwn ọ̀rọ̀ tẹ́ẹ lè fi rọ́pò rèé",0,yoruba ọ̀run dídì. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba "Fún gbogbo ìgbésẹ̀ rẹ lọ́dún tí ń bọ̀, á dára kí o ro gbogbo rẹ̀ dáadáa. Èrò lọbẹ̀ẹ gbẹ̀gìrì 🤔 https://t.co/al2UFfODfa",0,yoruba aṣà. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé.,0,yoruba ọlọ́un sì wípé kíyè síi mo fi ewéko gbogbo tó wà lórí ilẹ̀,0,yoruba "dídì. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn aláìì lẹ̀.,0,yoruba "Wakati melo kan sẹyin ni wọn fi sita gẹgẹ bii pipe akiyesi ẹgbẹ oṣelu to wa lori alefa lọwọlọwọ ni Naijiria, All Progressives Congress si ikede wọn pe awọn ti n ro ẹni ti yoo jẹ oludije to n bọ. Ẹgbẹ oṣelu PDP ni awọn n fi to aarẹ Buhari atawọn adari ẹgbẹ oṣelu APC leti wi pe awọn Naijiria ti tẹsiwaju ninu irinajo wọn kọja ki wọn maa ronu ọrọ APC. Awọn si ti n pinu ẹni ti yoo gba eku ida iṣejọba ni ọdun 2020 fun ẹgbẹ oṣelu PDP lati mu apapọ ireti wọn ṣẹ gẹgẹ bi ẹgbẹ lati tun orilẹede yii kọ. Mo funra sí 'Swimming Pool' tí ọkọ àti àwọn ọmọ mi rì sí - Olubunmi Diya Àlùfáà ìjọ Redeem àti ọmọ rẹ̀ méjì kú sílé ìgbafẹ́ kan lásìkò Kérésì Ìdí tí mo fi gún olólùfẹ́ mi tẹ́lẹ̀ pa - Jacinta Igboke Ìjọba korò ojú sí bí Islamic State ṣe bẹ́ àwọn Kristiẹni mẹ́wàá lórí ní Bornu Orí yọ èèyàn mẹ́ta nínú ilé tí ọkọ̀ bàálù dédé já wọ̀ Wọn jẹ ko di mimọ pe dajudaju itan ti fi han pe ati APC ati iṣejọba rẹ, ko ṣee ma ni ni wọn ṣugbọn pe wọn ti de opin irinajo wọn bayii. Wọn ta abuku ba iṣejọba ẹgbẹ oṣelu APC pe pẹlu iroyin ti oniruuru ẹgbẹ ilẹ okere to fi mọ United States Department of State kọ ṣafihan iwa ipa lasiko idibo, dida ibo ru, didi awọn araalu lọwọ ẹtọ wọn ati bẹẹ bẹẹ lọ. Wọn fi ọpọlọpọ nkan to ṣẹlẹ lasiko idibo ipinlẹ Bayelsa ati Kogi ṣe apẹẹrẹ. Yàjóyàjó: Èsì ìdìbò Kogi tó gbé Yahaya Bello wọlé rèé Ẹgbẹ́ òṣèlú AA kò gbọdọ̀ kópa nínú ìdìbò gómìnà ní Kogi, Bayelsa - Ilé ẹjọ́ Ohun tawọn eeyan Kogi n sọ saaju idibo Gomina Ẹwẹ, bi PDP ṣe fi igboya kọ ikede wọn yii sita ni awọn ọmọ Naijiria ti ya bo wọn lati fesi. Bi awọn kan ṣe ni paaga, ki PDP da ọrọ ti wọn sọ pada pe ki wọn ye yin ara wọn tabi tabuku ba ẹgbẹ APC bẹẹ lawọn to fọwọ si ohun ti wọn sọ naa n kan sara si wọn. Kogi vs Bayelsa: Primate Ayodele sọ àsọtẹ́lẹ̀",0,yoruba agba a yi yi ti o nuni ti o nuni ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo.,0,yoruba "Gbajugbaja oṣere tiata Yoruba, Ibrahim Chatta ti sọ pe aye ti su oun. Chatta lo kede bẹẹ ninu atẹjade kan to fi lede loju opo Instagram rẹ. Gẹgẹ bii ohun ti gbajumọ oṣere naa sọ, o ni o ti to nnkan bii ọjọ melokan ti oun ti gbe ninu ibanujẹ. O ni ""Ọlọrun jare, o ti ṣe diẹ ti mo ti n gbe pẹlu ibanujẹ ṣugbọn mo n dibọn bii pe gbogbo nnklan n lọ dede fun mi."" ""Lọwọ yii, aye ti su mi, Ọlọrun jọọ, gba mi la."" Ọpọ awọn akẹgbẹ rẹ nidi iṣẹ tiata lo ti bẹrẹ si n fi adura ranṣẹ si loju opo Instagram naa lẹyin to fi ọrọ naa lede tan. Bakan naa ni ọpọ awọn ololufe rẹ mii ti n gba niyanju lati tu ninu. Bi awọn kan ṣe fi adura ranṣẹ ni awọn mii fi ọrọ iyanju sọwọ si, ti awọn mii pẹlu n sọ pe ki gbajunmọ oṣere naa ma mikan nitori ko si iṣoro ti Ọlọrun ko le yanju rẹ. Wayi o, ọpọ awọn ololufẹ oṣere naa lo ti n woye eredi to ṣe fi irufẹ ọrọ bẹẹ sita lori ayelujara. Ibrahim Chatta jẹ ọkan pataki lara awọn oṣere tiata Yoruba to dantọ ti ko si ipa ti ko le ko. To ba jẹ ni ti ere ṣiṣe ni, Ibrahim Chatta le ṣe bii ọdọ langba, arugbo, babalawo, oniṣegun tabiu afaa. Adura wa nip e ki Ọlọrun tu ninu, ko sib a yanju ohunkohun to ba n la kọja.",0,yoruba ojú òní. ti Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba Àkójú ọ̀rọ̀ yi kún fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde sí ara ilẹ̀. (Item 124),0,yoruba yi ti o nuni ti o nuni ti o nuni ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọmọ lo ni ẹ̀ká àwẹ eyti o gbe lori iwa rere.,0,yoruba "Ọdaran tó wà lẹ́wọ̀n tún wóke $100miílíọnu níta-EFCC Nínú ọgba ẹwọn lo ti ń ni ajọsẹpọ pẹ̀lú àwọn aráa rẹ̀ to kù nita pàápà jùlọ àwọn ti àjọ EFCC ń ṣewadiìí wọn fún kíkó owó ìlú pamọ lọ́nà àìtọ. 'Lóṣù mẹ́ta sẹ́yìn, mò ń wa ọkọ̀ taasín, ṣùgbọ́n wọ́n sọ mí di afọ́jú lọ́san gangan' Bawo ní Aroke ṣe tún le hùwà ọdaran láti inú ọgbà Ẹwọn Ajọ EFCC sàlàyé pé ìwádìí fi han pé lòdi si òfin to gbe ọgbà ẹwọn ró o ní ànfani sí ẹ̀rọ ayelujara àti ẹrọ iléwọ nínú ọgbà ẹwọn to yẹ ti maa ṣẹwọn rẹ. Wọn ni òun to tún wá yani lẹ́nu jùlọ ni pe Aroke lọ fun ìtọjú ara rẹ ni ilé ìwòsàn àwọn ọlọpàá ní Falomo nilú Eko fun àisan kan. Láti ile ìwòsàn yìí ni o ti maa ń ló si ilé ìtura nibi tí o ti n ri ìyàwọ àti àwọn ọmọ rẹ̀ méjí, nígba miran a tún maa lọ fún awọn ayẹyẹ to ba ni. Bakan náà lo n lo orúkọ ti kìí jẹ Akinwumi Sorinmade, lati sí àpò ikówópamọ meji ni First Bank àti Guaratee Trust Bank (GTB), o ra oun ini si Fountain Spring Estate ni Lekki lọdun 2018 ni mílíọnù mejilélógun àti Lexus RX 350 fún iyawo rẹ̀ Maria Jennifer Aroke. Ọdaran náà ni asẹ ǹkan ti ìyàwo rẹ̀ fi n gbowo ni Banki lọ́wọ́ nínú ọgbà ẹwọn to n lo lati rà tàbi ta bo ṣe wù ú nínú ọgbà ẹwọn to wá. Wọn tun sàlàye pé lasìkò ti ìgbẹ́jọ rẹ̀ ń lọ lọdun 2015 ni Aroke ra ilé oni yàra mẹrin ni Plot 12, Deji Fadoju òpópònà, Megamounds Estate Lekki County Homes , Lekki ní mílíọnù N48. Ọ̀daràn tó wà lẹ́wọ̀n tún wọ́'ke $100miílíọnu - EFCC Ọdaran tó wà lẹ́wọ̀n tún wóke $100miílíọnu níta-EFCC Ajọ to ń gbógun ti ìwà jẹgúdújẹra ní orílẹ̀èdè Naijiria (EFCC) ní àwọn tí rí àsírí Hope Olusegun Aroke tí wọ́n jù sí ẹwọ̀n ọdún mẹ́rìnlélógun fún ìwà ọdàràn gbájuẹ̀ orí ayélujára pé o tún ni ibánisọrọ kíkún pẹ̀lú àwọn ọdàran mìíràn ti wọ́n si n ṣe ìwádiìí wọ́n lọ́wọ́. EFCC ni àwọn ń ṣe ìwádìí wọ́n fún oníruuru ìwà ọdaran ori ayelujára àti kíko owó pamọ lọ́nà àìtọ́, àti pé ìwádìí fi han pé Olusegun Aroke lo ṣe agbódegbà fún olé ori ayelujara tó tó ọgọ́rún kan mílìọnù dọ́là bi o ṣe n ṣẹ̀wọ̀n rẹ̀ lọ́wọ́. Kogi vs Bayelsa: Primate Ayodele sọ àsọtẹ́lẹ̀ Adajọ Lateefa Okunnu ti ilé ẹjọ giga ìlú Eko to wà ni Ikéja lo dájọ rẹ ninu osù kini ọdun 2016 láti ṣẹ̀wọ̀n ọdun mẹ́rìlélógun fun gbájuẹ̀ ori ayélujára lórí owó mílíọnù márundinlọ́gbọ̀n. Akẹ́kọ̀ọ́ fasiti kan ni Malaysia ni Olusegun ki wọ́n tó mú u, ṣùgbọ́n kò fi ìgbà kankan simi iṣẹ́ gbájuẹ, lẹ́wọ́n gan ko dáduró láti tẹsíwájú iṣẹ́ gbájúẹ̀ rẹ to n ṣe. 'Lóṣù mẹ́ta sẹ́yìn, mò ń wa ọkọ̀ taasín, ṣùgbọ́n wọ́n sọ mí di afọ́jú lọ́san gangan'",0,yoruba "Bákan náà ni oyè Alápini àti Ọlọ́jẹ̀, ẹni tí ò bá mọ t'inú t'ìta orò ò lè e jẹ oyèe wọnnì. Irọ́ àti èké l'ó b'ayé jẹ́. #EseBoSeYe #Brazil",0,yoruba "Evangelist Yinka Alaṣeyori ti fi idunnu rẹ han lori bi Woli rẹ, Josua Iginla ṣe fi ọkọ bọgini ta a lọrẹ. Alaṣeyori naa lo lọ kọrin ni ile ijọsin wọn to wa ni ilku Abuja ti wọn pe ni Champions International, lorilẹede Naijiria. Alaṣẹyọri lasiko to n fi idunnu rẹ han bẹrẹ ibeere wi pe tani Woli rẹ, nibo ni ile ijọsin rẹ, to si gbadura fun woli rẹ naa. ''E wo ni ki a lọ minister, ki a gba honourarium to lamilaaka, ki wọn tun fi ọkọ bọgini, mọto ẹlẹṣẹ mẹrin ta wa lọọrẹ.?'' Bakan naa lo bẹrẹ si ni kọ orin lati fi idunnu rẹ han pe aanu ni oun ri gba. Alaṣeyori ni igba akọkọ ni yii ti oun yoo ri Woli Joshua Iginla, ti oun si lọ si ile ijọsin rẹ. O ni ko sọ wi pe ki oun polongo ore to ṣe fun oun, amọ lati fi idunnu oun han ni oun ṣe gbe si ori ẹr ayelujara wi pe aanu ni oun ri gba. Ko pẹ ti olorin ẹmi ,Yinka Alaseyori di ilumọka lẹyin ti gbas gbos waye ni aarin rẹ ati olorin ẹmi, Tope Alabi to sọrọ orin rẹ, Oniduromi, to si ni pe ko tọ ki o pe Ọlọrun ni ""Oniduro Mi"". Amọ awọn ọmọ Naijiria faraya, ti wọn si sọrọ kubakugbe si Tope Alabi wi pe ko tọ si lati tabuku. Lẹyin naa ni Adeyinka Alaseyori kọkọ ṣebi ẹni ti ko fẹ mẹnu ba ọrọ yii rara lati igba to ti ṣẹlẹ, amọ ni ibi ti o ti n ṣe isin orin iyin lati ṣaami ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ lo ti bẹ gbogbo awọn eeyan lori ọrọ yii. Lo ba tun fi adura bọ ẹnu fun gbogbo awọn to n ṣe iṣẹ to jẹ ọna to tọ pe: ""gbogbo ẹyin tẹ n ṣe iṣẹ ọna to tọ to n mu ounjẹ wa sori tabili yin, ẹ o maa lowo sii ni"".",0,yoruba "Barcelona vs Osasuna: Real Madrid gbadé ògo La Liga, Messi ní Barcelona ò lè ta pútú mọ́",0,yoruba "tí Ọmọ fè se, Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba RT @user: @user ẹ kú ọjọ́ ibí ayọ̀ òní o! Ẹ̀mí yín yóò ṣe ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọdún síi láyọ̀ àti làlàáfíà! Ẹ jayé orí yín lọ...ẹ ...,0,yoruba "Iyawo aarẹ orilẹede Naijiria ti ṣalaye bo ṣe mori bọ lọwọ ọkọ baalu to ri idamu loju ofurufu lasiko to n rinrinajo pada bọ wale lati ilẹ United Arab Emirates (UAE). Arabinrin Aisha Buhari ni oun rinrinajo lọ si orilẹede naa lati lọ fun itọju to so pada wale pẹlu ọkọ ofurufu ileeṣẹ ogun ofurufu Naijiria. ""Mo fi asiko yii dupẹ lọwọ gbogbo ọmọ Naijiria fun adura ati ọrọ ikini wọn nigba ti mo lọ fun itọju. Ara mi ti ya bayii mo si ti pada bọ sipo bẹẹni mo ti dari wale si Naijiria"" End of Twitter post, 1 Ko ye iru aisan pato to ba aya aarẹ kuro ni Naijiria ṣugbọn ko ba a pada wale gẹgẹ bo ṣe sọ. Ẹwẹ, o ni ""loju na wa pada, ọkọ baalu awọn ọmọ ogun ofurufu ri idamu nla ninu ofurufu ṣugbọn awakọ atawọn oṣiṣẹ inu baalu naa ṣe iṣẹ takun takun lati da a pada sọna rẹ"". Aisha gboriyin fun igboya ti awakọ naa atawọn oṣiṣẹ toku ni si iṣẹ wọn. Lootọ, Aisha Buhari lọ Dubai Iroyin to n ja rayin-rayin lori ayelujara ni wi pe iyawo aarẹ orilẹede Naijiria ti rinrinajo lọ si Dubai ni orilẹede United Arab Emirate fun idi pato ti a ko mọ. Awọn iroyin kan tilẹ n sọ pe bi awọn ṣe gbọ ọ, ọrun lo n dun arabinrin Aisha ṣugbọn iroyin naa sọ pe awọn apẹrẹ ṣaa han pe tori ilera rẹ ni. Ọpọlọpọ ọmọ Naijiria lo ti fọn si oju opo Twitter lati sọ ero wọn nipa irinajo ti a gbọ pe iyawo aarẹ lọ yii. Igba ti a ri iyawo aarẹ kẹyin ni ita gbangba ni asiko adura ọdun Eid-el-Kabir pẹlu awọn idile rẹ nile Aso Villa nilu Abuja. Awọn iroyin mii ni lẹyin ọdun Sallah lọsẹ to kọja ni wọn gbe iyawo aarẹ kuro ni Naijiria lẹyin to n kerora ọrun didun lati bi ọsẹ meji to bere fun ki wọn gbe oun lọ oke okun. Èèyàn mẹ́tàdínláàdọ́fà ló móríbọ́ lọ́wọ́ Covid-19, 443 míì tún lùgbàdì rẹ̀ lọ́jọ́ Ẹtì Èèyàn 16 kú lẹ́yìn tí bàálù Air India já lulẹ̀ , tó sì kán sí méjì ní Kerala Ìtàn ayé Shina Rambo, adigunjale tó fi oyún 27 gún ọṣẹ Ohun tẹ́ẹ gbúdọ mọ nípa kókó orí ọyàn yín lásìkò fífọ́mọlọ́yàn Kí ló mú Aisha Buhari figbe bẹnu pé kí Ọ̀gá Ọlọ́pàá tú àwọn ẹ̀sọ́ rẹ̀ sílẹ̀? Ọrọ miran tun ti n rugbo bọ nidile aarẹ orileede Naijiria Muhammadu Buhari pẹlu bi iyawo aarẹ Aisha Buhari ti se ke gbajare si ọga ọlọpaa lati tu awọn ẹsọ oun silẹ ki wọn ma ba lugbadi Covid-19 lọdọ wọn. Aisha fi ọrọ yi sita lọjọ Eti si oju opo Twitter nibi to ti sọ awọn ọrọ pe ko yẹ ki ẹnikankan kọja ofin ti ijọba gbe kalẹ nipa irina lasiko Covid-19 . Aisha ni ẹnikẹni to ba tasẹ agẹrẹ si ofin yii gbọdọ lọ si iyasọtọ ọlọjọ mẹrinla lati le mọ boya o ko arun naa tabi ko ni. O pari ọrọ rẹ pe ki ọga ọlọpaa tu awọn ẹsọ oun ti wọn mu sọdọ silẹ ki wọn ma ba ko Covid-19. Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀ Ta lẹni ti o tapa si ofin bawo lo si sẹ kan awọn ẹsọ Aisha Buhari? Ninu ọrọ ti Aisha Buhari sọ, ko darukọ ẹni kankan pe o tapa si ofin ma rina lasiko Covid 19. Sugbọn o jọ gate ko jọ gate, awọn ileesẹ iroyin Naijiria kan sọ pe ọrọ yii ko sẹyin bi ọkan lara awọn amugbalẹgbẹ aarẹ Buhari kan ti se dari si Aso Rock lati irinajo si ipinlẹ miran ni Naijiria. Gẹgẹ bi wọn ti se sọ, awọn ẹsọ Aisha Buhari ko jẹ ki amugbalẹgbẹ yi wọ Aso Rock nitori pe wọn ni o seese ki o ti ko Covid-19 lati ibi to ti n bọ. Amugbalẹgbẹ yii la gbọ pe o fi ibinu pe olori awọn alaabo iyẹn CSO ti o si ni ko fi awọn ẹsọ iyawo aarẹ to da lọna si ahamọ. O seese ki o jẹ idi ree ti Aisha Buhari fi n lọgun sugbọn a ko ti ridi ọrọ yi fi mulẹ. June 12:Àwọn tó wà ní ìjọba Baba mi ní kò lu owó ìlú ní póńpó- Ọmọ Abacha Ileesẹ ọlọpaa Naijiria naa ko ti fesi boya lootọ lawọn ẹsọ iyawo aarẹ wọn wa lahamọ. Awọn ọmọ Naijiria ni imọtaraẹni lo n damu Aisha Buhari Kete ti Aisha Buhari fi ọrọ yi sita loju opo Twitter lawọn eeyan yabo oju opo rẹ ti wọn si bẹrẹ si ni fesi. Ọpọ ko tilẹ beere ohun ti o mu ki Aisha Buhari ke gbajare si ọga ọlọpaa. Ninu ero wọn, Aisha Buhari ko tori awọn eeyan sọrọ nipa titẹle ilana ijọba lasiko Covid-19 yi bi kii se pe eeyan kan tun ti fọwọ tẹ ẹtọ rẹ mọle ni Awọn kan tilẹ n beere pe se ko ni nọmba ọga ọlọpaa ni abi ki lo wa de to fi n damu awọn loju opo Twitter Ninu ero awọn ẹlomiran, wọn ni se ko yẹ ki iyawo aarẹ da si awọn ọrọ miran to n jẹ Naijiria logun lasiko yi bi ipaniyan ati ijingbe to n waye lawọn ipinlẹ kaakiri Naijiria. Buhari yóò báwọn ọmọ Nàìjíríà sọ̀rọ̀ lọ́la 'June 12' tí ṣe àyájọ́ ìjọba àwarawa Aarẹ orillẹede Naijiria, Muhammadu Buhari yoo bawọn eeyan sọrọ lọjọ Ẹti, ọjọ kejila oṣu to ti di ayajọ ijọba awarawa bayii. Gẹgẹ bi atẹjade ti oludamọran pataki si aarẹ, Femi Adesina fi sita, aago meje aarọ ọjọ Ẹti ni Buhari yoo bawọn ọmọ Naijiria sọrọ. Ijọba rọ awọn ileeṣẹ redio ati amohunmaworan to fi mọ awọn ileeṣẹ iroyin mii pe ki wọn darapọ mọ ileeṣẹ tẹlifisan ijọba apapọ, NTA lati le ṣafihan ọrọ fawọn eeyan. Ọjọ kejila oṣu kẹfa ọdun 1993 lawọn ọmọ Naijiria dibo aarẹ ninu eyi ti MKO Abiola ti ẹgbẹ SDP ti waako pẹlu Alhaji Bashir Tofa ti ẹgbẹ NRC. Abiola lo jawe olubori ibo naa, ṣugbọn Ọgagun fẹyinti Ibrahim Babangida wọgile esi idibo naa eleyi to da rogbodiyan silẹ kaakiri Naijiria nigba naa. Ti ẹ ko ba gbagbe, lọdun 2018 ni Aarẹ Buhari kede ''June 12'' gẹgẹ ayajọ ọjọ ijọba awarawa dipo ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu karun ti ijọba ologun gbejọba fun alagbada ti ijọba kede tẹlẹ.",0,yoruba Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó ṣe pàtàkì. (Item 171),0,yoruba lojiji. Ọba lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ àti ìbi tí wọn wà.,0,yoruba "NBC ni ileesẹ igbohun-safẹfẹ Ekiti n hu awọn iwa to tako ofin isẹ igbohunsafẹfẹ. Ikọ iroyin BBC to wa ni ipinlẹ́ Ekiti ni, ajọ NBC pasẹ pe ki wọn ti ileesẹ igbohun-safẹfẹ naa pa nitori pe o n hu awọn iwa to tako ofin isẹ igbohunsafẹfẹ. Ninu atẹjade kan ti ajọ naa fi sita ni alẹ ọjọ abamẹta ni eyi ti jẹyọ. Ajọ̀ to n ri si eto igbohunsafẹfẹ lorilẹ-ede Naijiria ni, bi gomina ipinlẹ Ekiti, Ayọdele Fayose se n kede awọn esi ibo ti ajọ eleto idibo ko fọwọ si, lo mu ki oun gbe igbesẹ naa. Ajọ̀ NBC ni ileesẹ igbohunsafẹf Ekiti yoo si wa ni titi pa fun igba diẹ na. Bakan naa ni NBC salaye pe, Fayose tun bọ sori afẹfẹ ileesẹ agbohunsafẹfẹ ipinlẹ Ekiti lati maa sọrọ abuku nipa ajọ eleto idibo ilẹ wa, Inec, ileesẹ ọlọpaa ati awọn osisẹ ọtẹlẹmuyẹ. Ajọ̀ NBC ni ileesẹ igbohunsafẹfẹ Ekiti yoo si wa ni titi pa fun igba diẹ na.",0,yoruba "RT @user: e daagba, e fowo p'a ewu, isu oma a jina fun yin je. Eku ase oni Oo°˚˚˚°! @user @user @user @user…",0,yoruba "Ìyá lo ni ìgbà mi owó àkokò, Ìyá lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé.",0,yoruba "Sẹnẹtọ Dino Melaye Adajọ Yusuf Halilu gba ẹbẹ agbẹjọro rẹ, Mike Ozekhome, wọle ninu idajọ kan to gbekalẹ lọjọ Ẹti. Adajọ ni ki wọ̀n gba oniduro Melaye nitori ailera rẹ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Moses Melaye: Dino Melaye sùn ìta gbangba mọ́jú níléesẹ́ DSS Amọ ṣa, Adajọ naa ni Melaye gbọdọ mu oniduro mẹta wa sile ẹjọ, ki igbesẹ naa to o le fidimulẹ. Ọjọ kẹrin, oṣu Kinini ọdun 2018 ni Melaye jọwọ ara rẹ fun awọn agbofinro, lẹyin bi ọsẹ kan ti wọn ti yi ile rẹ, to wa niluu Abuja,po. Wọn fi ẹsun kan Dino pe, o lọwọ si bi awọ̀n kan ṣe yinbọn mọ ọlọpaa kan lọjọ kọkandinlogun, oṣu Keje ọdun 2018.",0,yoruba "Fayose ni kawọn osisẹ bi ijọba apapọ ohun ti wọn n fi owo se Fayoṣe kédè ọrọ náà lójú òpó Twitter re lásìkò ayajọ ọjọ oṣiṣẹ lorílè-èdè Nàìjíríà. End of Twitter post, 1 Ọ wa kesi awọn olórí ẹgbẹ òṣìṣẹ́ láti máṣe kaare nipa bibi ìjọba àpapọ̀ lori ohun ti wọn n fí ọrọ ìlú ṣe. ""Lai se bẹẹ, òpó ìpínlè ní kò ní ríbi ṣe òun tó yẹ"" O ni fún àpẹrẹ, ''dollar méjìlelogójì ní gbedeke iye owó èpo robi ti won lò fún ètò ìṣúná lọdun yi ṣugbọn ni báyìí ti owo èpo tí di aadọrin dollar, nse ni won tun kọ̀ láti sàn gbogbo owo to wole sí akoto apapo ti eyi si lòdì sí àṣẹ ilé ẹjọ to ga julo lorílèèdè yìí .'' Fayoṣe tun dupe lówó àwọn oṣiṣẹ fún àtìlẹ́yìn wọn ati wí pé, bi kìí bá ṣe tí wọn, òun ko ba ti jáwé olúborí nínú ìdìbò to gbe oun padà sípò.",0,yoruba "Ilu Abuja ni ọkọ afurufu to gbẹ abẹrẹ ajẹsara naa balẹ si, awọn eleto ilera si wa nibẹ lati ri wipe gbogbo rẹ lọ daradara. Nibayii, Ijọba ti ni awọn elto ilera ni yoo kọkọ gba abẹrẹ ajẹsara naa. Ti awọn oloṣelu yoo si bẹrẹ si ni gba lati Ọjọ Ajẹ, ọṣẹ too n bọ. O ti le ni ẹgbẹrun eniyan ti aarun Coronavirus ti mu ẹmi wọn lọ lorilẹede Naijiria. Wo alakalẹ lati pin abẹrẹ ajẹsara Covid-19 Ni bayii ti ijọba apapọ ti n reti abẹrẹ ajẹsara Covid-19 ni Naijiria, ọpọ eeyan lo ti n woye bi wọn ṣe le ri abẹrẹ naa gba, ati ibi ti wọ ti le gbaa. Ṣaaju ni minista eto ilera, Ọlọruninbẹ Mamora ti kọkọ kede pe awọn oṣiṣẹ eto ilera to n ṣetọju awọn to ti lugbadi arun na ni yoo kọkọ gba abẹrẹ ọhun. Ẹwẹ, ileeṣẹ ijọba apapọ to n ri si eto ilera alakọbẹrẹ, iyẹn National Primary Health Care Development Agency, NPHCDA, ti kede bi awọn ṣe le gba abẹrẹ naa. Ninu atẹjade ti wọn fi lede loju opo Twitter wọn, NPHCDA ni awọn eeyan le lọ fi orukọ silẹ lati gba abẹrẹ naa lori ikanni www.nphcda.gov.ng. Bawo ni ẹ ṣe le fi orukọ silẹ fun abẹrẹ naa? Ti ẹ ba ti de ori ikanni nphcda.gov.ng, ẹ lọ si abala ti ẹ ti le fi orukọ silẹ fun abẹrẹ naa ni igun apap ọtun. Ẹ o ri awọn imọran kan nibẹ pẹlu awọn nọmba ẹrọ ibaraẹnisọrọ ti ẹ le pe nipa abẹrẹ ọhun. Francis Olusola Alao: Wọ́n ti ti ọ̀rọ̀ òṣèlú bọ ọ̀rs Sunday Igboho, ṣùgbọ́n..- Oba Olugbọn Lẹyin naa ni ẹ o ri fọọmu iforukọsilẹ abẹrẹ ajẹsara ọhun. Lara awọn awọn ohun ti wọn yoo bere ninu fọọmu naa ni orukọ yin, ẹrọ ibaraẹnisọrọ, email, nọmba ile ti ẹ n gbe, ọjọ ibi yin, ibi ti ẹ ti fẹ gba abẹrẹ naa atawọn ohun miran to ṣe pataki nipa yin. Ti ẹ ba ti tẹ awọn alaye yin sinu fọọmu naa tan, ki ẹ fi ranṣẹ si ajọ NPHCDA. Ti ẹ ba ti ṣe eyii tan, NPHCDA yoo fun yin ni nọmba idanimọ kan gẹgẹ bii nọmba abẹrẹ ajẹsara yin. Ẹ wo àwọn tí yóò kọ́kọ́ gba abẹ́rẹ́ àjẹsárá Covid-19 to bá dé sí Naijiria... Ijọba orilẹede Naijiria ti fi lede awọn ti yoo kọkọ ni anfaani lati gba abẹrẹ ajẹsara ti yoo koju aarun Coronavirus ni Naijiria. Ninu atẹjade ti wọn fi lede pẹlu ajọṣepọ Ajọ eto Ilera Lagbaye, WHO ati Ajọ UNICEF ni wọn ti gbe alakalẹ naa jade. Ijọba ni awọn ti yoo kọkọ ni anfaani si abẹrẹ ajẹsara niiṣe pẹlu bi o ṣe pọn dandan si fun awọn eniyan, ti awọn onimọ nipa eto ilera si lewaju wọn. Ijọba ni awọn ti bẹrẹ si ni kọ awọn eleto ilera bi wọn yoo ṣe bẹrẹ si ni pin awọn abẹrẹ ajẹsara naa. Bakan naa ni awọn ẹrọ amohuntutu ti wọn nilo ti wa ni pese kaakiri awọn ojuko ti wọn yoo lo. Coronavirus after one year in Nigeria: Níbo ni ọ̀rọ̀ Covid 19 dé dúró ní Nàìjíríà? Eyi ni igba akọkọ ti orilẹede Naijiria yoo ma gba abẹrẹ ajẹsara Coronavirus to to miliọnu mẹrin fun awọn araalu lati koju aarun naa. Amọ orilẹede Naijiria ni orileede kẹta lẹyin Ghana ati Cote d'lvoire ti yoo gba abẹrẹ ajẹsara naa ni ẹkun iwọ oorun ilẹ Afrika. Ọjọ́ Ìṣẹ́gun ní abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 tó tó 4 milionu yóò bàlẹ̀ sí Nàìjíríà Orilẹede Naijiria yoo gba abẹrẹ ajẹsara covid -19 wọle si orilẹede yii bẹrẹ lati Ọjọ Keji, Oṣu Kẹta, ọdun 2021. Akọwe ijọba orilẹ-ede Naijiria, Boss Mustapha lo kede bẹẹ ninu atẹjade ti wọn fi lede. Mustapha ni Ajọ to n risi eto ẹkọ lagbaye, UNICEF ni yoo gba abẹrẹ ajẹsara naa wọle lati ileeṣẹ COVAX. ''Abẹrẹ ajẹsara wa kuro ni India ni Ọjọ Kini, Oṣu Kẹta, ọdun 2021 ni alẹ, ti yoo si de ilu Abuja ni ọjọ kẹji ni nkan bi aago mọkanla, ni iyalẹta. '' A n reti bii miliọnu mẹrin abẹrẹ ajẹsara lati ileeṣẹ COVAX '' Badagry Historical Wells: Omi inú kànga Wawú ló ń kó ọpọlọ àwọn ẹrú lọ ''Kini Osu kẹrin to pe, a n rẹti bii abẹrẹ ajẹsara bii miliọnu ọgọta, ti yoo si ju bẹẹ lọ ki ọdun to pari.'' O damiloju pe oogun abẹrẹ ajẹsara naa yoo wa lati ileeṣẹ apoogun AstraZeneca, eleyii to dara lati gbe pamọ di igba ti wọn ba n fun awọn eniyan'' Bakan naa ni ileeṣẹ to n risi ọrọ oogun ati ounjẹ lorilẹede Naijiria, NAFDAC ti buwọlu abẹrẹ ajẹsara AstraZeneca pe o dara lati lo ni orilẹede Naijiria. Amọ akọwe ijọba Naijiria naa fikun un pe awọn ilana to de aarun Coronavirus naa yoo si wa ni ṣẹpẹ lẹyin abẹrẹ ajẹsara naa. Aarẹ orilẹede South Africa, Cyril Ramophosa ti gba abẹrẹ ajẹsara. Bakan naa lo ni ida ogoji Naijiria ni awọn yoo fun ni abẹrẹ ajẹsara ni ọdun 2021, ti ida ọgbọn yoo gba ti wọn ni ọdun 2022. Mother tongue day 2021, Akomolede, YSAN: A ti parí iṣẹ́ lórí èdè ìperí Meta-Language Yorùb",0,yoruba "Bí a kò bá dẹ́kun ìgbìyànjú, bópẹ́ bóyá akitiyan á dópin lọ́jọ́ kan. / If one won't give up trying, one's hustling will one day come to an end. [Never give up, never quit; if we won't quit, we will win eventually.] #Yoruba #proverb",0,yoruba "Tó bá jẹ́ òótọ́, ṣàfihàn déètì nínú aago gẹ́gẹ́ bí àfíkun àkókò",0,yoruba "Osere tiata naa, to sọrọ naa loju opo Instagram rẹ tun ni oun sẹsẹ gbe sinima kan jade ni to da lori igbeyawo, eyi to gbe akọle rẹ ni 'Ki ni Igbeyawo'. Mercy ni bi o tilẹ jẹ pe oun ti kuro lọdọ oun, sibẹ oun ko tii sinmi lori ọrọ ifẹ, oun ko si lee pa ifẹ ti laelae. ""Awọn eeyan maa n bi mi pe Mercy, se o ko ni pada lọ sọdọ ọkọ rẹ mọ ni tabi tun ọkọ miran fẹ? Amọ otitọ ibẹ ni pe n ko mọ idahun fun ibeere yii. Okoowo mi ni mo gbajumọ, mo n tọju awọn ọmọ mi ati isẹ ti mo yan laayo. Nigba to ba ya, ohunkohun to ba yọju nipa ọrọ ifẹ ati igbeyawo, maa mọ bi maa se yanju rẹ."" Gẹgẹ bii osere sinima, a da bii ojisẹ Ọlọrun to yẹ ko maa tọ awọn araalu sọna ni, ki wọn si maa ri ẹkọ kan abi omiran kọ ninu awọn ere ta ba n gbe jade. Mercy ni igbeyawo ko yẹ ko dabi igba ti a mu ni lẹru. O ni o yẹ ko jẹ ifọwọsowọpọ ni , ki ẹnikan ninu igbeyawo gba ẹnikeji laaye lati dagba, ko si le da nnkan se. O fikun pe o maa n bani ninu jẹ bi ọpọ igbeyawo se n fori sanpọn, paapa nitori bi awọn eeyan kan se maa n se igbeyawo nitori awọn idi ti ko yẹ. Nigerian Fraudsters: Ìwádìí BBC fihàn pé ìdajì àwọn gbájúẹ̀ lágbàyéé wá láti Nàíjíríà ""Bi igbeyawo se n dojude n ba mi lẹru. O dabi ẹni pe esu mọọmọ dojukọ igbeyawo bayii ni, to si n baa jẹ, ti ọpọ lọkọ-laya si n ronu pupọ nipa igbeyawo wọn to fori sanpọn. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Osere tiata naa wa n gbarata pe ki lo de tawọn eeyan yoo fi owo iyebiye ra asọ ẹbi fun ayẹyẹ igbeyawo amọ lẹyin osu diẹ ni iru igbeyawo bẹẹ yoo fi ori sanpọn. O wa n gba wọn nimọran pe ti wọn ba ti ri daju pe awọn ko ba ara awọn mu tabi ti iwa wọn ko papọ, yoo dara ki wọn mase se igbeyawo. 'Pásítọ̀ ló sọ fún mi pé Ọlọ́run pè mí láti di Olokun tó ń bọ omi' Bakan naa ni Mercy ni ifarada se koko ninu igbeyawo, ti tọkọtaya yoo si ni iwa ipamọra amọ oun tako igbeyawo to ba ni iwa ipa ninu, eyi to le mu okun ẹmi wọn lọ lojiji. ""Lootọ ni awọn ọkunrin jẹ ori amọ o yẹ ki wọn mọ pe awa obinrin ni ọrun, bi ko ba si si ọrun, ori ko le duro, nitori naa lo se yẹ ki asọyepọ ati igbọraẹniye wa laarin lọkọ-laya."" O wa gba awọn tọkọ-taya nimọran pe ki wọn sa asala fun ẹmi wọn nibi ti iwa ipa ba ti wa ninu igbeyawo, ẹ mase fara daa tabi duro sibẹ. ""Awọn ọrọ eebu mii gan buru ju ki wọn na eeyan lọ. Ti ọkan ninu lọkọlaya ba si maa n binu pupọ, iru ẹni bẹẹ gbọdọ lọ fun igbani nimọran abi itọju.""",0,yoruba gbfi yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba "Ifẹsẹwọnsẹ laarin ẹgbẹ agbabọọlu Super Eagles orilẹ-ede Naijiria, ati akẹẹgbẹ rẹ lati Ghana, Black Stars n waye lọwọ nilu Abuja. Ẹgbẹ agbabọọlu Black Stars lo kọkọ gba bọọlu sinu awọn nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju mẹrinla. Amọ ko ju iṣẹju diẹ lọ, lẹyin iṣẹju mẹjọ, ni Super Eagles naa fi gba bọọlu sinu awọn Ghana. Oni loni n jẹ, ẹni a bẹ lọwẹ. Taani yoo bori laarin Naijiria ati Ghana ni abala keji idije komẹsẹoyọ fun ife agbaye ọdun 2022? Lẹyin ti Ghana ati Naijiria gbá abala akọkọ ifẹsẹwọnsẹ wọn ni ọsẹ to kọja nilu Kumasi, lorilẹ-ede Ghana, eyi ti wọn ti ta ọmi odo, dandan ni ki ẹnikan ninu wọn bori ni idije ti oni. Papa iṣere Moshood Abiola ni yoo ti waye, nilu Abuja laago mẹfa irọle orilẹ-ede Naijiria. Ẹni to ba jawe olubori ninu awọn mejeeji, yoo wa lara orilẹ-ede marun-un ti yoo ṣoju Africa ni idije ife agbaye ti yoo waye ni Qatar. Orilẹ-ede Ghana kuna lati kopa ni idije ife agbaye lọdun 2018, botilẹ jẹ pe Naijiria ko padanu idije ife agbaye kankan fun igba mẹrin leralera. Ẹgbẹ agbabọọlu ti goolu rẹ ba pọju laarin awọn mejeeji ni yoo lọ si idije naa. Ti Naijiria yoo ba kopa ni World Cup , o gbọdọ bori Ghana larin aadọrun iṣẹju ti ifẹsẹwọnsẹ yoo fi waye, tabi laarin asiko ti wọn ba fun wọn si tabi nipasẹ pẹnariti. Fun Ghana, awọn ni yoo lọ si World Cup ti Ileeṣẹ to n mojuto ere idaraya ni Naijiria, ati ajọ bọọlu, NFF, ti ko ẹgbẹrun lọna ogun tikẹẹti iworan silẹ lọfẹ fun awọn to ba fẹ wo ifẹsẹwọnsẹ ti yoo waye laarin Ghana ati Naijiria. Ọjọ Iṣẹgun ni ifẹsẹwọnsẹ naa yoow aye ni papa isẹre MKO Abiola to wa nilu Abuja. Idije naa ni yoo sọ ẹni ti yoo kopa ni idije ife agbaye ti yoo waye ni orilẹ-ede Qatar. Agbẹnusọ fun Aarẹ Muhammadu Buhari, Bashir Ahmad, kọ si oju opo Twitter pe ọkọ bọọsi ọfẹ tun wa nilẹ lati ko awọn ololufẹ super Eagles lọ si papa iṣere naa. Ibudokọ awọn bọọsi si ni wọn o ti ri tikẹẹti gba. Ọjọ Ẹti ni abala akọkọ ifẹsẹwọnsẹ naa waye ni ilu Kumasi lorilẹ-ede Ghana. Ọmi odo ni Super Eagles ati Black Stars ta. Ninu iroyin miran, ẹgbẹ agbabọọlu Black Stars ti gunlẹ si ilu Abuja bayii, ni imurasilẹ fun ifẹsẹwọnsẹ ọhun.",0,yoruba "Ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "Irọ́ ni àwọn ìròyìn náà , Àjọ Ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Èkó sì tètè fi òtítọ́ hàn láti pa á rẹ́ .",0,yoruba yoruba ni mi omoluabi ni mi omo oduduwa ni mi,0,yoruba "T. B Joshua: Chris Okotie ní wòlíì èké, onídán àti onítànjẹ tó ń fi ara rẹ̀ wé Jesu ní Joshua",0,yoruba ọlọ́run fẹ. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó ga jù.,0,yoruba "O yẹ ki opin de ba lilo awọn obinrin gẹgẹbii ohun elo amuludun nikan Ninu ifọrọwerọ pẹlu BBC, Dokita okei-Odumakin ni asiko to fun awọn obinrin lati dide ja fun itẹsiwaju ara wọn bayii. Odumakin ni awọn obinrin nilo ati pe fun idasilẹ asuwọn alajọni kan ti awọn obinrin lee maa ti inu rẹ mu owo lati ja fun ipo oṣelu. Ajafẹtọ naa ni bi o tilẹ jẹ wi pe nkan ti n yi pada lori pipese eto ẹkọ fun awọn obinrin ṣugbọn aabo fun wọn si n mẹhẹ patapata. 'Eredi ikọlu awọn agbebọn si awọn ile ẹkọ awọn akẹkọbinrin ni lati dawọn lẹkun lilọ si ileewe' ""Ajọṣepọ wa laarin eto abo ati eto ẹkọ nitori ẹni ti ko ba ni aabo to peye ko lee ronu ati lọ kẹkọ. ""O yẹ ki a kede akoko pajawiri lẹkun eto abo lorilẹede Naijiria. ""Bi a se n sọrọ yii, ọgọrun ninu awọn ọmọbinrin ti wọn ji gbe ni Chibok ni a si n wa, latun ri ti awọn ti Dapchi ti wọn ji gbe. ""Ijọba ni lati fi ipinnu han lori ipese abo ki wọn si yọ gbogbo awọn ti wọn ba rii wi pe wọn ko lee ṣiṣẹ ipese abo sita bi ẹni yọ jiga."" Odumakin: Naijiria ko gbọdọ ja awọn ọmọdebinrin naa kulẹ nipa ririi daju pe wọn ri wọn gba pada O ni orilẹede Naijiria ko gbọdọ ja awọn ọmọdebinrin naa kulẹ nipa ririi daju pe wọn ri wọn gba pada. Dokita Joe Okei-Odumakin ṣalaye wipe o yẹ ki opin de ba lilo awọn obinrin gẹgẹbii ohun elo amuludun nikan. Gẹgẹbii ọrọ rẹ, igba ọdun ni awọn obinrin orilẹede Naijiria fi n rakoro lẹyin gbogbo iran yooku gẹgẹbii iwadi naa ti se sọ. ""Anfani ayajọ awọn obinrin yii ni lati woye awọn isẹ takuntakun ti awọn obinrin n se lagbaye. ""Ninu iwoye temi, isẹ si pọ fun awọn obinrin lati se ki wọn lee de ibi ẹkunrẹrẹ wọn."" Awọn iroyin ti ẹ le nifẹ̀ si:",0,yoruba "Seyi Awolowo dupẹ lọ́wọ́ lórí akanṣe eto BBC Yorùbá dupẹ lọwọ awọn ololufẹ rẹ fún gbogbo ibo ti wọn di fun un nile Ẹlẹgbọn agba eyi ti gbogbo eeyan mọ si Big Brother Nigeria. Kí ló sún Seyi dé ilé ẹlẹ́gbọ́n àgbà? ""Gbogbo eeyan lo mọ mi ni Awolowo, Seyi, ọmọ Awolowo ṣugbọn mo fẹ ni orukọ temi to bẹẹ to jẹ pe ti mo ba ṣe nkan ni'ta, wọn a sọ pe Seyi lo ṣe e, kii ṣe Awolowo"". Eyi ni esi Seyi gẹgẹ bi awọn eeyan ṣe fẹ mọ idi pato to fi lọ fun eto yii tori wọn mọ pe olorukọ ati onile ọlọna ni. Seyi ni ""mo fẹ ko jẹ wi pe bi mo ba ṣe ohunkohun emi, Seyi ni mo ṣe e kii ṣe Awolowo"". Araale: Ọmọ ọdun melo gan ni Seyi Awolowo, ati pe ṣe Dokita ni? Seyi: Ọmọ ọgbọn ọdun ni Seyi. Mi o kii n ṣe Dokita rara o, ibi ti mo ti ṣiṣẹ ri ni wọn ti fun mi lorukọ yẹn o 'Doc' lati igba naa lawọn eeyan ti n pe mi bẹẹ. Mo kawe o ṣugbọn mi o kawe to oye dokita (PhD), oye onipele ikini (BSc) ni mo kawe gba oye rẹ ninu imọ ẹkọ Psychology. Araale: Awọn ileewe wo ni ẹ lọ? Seyi: Ile iwe Girama ti ijọ̀ba Odogbolu, Fasiti Olabisi Onabanjo, Fasiti Caleb(mi o pari ti mo fi bẹrẹ iṣẹ), Udegbe North American Univeristy. Araale: Ta lo fẹran ju lọ ninu gbogbo awọn to kopa ninu ile Ẹlẹgbọn Agba? Seyi: Mo nifẹẹ gbogbo eniyan ninu ile yẹn tori mo kọ ẹkọ kan latara ẹnikọọkan wọn. Ni bayii mo ti di ẹlomiran tori ẹkọ ti mo kọ lọdọ gbogbo wọn. Ko seeyan kan ni pato, gbogbo wa ni padi. Araale: Njẹ Seyi n pinu lati dara pọ mọ oṣelu? Seyi: Mi o sá fun oṣelu ṣugbọn o di tasiko Ọlọrun ba to. Mo fẹ kọkọ ni owo temi na ki wọn ma baa ni mo fẹ wa kowo jẹ nigba ti mo ba kara bọ oṣelu. Nigba ti wọn mẹnu le ọrọ oriṣiriṣi nkan to tẹyin awọn idije to waye ninu ile, itakurọsọ, ede aiyede, tawọn araale si n jẹwọ ẹni ti wọn fẹ gbaruku ti tabi bi wọn ṣe n ṣi kuro lẹyin ẹnikan bọ sẹyin ẹlomiiran tawọn eeyan wa n jẹ ọrọ Tacha ati Seyi lẹnu, Seyi fesi pe ọrẹ oun ni Tacha. Ko sohun to jọ mọ ede aiyede. ""O bu mi gbangba lori ẹrọ amohunmaworan ṣugbọn emi o ka a si, mo ṣi n bá a ṣọrẹ. Araale: Ẹgbẹ agbabọọlu wo lẹ n ja fun? Seyi: Manchester United ni o! Super Eagles naa wa nibẹ o, Eyimba Eyimba naa si wa nibẹ ṣugbọn Manu U ni mi o. BBC: Ṣe ẹ ro pé bi Baba Obafemi Awolowo gan ba wa laye, ṣe wọn a nifẹ si ki ẹ lọ sori eto BBNaija Seyi: Bẹẹ ni o da mi loju nitori idi pataki to mu mi lọ fun eto naa. BBC: Igbesẹ wo lẹ n gbé lati ri i pe awọn nkan ti Baba Awoo ṣe silẹ ko parun? Seyi: Mo ti ṣe agbekalẹ eto kan fun awọn to ni ẹbun pataki lori ẹrọ ayelujara lati jọ pade fun iwulo ara wọn. Ọna ti emi ya niyẹn. Kemi Lala: mo ń gbìyànjú láti mú inú òbí mi dùn Araale: Ṣe Seyi ti fẹyawo atipe ṣe ọmọ alawọdudu ni obinrin naa. Seyi: A o tii ṣegbeyawo ṣugbọn mo ni 'Baby' kan ti mo nifẹ gan, ẹni bi ọkan mi ni mo si ti wa pa pẹlu ẹ. Araale: Ṣe ẹ maa n lọ si ilu Ikenne daadaa. Seyi: Bẹ ni mo ma n lọ si Ikenne daadaa. Koda a jọ n lọ fun ayẹyẹ Ọdun Ereke laipẹ yii. Araale: Ṣe ẹ n gburo Aunty Tacha? Igba wo ni Seyi ri Tacha gbẹyin? Seyi: Bẹẹ ni. A ṣi rira ni nkan bii ọgbọn iṣẹju sẹyin. Gbogbo wa jọ wa gẹgẹ bi ọrẹ lasan ni. Araale: Ki lẹ́ ri kọ gan lori eto BBNaija? Seyi: Suuru. Keeyan maa fi suuru ṣe nkan. BBC: Iroyin sọ pe ni igba pipẹ sẹyin, ẹ fẹ gbiyanju lati gba ẹmi ara yin, ki lo fa a? Seyi: Ọmọde lo n ṣe mi nigba naa. Lati kekere ni ọrọ yii ti ṣẹlẹ o nigba ti mo wa ṣi wa nile iwe girama. Mo mu ago owo goolu to jẹ ti Baba mi, mo wọ ọ lọ sileewe lati fi ṣe fọri fọri fawọn ọrẹ mi. Baba mi si na mi gan to bẹẹ ti mo ro pe nina yẹn ti pọ ju tori naa mo kọ lẹta silẹ mo si gbe nkan jẹ. Nigba to maa fi di owurọ ọjọ keji wọn ti pe le mi lori ṣugbọn a dupẹ mo ṣi n mi. Eyi ni mo fi wa mọ pe wọn fẹran mi. Lori ọrọ yii ni Seyi fi gba awọn to jẹ pe idojukọ to tun ju ti oun lọ lo n mu wọn fẹ pa ara wọn ara wọn. O ni ko to bẹẹ nitori pe bi mi ba wa, ireti ṣi n bẹ. Eyi loun naa fi de ibi ti oun wa de lonii, bi o ba ti pa ara rẹ, ẹ o ba ma til gb pe ẹnikan wa to n jẹ Seyi. BBC: Ki lo tun ku ki awọ́n eeyan maa reti lọdọ Seyi lẹyin eto agbelewo Ẹlẹgbọn Agba? Seyi: Yatọ fun awọn nkan ti mo n ṣe tẹlẹ ki n to l fun eto naa bii arinrinoge, ere agbelewo, maa tun maa ṣe agbekalẹ eto fun awọn eeyan jankanjankan ati pẹlu awọn nkan ti mo n ṣe tẹlẹ.",0,yoruba ìlú.. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ àti ìbi tí wọn wà.,0,yoruba "Wọn bẹrẹ ifẹhonuhan naa lẹyin ti wọn fẹsun kan awọn adari ileeṣẹ naa pe wọn n gbe igbesẹ lati fa iṣakoso ileeṣẹ naa fun awọn adari miran lai jẹ ki wọn mọ bo ṣe n lọ, ati pe wọn ko san awọn ẹtọ kan fun wọn. Awọn oṣiṣẹ naa gbe oriṣiriṣi akọle lọwọ, eyii ti wọn kọ awọn ẹdun ọkan wọn si, ti wọn si n bere pe ki awọn adari ileeṣẹ ọhun wa ṣalaye fun wọn bi ọjọ ọla wọn yoo ṣe ri ni ileeṣẹ ọhun. Ni Eko, Ibadan, Akure atawọn ẹka Shoprite miran kaakiri Naijiria ni iwọde naa ti n waye. Niluu Ibadan, awọn oṣiṣẹ Shoprite to wa nibẹ kọ awọn akọle bii ""ọdun marun un si mẹwaa lai si igbega lẹnu iṣẹ, a gbọdọ gba owo wa ki Shoperite to salọ,"" ati bẹẹbẹẹ lọ. Lara awọn akọle ti awọn oṣiṣẹ Shoperite ilu Akure kọ ni pe o ti su wọn ki wọn maa ṣiṣe bi ẹru. Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun Bẹẹ naa ni wọn sọ pe ko bojumu to ki wọn ṣiṣẹ fun ọdun mẹwaa lai gba owo ajẹmọnu kankan. Ẹwẹ, nigba to n da si ọrọ naa, alaga awọn oniṣowo ni Dugbe, iyẹn niluu Ibadan, Ọgbẹni Silvanus Obisha ni gbogbo ẹka Shoperite to wa ni Naijiria ni ifẹhonuhan naa ti n waye. O ṣalaye pe awọn oṣiṣẹ ọhun ti gbe agagodo si ẹnu ọna Shoperite ni Ibadan ati gbogbo ẹka Shoperite miran ni Naijiria lori ẹtọ wọn ti wọn n bere fun. Gẹgẹ bo ṣe sọ, gbogbo akitiyan awọn oṣiṣẹ naa lati ni gbolohun pẹlu awọn alaṣẹ ile itaja igbalode ọhun lo ja si pabo nitori wọn ko ṣetan lati ni ijiroro kankan pẹlu awọn oṣiṣẹ naa. Ṣaaju ni awọn iroyin kan ti kọkọ sọ pe awọn alaṣẹ ile itaja naa ti bẹrẹ igbesẹ lati fa ileeṣẹ ọhun le awọn alaṣẹ miran lọwọ ninu oṣu Kẹrin ọdun yii. Francis Olusola Alao: Wọ́n ti ti ọ̀rọ̀ òṣèlú bọ ọ̀rs Sunday Igboho, ṣùgbọ́n..- Oba Olugbọn",0,yoruba "'Buhari yoo si tẹsiwaju lati pari awọn apati akanṣe iṣẹ gbogbo dipo bibẹrẹ awọn miran' Gẹgẹ bi minisita feto iroyin, Alaaji Lai Mohammed ṣe sọ ọ lasiko to fi n kopa lori eto ileeṣẹ Mohunmaworan apapọ Naijiria, NTA, inu òṣuwọn ajọni fun idokoowo, Sovereign Investment Fund ni wọn ti fa owo naa yọ lati fi yanju akanṣe iṣẹ marun kan kaakiri ibu ati oro orilẹede Naijiria. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Awọn akanṣe iṣẹ ti ọrọ kan ni opopona marosẹ Eko si Ibadan, afara keji ori odo Niger pẹlu opopo alasopọ ẹkun ila oorun si iwọ oorun orilẹede Naijiria. Awọn akanṣe iṣẹ miran ti ọrọ kan tun ni opopona marosẹ Abuja si Kano pẹlu akanṣe iṣẹ lori ipese ina ọba lati Mambilla. Minisita Lai Mohammed ni iṣejọba aarẹ Muhammadu Buhari ti fara rẹ jin fun idagbasoke ohun amayedẹrun gbogbo jakejado orilẹede Naijiria; yoo si tẹsiwaju lati pari awọn apati akanṣe iṣẹ gbogbo dipo bibẹrẹ awọn miran. 'Wiwa ọkọ Baalu da bi ki ẹ lọ da duro sori apata'",0,yoruba Àkójú ọ̀rọ̀ yi kún fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde sí ara ilẹ̀. (Item 68),0,yoruba wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba HPV Infection: Àpẹ́rẹ́ àìsàn tó ń fa àrùn jẹjẹrẹ pọ̀ lára àwọn obinrin tó wà ní ìlú Ibadan - Ìwádìí fìhàn,0,yoruba àìkú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó ṣe pàtàkì.,0,yoruba lẹ́yìn náà ló kan ọ̀gbẹ́ni bọ́lájí ògúnsẹ̀yẹ ti wọ́n nípé ọ̀rọ̀ ìnákúnà nínú ìjọba làwọn yóò kọ́kọ́ yọ dànù bíi jìgá,0,yoruba Chelsea: Chelsea dun DJ Cuppy nínú lẹ̀yìn tí Arsenal gba omijé lójú rẹ̀,0,yoruba "#ManipulativesUnethicals (ZERO) - (UNQUANTIFIABLE) #AwesomeJESUS: """"""""""""""""#YORUBA: """"""""""""""""Bíbíre kò ṣeé fi owó rà"""""""""""""""" #ITALIAN: """"""""""""""""Amor tutti eguaglia.""""""""""""""""😀😀 https://t.co/L0I07eh814",0,yoruba "Nígbàgbogbo , àwọn obìnrin tí kò lárá tí ó tálákà ní í máa ń fi ara kááṣá .",0,yoruba o pataki. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Alàji lo ìgbà ọkọ.,0,yoruba "Ní igba mi owó àkokò, Baàlè ri Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú. ti A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..",0,yoruba RT @user: Eranko N Pa Eranko Jaye Ninu Igbo: Odaju laye!: Bi omo eniyan se n pa ara won jaye bee naa ni omo eranko n se... http://t.co/1…,0,yoruba "“Mo mu ìtọ̀, mo jẹ èédú àti iyẹ̀pẹ̀ nítorí àìsàn ‘Ovarian cyst’ tó kọlù mí”",0,yoruba "Àwọn ìlúmọ̀ọ́ká olórí orílẹ́-èdè tó sọ̀rọ̀ fẹnu kọ pẹ̀lú ẹ̀rọ gbohùngbohùn rèé Ohun to wọ pọ lagbo oṣelu ni pe ifura lagba oogun, awọn oloṣelu ko gbọdọ maa ro pe gbohungbohun ko si ni titan nigba gbogbo. Ṣugbọn iyanlẹnu lo jẹ pe ọpọ awọn olori orilẹ-ede lo maa n saaba gbagbe eleyi. Awọn aṣisọ ọrọ lati ẹnu awọn ilumọọka oloṣelu lagbaaye kan ti fi abuku nla kan wọn. Lọsẹ yii ni olootu ijọba orilẹ-ede Canada, Justin Trudeau da bi ẹni pe o n fi Aarẹ ilẹ Amẹrika, Donald Trump ṣe yẹyẹ nibi ipade NATO. Awọn aṣisọ manigbagbe lati ẹnu awọn olori orilẹ-ede marun un ree: 1. Ronald Reagan: 'A o bẹrẹ si ni ju ado oloro ni iṣẹju marun un' (1984) Aarẹ ilẹ Amẹrika nigba kan ri, Ronald Reagan sọrọ fẹnu kọ nigba ogun 'Cold War' laarin orilẹ-ede Amẹrika ati orilẹ-ede Soviet Union tẹlẹ. Nigba ti wọn n ṣe ayẹwo gbohungbohun lọwọ ni Aarẹ Reagan ṣeesi sọrọ pe,: ''ẹyin eeyan Amẹrika, inu mi dun lati sọ fun un yin pe mo ti buwọ lu ofin to de Russia laelae, a o bẹrẹ si ni maa ju ado oloro laarin iṣẹju marun un. 2. Jacques Chirac ko fẹran ounjẹ ilẹ Gẹeṣi tabi Finland (2005) Aarẹ ilẹ Faranse tẹlẹ ri, Jacques Chirac sọrọ to da rugudu silẹ nigba to rinrin ajo lọ si orilẹ-ede Russia. Aarẹ Chirac ro pe gbohungbohun to wa lọwọ oun ko si ni titan nigba to bẹrẹ si ni sọrọ pe ''awọn eeyan ilẹ Gẹeṣi ko ṣee gbẹkẹle papaa julọ pẹlu bi wọn ko ti ṣe mọ ounjẹ se. Chirac ni lẹyin ilẹ Gẹeṣi, orilẹ-ede Finland lo tun buru jai pẹlu ounjẹ sise. Ọrọ naa di aawọ laarin ilẹ Gẹẹsi ati orilẹ-ede Faranse nigba naa. 3. 'Yo Blair!' (2006) Ninu ipade G8 niluu St Petersburg lorilẹ-ede Russia ni aarẹ ilẹ Amẹrika tẹlẹ ri, George W. Bush ti sọ pe 'Yo Blair!' nigba to ki olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi, Tony Blair. Awọn mejeeji ko mọ pe awọn akọroyin n gbọ ohun ti wọn n sọ nigba ti wọn n ki ara wọn. Awọn alatako Blair ati Bush fi ọrọ naa ṣe yẹyẹ lagbo oṣelu. Àwọn ìlúmọ̀ọ́ká olórí orílẹ́-èdè tó sọ̀rọ̀ fẹnu kọ pẹ̀lú ẹ̀rọ gbohùngbohùn rèé 4. Gordon Brown's 'alaṣeju obinrin' (2010) Olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi tẹlẹ, Gordon Brown lo pe obinrin kan ni alaṣeju nibi to ti n bawọn eeyan sọrọ ni Rochdale. Ọgbẹni Brown pada sinu ọkọ rẹ lai mọ pe gbohungbohun si wa lara rẹ, nibẹ ni o ti n ba ọkan lara awọn amugbalẹgbẹ rẹ sọrọ. Nibẹ lo ti sọrọ pe alaṣeju l'obinrin, Gillian Duffy to beere ibeere lọwọ rẹ. Amọ, Brown pada tọrọ aforijin lọwọ obinrin naa. 5. 'Ọrọ rẹ ti su mi'- Aṣiṣẹ Obama ati Sarkozy Awọn akọroyin ni wọn gbọ nigba ti aarẹ ilẹ Faranse nigba kan ri, Nicolas Sarkozy n sọ fun akẹgbẹ rẹ lati Amẹrika, Barack Obama nibi ipade G20 lorilẹ-ede Faranse. Ọgbẹni Sarkozy lo n sọ fun Obama pe ọrọ olootu ilẹ Israel, Benjamin Netanyahu ti su oun. Obama fesi pe 'opurọ ni Netanyahu, ọrọ rẹ gan an le mu eeyan ṣe aisan, ohun ti mo n la kọja lojoojumọ niyẹn.'' Aṣiri ọrọ yoo to tu sita ṣakoba fun ibaṣepọ to wa laarin ilẹ Israel ati ilẹ Faranse pẹlu orilẹ-ede Amẹrika. UI graduation: Fasiti Ibadan ló fún mi ni ẹ̀bùn ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ tí mo fi kàwé síi- Habibat",0,yoruba "nípa àìmọ́. Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba iṣẹ́ ṣẹlẹ ni Ibadan ti gbogbo eniyan sọ o ṣe pataki. (2013),0,yoruba wúlò. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa àwọn ènìyàn: ti o wulo.,0,yoruba "( Árẹ̀wá ni èdè - ìperí fún “ Àríwá """""""" ní èdè Haúsá ) — tí ó tan ìjì àsọgbà ọ̀rọ̀ lórí ìfipábánilòpọ̀ àti irú àwọn ìwà - ipá sí àwọn obìnrin ní orí ẹ̀rọ ayélukára - wọn - bí - ajere .",0,yoruba ògún onírè o ògún ayẹ̀nà fún eníyán ayẹ̀nà fún ọmọ ènìyàn lánà ire kò mi tẹbí tará,0,yoruba "Ìdí pàtàkì tí a fi máa ń wípé """"""""""""""""""""""""""""""""Ajé Olókun"""""""""""""""""""""""""""""""" ò ju pé, inú òkun ni a ti ń kó Ajé ìyẹn owó ẹyọ. #OwoEyo #Yoruba",0,yoruba Peter Obi kò lè rí tó alátìlẹyìn igba ni ìpínlẹ̀ Kaduna- El-Rufai,0,yoruba ìròyìn tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ẹkọ́: ti o pẹ jú nìlọ̀ ni ọ̀nà tí ẹ̀ọ́ kan máa ń gbé ìyẹ̀ alẹ́.,0,yoruba í tún ṣe àwọn iṣẹ́ tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba ìpọ́n tàbí amọ̀kú ni a óò fi gbókú ọba kúrò láàfin lọ sí ibojì àgàgà nílú ọ̀yọ́ ilé bàràìpẹ̀bí là ń sin àláàfin ọba sí,0,yoruba Zhao Yunlin ni ó tú ìmọ̀ọ rẹ̀ sí èdèe Gẹ̀ẹ́sì .,0,yoruba "Awọn ọmọ Naijiria naa ni; Esther Agbaje, Oye Owolewa ati Nnamdi Chukwuocha. Esther Agbaje lo dije lati ṣoju ẹkun 59B ni Minnesota, iyẹn nile igbimọ aṣoju-ṣofin labẹ asia ẹgbẹ Democratic, to si ni ibo 17,396. Ẹni ọdun marundinlogoji na fi ẹyin Alan Shilepsky gbolẹ, eyii to jẹ ọmọ ẹgbẹ oṣelu Republican, ati Lisa-Delgado ti Green Party. Agbaje to kawe gbowe ninu ẹkọ imọ ofin lati fasiti Harvad jẹ ọkan pataki lara awọn ọmọ Naijiria mẹsan an to n kopa ninu eto idibo ọhun. Ṣaaju akoko yii, Agbaje ti kọkọ ṣiṣẹ pẹlu ileeṣẹ ijọba ilẹ Amẹrika, US State Department, bẹẹ lo tun ṣiṣẹ nileesẹ awọn amofin kan lẹyin to kọkọ kẹkọọ gboye ni Fasiti Pennsylvania. Esther Agbaje ni ọmọ Naijiria akọkọ tii yo jẹ ọmọ ile aṣoju-ṣofin ni Minnesota. Ọmọ Naijiria miran to bori nin ninu idibo ọdun 2020 ni Nnamdi Chukwuocha ti wọn dibo yan lati ṣoju ẹkun kinni ti ipinlẹ Deleware nile igbimọ aṣoju. Gẹgẹ bi ọmọ ẹgbẹ Democrat ti ko ni alatako kankan, Chukwuocha bori ninu idibo ọhun pẹlu ibo 7,640. Orlando Owoh: Èmí àti Oladipupo Owomoyela jọ lọ ẹ̀wọ̀n Alágbọn- Caroline Owoh, aya Orlando Ṣaaju ni wọn ti kọkọ yan Chukwuocha lati ṣoju ẹkun kinni ni ile igbimọ aṣoju Deleware lọdun 2018. Chukwuocha kẹkọọ nipa itan ni fasiti ipinlẹ Deleware, o si ni iriri nipa eto oṣe abẹle ipinlẹ ọhun. Ọmọ naijiria kẹta ti yoo di ipo oṣelu mu l'Amẹrika bayii ni Oye Owolewa. EndSars Protest:Ọ̀gá Àgba Ọlọ́pàá ṣàbẹ̀wò sí ìpínlẹ̀ Eko lẹ́yìn ìfẹ̀họ́núhàn EndSars Owolewa gbegba oroke ninu odibo naa lẹyin to fi ẹyin awọn alatako rẹ, Joyce Robinson-Paul ati Sohaer Syed gbolẹ. Owolewa ni ibo 164,026, nigba ti Robinson-Paul ni ibo 18,600, ti Syed si ni 15,372. Ọmọ Naijiria ọhun kẹkọọ gboye Ọmọwe ni Northeastern University, iyẹn ni ilu Boston. Oun ni ọmọ Naijiria akọkọ ninu iwe itan ti yoo di ipo yii mu ni agbegbe Colombia. Owolewa jáwé olúborí gẹ́gẹ́ bìi ọmọ Naijiria àkọ́kọ́ nílé ìgbìmọ̀ aṣòfin Amẹrika Ọmọ Naijiria to n dije lati ṣoju ẹkun Colombia nilẹ Amẹrika, Oye Owolewa, ti jawe olubori ninu idibo to n lọ lọwọ. Owolewa gbegba oroke ninu odibo naa lẹyin to fi ẹyin awọn alatako rẹ, Joyce Robinson-Paul ati Sohaer Syed gbolẹ. Owolewa ni ibo 164,026, nigba ti Robinson-Paul ni ibo 18,600, ti Syed si ni 15,372. Ninu atẹjade to fi soju opo Instagram rẹ, Owolewa sọ pe ""mo fẹ fi akoko yii dupẹ lọwọ gbogbo awọn ẹbi ati ọre mi lagbegbe Colombia."" ""Nitori akitiyan ati ifarajin yin ni mo ṣe di ọmọ Naijiria akọkọ ti yoo di asojuṣofin nilẹ Amẹrika."" Ipinlẹ Kwara ni baba Owolewa ti wa, ti iya rẹ si jẹ ọmọ bibi ipinlẹ Oyo. Lẹyin ti iroyin jade pe Owolewa ti bori ninu idibo ọhun, ọpọ awọn ololufẹ rẹ kaakiri Naijiria ati loke okun lo ti bẹrẹ si n kii ku ori ire lori itakun agbaye. Lara awọn to ti bẹrẹ si n kii ni ajọ to n ri si ọrọ awọn ọmọ naijiria nilẹ okeere, NIDCOM. Wo awọn ọmọ Yorùbá méje, tó ń dupò nínú ìdìbò ilẹ̀ America Mọ̀ sí i nípa àwọn ọmọ Nàìjíríà mẹ́sàn-án tó ń díje nínú ìdìbò ilẹ America lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun. Ko din ni ọmọ orilẹ-ede Naijiria mẹsan an to n dije ninu idibo gbogboogbo ti yoo waye nilẹ America lọjọ Iṣẹgun. Pupọ ninu wọn lo n dije lati inu ẹgbẹ oṣelu Democrat, wọn si n du ipo ninu ijọba apapọ, ipinlẹ, ati ni agbegbe. Yatọ si idibo aarẹ, idibo gomina yoo waye nipinlẹ mọkanla, ati ẹkùn meji. Bakan naa ni idibo sile aṣofin yoo waye, fun gbogbo ijoko ile 435 nile igbimọ asoju-sofin, marundinlogoji ninu ọgọrun un yoo si waye nile aṣofin agba. EndSars, EndSwat Protest: Òbí agbábọ̀ọ̀lù Gbenga Tiamiyu Kaka àtàwọn míì tí ọlapàá pa sọ̀r Awọn ọmọ Naijiria to n dije: Ni ipele ijọba apapọ, 1) Ọgbẹni Oye Owolewa: Ẹni yii ti baba rẹ jẹ ọmọ ipinlẹ Kwara, ati ti iya rẹ wa lati ipinlẹ Oyo, n du ipo (ti ko nilo ibo) sile igbimọ asoju-sofin Onimọ nipa oogun oyinbo ṣíṣe ni Owolewa, o si ni iwe ẹri Ph.D lati Fasiti Northeastern, ni Boston. O n dije lati ṣoju Ẹkùn Colombia, labẹ ẹgbẹ oṣelu Democrat. Jija fun owo oṣu to dọ́gba fun gbogbo oṣiṣẹ nilẹ America, ni afojusun rẹ. Ti wọn ba fi le yan-an, ẹni ọgbọn ọdun ọhun ni yoo jẹ ọmọ Naijiria akọkọ nile aṣofin ilẹ America. 2) Ọgbẹni Yomi Faparusi: Ẹlomiran to tun n dije fun ipo ninu ijọba apapọ ni Ọgbẹni Yomi Faparusi. Ọmọ ipinlẹ Ekiti ni, sugbọn ilu Ibadan ni wọn bi i si.Oludije to da duro ni lai si ẹgbẹ oṣelu kankan. O si fẹ ẹ ṣoju ipinlẹ Tennessee nile aṣofin agba lorilẹ-ede America. Faparusi kekọọ gboye ninu iṣẹ iṣegun oyinbo, ni Fasiti ilu Ibadan nibitri sanmọnti gbe dun ile ti wọn tun ni ọgba ẹlẹranko. Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ Bakan naa lo gba Ph.D, lati Fasiti Johns Hopkins, ati imọ nipa ofin, Widener University, ni Delaware. Kii ṣe igba akọkọ niyi to dije fun ipo ile aṣofin ni America. O gbiyanju lati gba tikẹẹti ẹgbẹ oṣelu Republican fun ile igbimọ asoju-sofin, lọdun 2014 ati 2016, sugbọn o fidi rẹmi nigba mejeeji. Ohun to jẹ Faparusi logun ni lati jẹ ""ohùn rere"" fun gbogbo ọmọ Naijiria ati ilẹ Africa, to ba fẹ ẹ dije fun ipo oṣelu lorilẹ-ede naa. 3) Yinka FaletiNi Missouri: Ọgbẹni Yinka Faleti, to jẹ ọmọ ipinlẹ Eko, naa n dije lati inu ẹgbẹ oṣelu Democrat, bo tilẹ jẹ pe ẹgbẹ oṣelu Republican lo n dari nibẹ. Ipo Akọwe Ijọba Apapọ lo n dije fun.Akọsilẹ lori ayelujara Wikipedia sọ pe, Faleti, jẹ sọja nileesẹ ọmọ ogun ilẹ America, laarin ọdun 1998 si 2004. Orilẹ-ede Kuwait lo ti sisẹ.Ẹni ọdun mẹrinlelogoji ọhun, ni iwe ẹri lati Ileewe ikọsẹ ologun ilẹ America, ni West Point. O si tun kekọọ gboye ninu imọ ofin ni Fasiti Washington.Afojusun rẹ gẹgẹ bi oloṣelu ni lati ri i daju pe awọn ti wọn ba dibo yan n tẹti si awọn to dibo yan wọn. Láàrín ìṣẹ́jú díẹ̀, ẹ ka ìwé Akinwumi Ishola, ""Nítorí Owó"" lórí Akomolede Yoruba 4) Paul Akinjo Ọgbẹni Paul Akinjo, lati ipinlẹ Ondo, n dije fun ile igbimọ aṣofin ipinlẹ California, lati ṣoju ẹkun idibo kejila. Akinjo ti fi igba kan jẹ igbakeji Mayor ilu Latherop, o si tun sisẹ gẹgẹ bi ọmọ ologun ilẹ America, laarin ọdun 1982 si 1989. Ọrọ ile gbigbe, eto irinna, ati ọrọ awọn asatipo lo jẹ ẹ logun. Victor Agunbiade ni ojú àlá ni Ọlọrun ti yan iṣẹ́ ọmọ ogun ojú omi fún òun ní America 5) Adewumi Kuforiji: Ni Delaware, Adewumi Kuforiji n dije fun ile igbimọ aṣofin ipinlẹ, lati ṣoju ẹkun idibo kẹrinlelọgbọn. Ọmọ ilu Ibadan, nipinlẹ Oyo ni Kuforiji O gba iwe ẹri ninu imọ isiro, ati iwe ẹri imọ ijinlẹ kejì ninu imọ amojuto okoowo,lati Fasiti ipinlẹ Delaware. O dije fun ipo yii kan naa lọdun 2018, sugbọn ẹni to wa nipo naa, Lyndon Yearick, ti ẹgbẹ oṣelu Republican, fi ẹyin rẹ janlẹ .Àwọn mejeeji lo tun jọ n dije lọjọ Iṣẹgun. 6) Esther Agbaje: Ni ipinlẹ Minnesota, Arabinrin Esther Agbaje, naa n dije fun ile igbimọ aṣofin, lati ṣoju ẹkun idibo 59B. Ẹgbẹ oṣelu Minnesota Democratic Farmer-Labour Party, to jẹ isọmọgbe ẹgbẹ Democrat, lo ti fẹ ẹ dupo. Ọmọ orilẹ-ede Naijiria ni awọn obi rẹ, sugbọn wọn ti di ọmọ ilẹ America. O n dije fun ipo ile igbimọ aṣofin ipinlẹ, lẹyin to fi ẹyin Raymond Dehn, to ti n ṣoju ẹgbẹ naa fun ọjọ pipẹ, janlẹ l'oṣu Kẹjọ. Agbaje ni iwe ẹri nipa imọ ofin, lati Fasiti Harvard. Iwe ẹri imọ ijinlẹ kejì lati Fasiti Pennsylvania. Bakan naa lo sisẹ nile isẹ ijọba ọtẹlẹmuyẹ ilẹ America. 7) April Ademiluyi: Ngozi Akubuike, ati Benjamin Osamenam, naa n dije. Ẹni ọdun mọkandinlogoji ni Ademiluyi. O si n dije fun ipo Adajọ nile ẹjọ Seventh Circuit, ni ijọba ibilẹ Prince George, ni Maryland. Akubuike ni ti ẹ, to jẹ amofin, jẹ oludije to da duro, fun ipo adájọ nile ẹjọ Minnesota 2nd District. Orilẹ-ede Naijiria ni Akubuike ti kekọọ imọ ofin, o si sisẹ nile ifowopamọ, ko to o ko lọ silẹ America. Nibẹ lo si tun ti kekọọ imọ ofin ni ileewe imọ ofin, Mitchell Hamline. Super Tuesday: ìdìbò láti yan ẹni tí yóò díje tako Trump bẹ̀rẹ̀ O ti sisẹ gẹgẹ bi amofin fún ipinlẹ Minnesota. Ọdun 1982 ni Osamenam, de si ilẹ America. O si n dije fun ipo aṣofin nijọba ibilẹ Brooklyn City Council ni Minnesota. Onimọ ẹ̀rọ lo jẹ, ni ileesẹ eto irinna ipinlẹ naa.Labẹ ẹgbẹ oṣelu National Party, lo si ti n dije. O ti fi igba kan jẹ Aarẹ ẹgbẹ awọn onimọ ẹ̀rọ, to jẹ ọmọ Naijiria, ni Minnesota.",0,yoruba mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "Àbẹ́òkúta. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.",0,yoruba "Nígbà tí Ọba fè joko, Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..",0,yoruba "ìyẹ̀ alẹ́. Èyí ni òun tí a ní nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Nitori eyi, ara eni lo ni Bẹ́ẹ̀ ni.",0,yoruba eni lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí gbogbo ènìyàn gbọ́dọ̀ kọ̀ láti rí ìdìsẹ̀ àti àlàáfíà.,0,yoruba "Ìlú kan wà ní ìpínlẹ̀ Èkó #IfakoIjaye, arábìnrin afínjú kan láti #Abeokuta tí ń gbégbègbè ọ̀hún ló fà á tí a fi pe ibẹ̀ ní arógángán #Yoruba",0,yoruba àwọn ọ̀jọ̀gbọ́n awòràwọ̀ ní ó tún di bíi ọdún márùndínláàádọ́fà kí ìṣẹ̀lẹ̀ yí tó tún wáíyé,0,yoruba "àtọ́wọ́dá, àwọn oníṣẹ́ ìṣẹ́ ni ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó wáyé..",0,yoruba "àkerekere, Baàlè ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́.",0,yoruba jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìwà: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó ṣe pàtàkì.,0,yoruba kakaaki. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "kan. Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.",0,yoruba "Gẹgẹ bi iroyin ti a gbọ, opin ọsẹ yii naa ni Alaaja Ọṣuntoun jade laye lẹni ọdun mẹtadinlaadọrin. Ko si ẹni to ba n wo awọn ere ibilẹ Yoruba to kun fun aṣa, iṣe ati igbagbọ ẹya Yoruba ti ko ni mọ mama, Ọṣuntoun paapaa julọ nitori awọn ipa awọn ""ẹlẹmi agba"" to ko ninu awọn ere oloogbe Yẹkini Ajilẹyẹ. Ile rẹ lagbegbe Ijẹtu nilu Osogbo ni Mama dakẹ si. Akọwe fun ẹgbẹ awọn onitiata ni ipinlẹ Ọṣun, Ademọla Adedokun fi idi iroyin iku rẹ mulẹ fun awọn oniroyin. Lara awọn ere ti oloogbe Osuntoun ti kopa ni Koto Orun, Aye Akamara, Koto Aye, ti gbogbo rẹ jẹ latọwọ oloogbe Ajilẹyẹ. Oloogbe Ọṣuntoun funrarẹ naa gbe awọn ere kan jade bii 'Omi Ipin,' 'Imi Esin' ati 'Ogun Omo Iya le', to jẹ ere ti o ṣe gbẹyin, gẹgẹ bi ọgbẹni Adedokun ṣe sọ. Tóò bá fún ọkùnrinn lóúnjẹ́ tóo tẹ́ kiní yẹn sílẹ̀ fún un dáadáa... - Yinka TNT",0,yoruba Àwọn ẹ̀kọ́ dídì yìí ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọba lo tun se fi.,0,yoruba "Methodist church Prelate Samuel Kanu: Báyìí nì orí ṣé kò olórí ìjọ Methodist, àlùfáà méjì ní Abia yọ lọ́wọ́ ajínigbé",0,yoruba ní nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o pataki.,0,yoruba Àpè Mọrà Ẹnì ní tèmi dire! Talk your own ñow ooo! #laleerebe #iyil2019 #africa #culture #nigeria #yoruba #unilagbabes #gbajumoÒṣeré #mynigerianproverb #lagosnigeria #africancatoon #ologbontv… https://t.co/W091Gwk9Ms,0,yoruba "Àwọn ará ẹbí wọn ma dá aṣọ jọ fún òkú náà, tí wọ́n ma kó sí inú ihò ilẹ̀ kí wọ́n tó tẹ́lẹ̀ òkú náà le ní orí. Ìgbàgbọ́ wọn ni wípé, wọ́n ń di ẹrú fún òkú náà lọ sí ọ̀run",0,yoruba "9. Gbólóhùn mìíràn fún agbárí ni àtàrí, gbólóhùn mìíràn fún ọmọ kékeré ni aròbó, gbólóhùn mìíràn fún ìrètí ni_____ #Ibeere #Yoruba",0,yoruba "Ileeṣẹ ogun oju ofurufu ti ṣeranti oloogbe Tolulope Arotile lonii Lọjọ kejilelogun oṣu kẹsan ni ileeṣẹ ogun oju ofurufu tun awọn yara ikọ ọmọogun to n jẹ ""Crew Room"" ṣe to wa ni 115 Special Operations Group ni ilu Port Harcourt ti wọn si sọ lorukọ Ajagun Tolulope Arotile. Tolulope dagbere faye lọjọ kẹrinla oṣu karun ọdun 2020 lẹni ọdun mẹrinlelogun. To fi mọ gbogbo yara idana, baluwẹ, ile ijẹun, yara iwọṣọ awọn awakọ ati ọpọlọpọ ile igbọnsẹ ni wọn tunṣe ti wọn fi sọ ọ lorukọ Tolulope Arotile. Nigba to n sọrọ nibi ayẹyẹ iranti yii, ọga awọn ọmọ ogun oju ofurufu, Ọgagun Sadique Abubakar ni awọn ṣe ẹyẹ yii fun oloogbe Arotile, kii ṣe ni iranti rẹ nikan ṣugbọn lati ṣe moriya fun awọn ọdọbinrin ni Naijiria lati kawe, ṣiṣẹ takun takun lati mu ala ire wọn ṣẹ. ""O wu ni lori lati sọ pe lẹyin iku oloogbe Tolulope, ọpọ ọdọbinrin lo ti fifẹ han lati darapọ mọ ọlogun ofurufu"". Ọgagun Abubakar sọ bẹẹ.O ni awọn tun ṣe eyi lati fihan pe iṣẹ ire awọn eeyan ko gbudọ lọ lasan. O tẹnu mọ ọ pe titi lai ni iranti Tolulope Arotile yoo wa lọkan awọn ologun. Ninu atẹjade ti Ibikunle Daramola fọwọ si, awọn eeyan jankan jankan ninu iṣẹ ologun ati ni Naijiria lo peju sibi ayẹyẹ iranti naa.",0,yoruba "Nígbà tí Alàji fè se, Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..",0,yoruba "Èyí ni ìdáhún sí ìbéèrè wa àná o, ę Seun. 👏😉 #talkyourown #theyorubapeople #yoruba #blackpeople #cultur #asayorùbá #àsàyorùbá #àsà #traditionalart #òwe #theyorubasocialarena #streetstyle #street #talkyourown #mind… https://t.co/dty2qRBQ76",0,yoruba "ìsìnkú tí ó yẹni “ , Kaaw Elimane Bilbassi Toure tí í ṣe olóòtú ibùdó ìròyìn orí ayélujára Le Flambeau ti Mauritania kọ .",0,yoruba máà bọkàn jẹ́ àwé o gbìyànjú ìyá nìyáa múdà ọ̀pọ̀ èèyàn ni ò lè mú ọ̀bẹ,0,yoruba "Oluranlọwọ pataki fun gomina ipinlẹ Kaduna lori eto iroyin ati ibaraẹnisọrọ, Abdallah Abdallah fidi iṣẹlẹ yii mulẹ fun BBC pe lootọ ni ọwọ tẹ awọn eeyan naa. O ni ""nọmba ẹrọ ibaraẹnisọrọ ti wọn fi si ori iwe ipolongo ariya naa ni wọn fi tọpasẹ wọn, ti ọwọ fi tẹ wọn"". Bakan naa ni agbẹnusọ un ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Kaduna, ASP Mohammed Jagile sọ pe lootọ ni. Bawo lo ṣe yẹ ki eto naa lọ? Gẹgẹ bi nkan ti wọn kọ si ori iwe ipolongo fun ariya naa, awọn ti yoo ba wa sibẹ gbọdọ wa ni ihoho goloto. Oriṣiriṣi ere idaraya lo yẹ ko waye Ounjẹ loriṣiriṣi. Pabanbari ibẹ ni pe ibalopọ yanturu ni gbangba ati kọọrọ naa yoo waye nibẹ. 'Iru nkan bayii ko ṣẹlẹ ri nipinlẹ Kaduna' Habu Muazu, to jẹ ọmọ jayejaye, to tun jẹ olugbe nipinlẹ Kaduna lati bi ọdun mẹẹdọgbọn, sọ fun BBC pe, igba akọkọ niyii ti oun ri iru nkan bẹ ẹ ri lati igba ti oun ti n lọ sile ijo. ""Ko si ile ijo alaalẹ ti mi o mọ ni Kaduna. Ko si si iru ariya ti mi o ti i lọ lati bi ogun ọdun, amọ iru eyi ti awọn eeyan naa fẹ ṣe kan fẹ ba orukọ rere ti iru awọn eeyan bi temi to n fi iwa ọmọluabi jaye ori wa, jẹ ni."" Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: O ni o dara bi ijọba ati awọn ọlọpaa ṣe tete gbe igbesẹ, nitori pe eto naa ko ba fun awọn eeyan mii ni igboya lati tun ṣe bẹ ẹ. Ọrọ ariya naa si ni ọpọ eeyan n jẹ l'ẹnu lori ayelujara, pe o dara bi ijọba ṣe dawọn duro.",0,yoruba Ẹ̀yìn ọmọlúàbí dà? Ọlọ́run á gbé yín ga o!! Tiyín dire lónìí.,0,yoruba "Yemi Ayebo, Yemi My Lover: Ìdí rèé tí orin kíkọ fi máa ń pò nínú sinimá mi...",0,yoruba Cristiano Ronaldo ni agbábọ́ọ̀lù tó dàgbà jùlọ tí wọn yóò ra ní owó tó tó £99m Ṣugbọn ọpọlọpọ ololufẹ ere bọọlu lo ti n sọ pe owo naa pọ lati na lori agbabọọlu to ti pe ọmọ ọdun mẹtalelọgbọn. Awọn kan ro pe ọjọ ori Ronaldo le ma gba laye lati fakọyọ fun ikọ Juventus fun igba pipẹ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ronaldo gba ayo 450 sawọn ninu ifẹsẹwọnsẹ 438 nigbati o wa pẹlu Real Madrid O si gba ami ẹyẹ Idije Champions League pẹlu Real Madrid ni igba mẹrin. Àdéhùn ètò ọrọ̀ ajé ilẹ̀ Afirika le lẹ́yìn Ekiti Election: Ará Èkìtì ń fẹ́ gómìnà tí yòò tù wọ́n lára Stella Akinsọ: Àwọn Ìwé Mímọ́ fi àsẹ sí ìfètòsọ́mọbíbí,0,yoruba mi ò báa ní nǹkan pọ̀ rí àmọ́ mo mọ̀ ọ́ bí akọni ni mo salábàápàdé ní vi fún,0,yoruba lẹ ìkòkò wey ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò.,0,yoruba Àràá yóò sán pa ẹni ebi tí ń gbèrò ibi lè mi lórí. Àṣẹ. #Sango #Yoruba #Thunder ⚡,0,yoruba "lo joko. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba iṣẹ́ ṣẹlẹ ni Lagos ti gbogbo eniyan sọ o ṣe pataki. (2010),0,yoruba "Bàbá fè joko, Nitori eyi, ara eni lo ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba Baby Placenta: Ṣé lóòtọ́ọ́ làwọn kan máa ń fi ibi ọmọ ṣe oògùn?,0,yoruba "Oṣere naa k ọ bi ẹni n kọ itan ere ori itage o ni: ""Irọle ọla jẹ ọjọ faaji, nigba ti awọn ọkunrin ati awọn ọdọbinrin yoo ba ayanmọ ọpọlọpọ jẹ lori ibusun ifẹkufẹ ara"". Bamiloye ni nigba ti ilẹ ọjọ keji yoo fi mọ, nkan ti dahun. ""Ayanmọ yoo di tita fun ọdọkunrin tabi ọdọbinrin to ti ta ọjọ iwaju rẹ fun eṣu"". Ìwọ tó ń ṣí ara sílẹ̀ lọ ṣọ́ọ̀ṣì, ṣé apàyàn kọ́ ni ẹ́ báyìí?- Mike Bamiloye Àwọn ìgbà tí ìmọ̀ràn Pásítọ̀ Adeboye lóri igbéyàwó ti fa àríyànjiyàn Wo nkan tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa gbajúmọ̀ oníwàásù 'Lórí irọ́' Ẹ̀yin olórin ẹ̀mí tó ń bóra, lo èékáná gígùn, oò yàtọ̀ sí aṣẹ́wó hòtẹ́ẹ̀lì tí wọ́n ń gbé bíi súùtì Pepper Menti - Bola Are Gbajugbaja oṣere yii fi apẹrẹ ọrọ we Josẹfun ninu bibeli to ni ayanmọ rẹ ko ba ti di gige kuru to ba jẹ pe o ba iyawo Potiphar ọga rẹ lajọṣepọ. O fi sita lori ayelujara pé ""ẹ ku ayajọ ọjọ ololufẹ...! Bi o ba ṣe pe Josẹfu ba iyawo Portiphar ni ajọṣepọ, ko ba ma de aafin to ti di ọba to si ri iru opgo to ri"". Bamiloye ni Josẹfu moribọ lọwọ panp ti ko ba mu da ayanmọ rẹ legbodo eyi ti aye ọpọlọpọ eeyan ni ilu naa ati iran rẹ dara le lori"". Ọgbẹni Mike Bamiloye ni itan ọmọkunrin kan ni bibeli toun naa ṣe ""Valentine ninu iwe Oniwaasu ori ikeje, ẹsẹ ikẹfa si ikẹtadinlọgbọn jẹ itan ibanujẹ. ""O ti ro pe oun fẹ gbadun alẹ ọjọ naa, o ti ro pe oun yoo jaye ori ara oun amọ o doju ọjọ iwaju ara rẹ bolẹ po lalẹ ọjọ igbadun kanṣoṣo. There is a great story in Proverbs 7:6-27. It is a sad story of a young man on his own ""Valentine Night"". He had thought he wanted to have a fun that night, he had thought he wanted to enjoy himself, but crashed his future in a night of fun. ""Oniwaasu 7:21-23 21 Pẹ̀lú ọ̀rọ̀ dídùn ó sì í lọ́nà; ó tàn án jẹ pẹ̀lú ẹnu dídùn. 22 Òun sì tọ̀ ọ́ lọ lẹsẹ̀ kan náà, bí i màlúù tí ń lọ sí ibùpa, tàbí bí (aṣiwèrè) àgbọ̀nrín tí ń lọ sí ibi ọgbọ́n ìfabà kọ́. 23 Títí tí ọ̀kọ̀ fi gún un ní ẹ̀dọ̀, bí ẹyẹ ṣe ń fẹ́ wọ inú okùn, láìmọ̀ pé yóò gba ẹ̀mí òun.",0,yoruba "Akọwe ẹgbẹ naa, Yinka Odumakin lo sọ bẹẹ ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC Yoruba. Odumakin sọ pe, ohun to n ṣẹlẹ lọwọ pẹlu iwọde EndSARS kii ṣe ọrọ ẹlẹyamẹya, ṣugbọn o ti pẹ ti ara ti n kan awọn eeyan. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: O ni ""awa ko fi ọwọ si pe ija ti awọn eeyan n ja jẹ ti ẹlẹyamẹya, ṣugbọn ara n ni awọn eeyan naa, ni wọn fi ṣe ohun ti wọn n ṣe."" Akọwe Afenifere naa ni ohun to yẹ ki ijọba ṣe ni ko wa ọna lati yanju iṣoro to wa nilẹ dipo ko maa yinbọn pa awọn eeyan ilu. Odumakin wa gba ijọba ni imọran pe o yẹ ko dahun ohun ti awọn eeyan n beere. O ni ""lọna kinni, o yẹ ki ijọba ṣe ohun ti awọn eeyan n bere, lẹyin naa, o yẹ ki a bẹrẹ atunto ilu yii ni kiakia. Ọmọ ẹgbẹ Afenifere ọhun sọ pe iya n jẹ awọn eeyan, nitori naa o yẹ ki ijọba wa gbogbo ọna lati tan ijiya wọn dipo ko maa ṣina ibọn bo wọn. ShopRite, SPAR, Cash 'N' Carry àtàwọn dúkìá míì tí jàǹdùkú jó níná Lati igba ti iṣẹlẹ isekupani awọn oluwọde End SARS ti waye ni Lekki, ni awọn janduku ti bẹrẹ si n da ilu ru ni ipinlẹ Eko. Bi wọn ṣe n jo agọ ọlọpaa, ni wọn n ṣe wọn leṣe, ti wọn si tun n kọju ija si araalu, ọba alaye atawọn ileesẹ ijọba pẹlu ti aladani. Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko, Muyiwa Adejobi sọ fun BBC Yoruba pe, awọn janduku ti jo ọọfisi ọlọpaa marundinlogun lapapọ.Ọ̀rọ̀ Nàíjíríà kúrò ní sinimá àwòrẹ́rìn-ìn, Buhari gbé ìgbésẹ̀ bíi òbí àti olórí - Obasanjo gbarata Adejobi ni bi awọn oluwọde ṣe n sọ oko si awọn oṣiṣẹ wọn naa, ni wọn n yinbọn si wọn lati pa wọn tabi se wọn leṣe. O fidi rẹ mulẹ pe, ko din ni ọlọpaa meji toun lee fidi rẹ mulẹ pe wọn dagbere faye lati ipasẹ awọn ikọlu to waye yika ilu Eko naa. Yatọ si awọn ọọfisi ileeṣẹ ọlọpaa ti wọn dana sun, tun wo diẹ lara awọn ileeṣẹ miran ti awọn janduku ọhun tun ti ṣọṣẹ l'Eko. Olùwọ́de 12 kú ni Lekki, 38 lapapọ kú lọ́jọ́ Isẹ́gun, 56 ni àròpọ̀ àwọn tó bá ìwọ́de lọ - Amnesty International Saaju la ti sọ fun yin pe gudugbẹ ọrọ ti jabọ lati ẹnu ẹgbẹ ajafẹtọ ẹni lagbaye, Amnesty International, ẹka ti orilẹede Naijiria lori iwa ipaniyan to waye ni Lekki lọjọ Isẹgun. Atẹjade kan ti ẹgbẹ Amnesty naa fi soju opo rẹ lori Twitter, lo pe akọle rẹ ""Ẹ se iwadii bawọn ologun se pa awọn oluwọde EndSARS"". Atẹjade naa ni salaye pe awọn oluwọde mejila ni awọn agbofinro yinbọn pa ni Lekki lọjọ Isẹgun. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Bakan naa lo ni iwa isekupani ọhun tun waye ni Alausa, tawọn osisẹ sọja ati ọlọpaa to pa wọn si gbe oku wọn pamọ, gẹgẹ bi wọn ti maa n se. Bakan naa ni ẹgbẹ ajafẹtọ ẹni ọhun tun sisọ loju rẹ pe lati igba ti iwọde EndSARS ti bẹrẹ, eeyan mẹrindinlọgọta lo ti ba isẹlẹ naa lọ. O ni lọjọ Isẹgun nikan, eeyan mejidinlogoji lapapọ lo jade laye lasiko iwọde ọhun yika orilẹede wa. Ẹgbẹ Amnesty ni iwadii oun lori isẹlẹ naa lati ipasẹ awọn fidio to jade, ọrọ awọn ti isẹlẹ naa soju wọn ati abẹwo sile iwosan lo fidi isẹlẹ naa mulẹ. O ni awọn ẹri yii fihan pe awọn sọja yinbọn mọ awọn oluwọde lootọ ni Lekki laarin aago meje ku isẹju mẹẹdogun si mẹsan alẹ. Ẹgbẹ ajafẹtọ ẹni naa wa koro oju si iwa ika naa pẹlu afikun pe iwa kikọju ibọn sawọn oluwọde jẹ ara titẹ ẹtọ wọnsi ipejọpọ, isọrọ sita ati igbe aye loju. Bakan naa lo bu ẹnu atẹ lu iwadii kan to ni awọn osisẹ ijọba yọ ẹrọ ayaworan to n ka isẹlẹ silẹ, CCTV to wa ni bode Lekki nibi tawọn oluwọde naa wa lati ọsẹ meji sẹyin.",0,yoruba "Ó ń kọ́ ẹ̀kọ́ọ rẹ̀ nínú ìmọ̀ òfin bí ó ṣe ń ṣiṣẹ́ ní ọ́fíìsì àwọn oníṣirò kan , ó sì sọ ọ́ nínú ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò kan láìpẹ́ , pé òun ṣetán ní ilé - ẹ̀kọ́ ní ọdún kan ṣáájú ìgbà tí ó yẹ kí òun ṣetán tí òun sì gbé ipò karùn - ún nínúu kíláàsìi rẹ̀ àti láàárín - in àwọn ọmọ ọlọ́lá ní Roraima .",0,yoruba "mú, Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba tí yóò rò papa re yóò ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba Omoluabi wa ni abọ́jú irúngbọ ni nfàn ojú kakaaki.,0,yoruba "Ọpọ asọdun lo maa n waye nipa aisan kan ta n pe ni otutu aya eyi ti oloyinbo n pe ni Pneumonia. Koda, aisan yii wọpọ ni Naijiria, paapa laarin awọn ọmọde, ti ajọ Unicef si ti kede pe orilẹede Naijiria wa lara awọn ti aisan naa ti wọpọ lagbaye. Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Onisegun oyinbo kan, Dokita Afeez Oladele ni aisan otutu aya ko ni ohunkohun se pẹlu otutu rara nitori eeyan lee sun si ori ilẹ lasan tabi si aya si ẹrọ amuletutu lai wọ asọ, ti onitọun ko si ni ni otutu aya rara. O ni awọn kokoro kan ti a ko lee fi oju ri lo n fa aisan naa, ti a si lee ko awọn kokoro kekeke naa latinu afẹfẹ buruku, eefin, eedu, tabi ka lo ife ati ifọyin ẹni to ba ni aisan naa. O wa gba awọn obi nimọran lati maa tete gbe awọn ọmọde ti wọn ba kẹẹfin pe o n hu ikọ lọ sile iwosan fun itọju, ki aisan naa to bọwọ sori.",0,yoruba Gbogbo ẹni tó bá ní ẹ̀rí wípé mo fi owó ra ìbò kó mú wá – Oyebanji,0,yoruba @user Àjọṣe ló dùn. Èmi náà yáa ti sáre tẹ̀lé yín padà,0,yoruba "Bí mo ti ṣe wí ní ṣàájú pé, onírúurú ibi ní à ńkọ ilà sí lára, bí a ṣe ńkọ ilà kan sápá, là ńkọ òmíràn sí àyà #ila #yoruba",0,yoruba twitter di pápá ìròyìn ayédèrú lásìkò ìdìbò ọdúnun ní nàìjíríà,0,yoruba "Brexit: Àpẹẹrẹ́ burúkú ni ìjọba gẹ̀ẹ́sì ń fi lílẹ̀ -Ọ̀jọ̀gbọ́n Wole Soyinka Ìgbésẹ̀ Boris Johnson gẹ́gẹ́ bí àwọn kan ṣe ríi dàbi ọ̀nà láti ka àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ aṣòfin lápákò kí wan baa le dá ilẹ̀ gẹẹsì dúro láti kurò ni àgbájọ Yúróòpù lábẹ àwọn àyàfi kan ti wọ́n lè gbe sílẹ̀. Ẹkúnrẹ́rẹ́ èróngbà ọ̀jọ̀gbọ́n Wole Soyinka lóri ìgbésẹ̀ Boris Johnson Soyinka fí kún pé ìjọba ilẹ̀ Gẹẹsì ń fi àpẹrẹ ""ti kò dára lélẹ̀"" Ọ̀rọ̀ lórí Brexit Àṣojú ìjọba ti sọ pé ààyè yóò pọ̀ fún àwọn ọmọ ilé aṣofin láti jíròrò lóri ọ̀rọ̀ náà, bótilẹ̀ jẹ pé o yé kí ilé jòkó lóri ọ̀rọ̀ náà lọjọ iṣẹ́gun. ""Mí o ti lẹ̀ mọ pé lóju ayé mi mo lé rii asoju ijóba ti yóò gbèsẹ̀ lé a[wọn ilé ìgbìmọ aṣofin láti maa pé nílẹ̀ ìgbìmọ láti ṣe iṣẹ́ tí wọ́n yàn wọ́n láti ṣe, kí ni ìtumọ èyí ṣe Oliver Cromwell ti pada dé ní""? Syinka lo sọ èyí Soyinka fí kún pé ìjọba ilẹ̀ Gẹẹsì ń fi àpẹrẹ ""ti kò dára lélẹ̀""",0,yoruba "BBC gba'lejo ife agbaye FIFA Ni ọjọ ẹti ni awọn alasẹ ere bọọlu lagbaye gbe ife ẹyẹ naa lọ si ileeṣẹ BBC ni Ikoyi, nilu Eko gẹgẹbi itaniji ati ipolongo ti o nlọ lọwọ lori idije ife ẹyẹ agbaye fun bọọlu afẹsẹgba ti yoo waye lorilẹede Russia ni osu kẹfa ọdun 2018. Igba kẹfa ree ti orilẹede Naijiria yoo maa kopa ninu idije ife ẹyẹ agbaye Ọga agba fun eto iroyin ni ileeṣẹ BBC lorilẹede Naijiria, Peter Okwoche fi idunnu rẹ han si awọn alaṣẹ ere bọọlu lagbaye fun ipade yii. Ọgbẹni Okwoche ṣalaye pe ayẹyẹ ọhun fun awọn ololufẹ eree bọọlu ni anfani lati jẹ ẹbun rẹpẹtẹ ati lati ri ife eye naa. Ileeṣẹ BBC gba'lejo ife agbaye FIFA nipinlẹ Eko Gbajugbaja agbabọọlu orilẹede France ni, Chritian Karembeu pẹlu Ọgbẹni Peter Njonjo to jẹ aarẹ ileeṣẹ Coca cola lẹkun iwọ oorun ilẹ Afirika lo ṣi aṣọ loju eegun ife ẹyẹ yii lọwọ lorukọ ajọ to n ṣe amojuto ere bọọlu afẹsẹgba lagbaye, FIFA. Ọgbẹni Peter Njonjo to jẹ aarẹ ileeṣẹ Coca cola lẹkun iwọ oorun ilẹ Afirika, lo ko ikọ FIFA sodi lọ si ilu Eko. Ife ẹyẹ agbaye yoo wa fun wiwo ni ọjọ abamẹta nilu Eko O ni ife naa yoo wa ilu Eko fun gbogbo eniyan lati woo ni ọjọ abamẹta. Iru awọn iroyin ti ẹ le nifẹ si:",0,yoruba "tó kún jú, àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ìyá lo ojú odò.",0,yoruba "@user ẹ̀n ẹ́n ẹ̀n! Odù Ọ̀wọ́nrín, ojú odù Ifá kẹfà nìyẹn. Kí lẹ fẹ́ mọ̀ nípa Ọ̀wọ́nrín?",0,yoruba Yan Atọ́nà,0,yoruba "@user Ẹni tó ṣìrègún (ṣe ìrègún) ni ẹni tó ṣe oore fúnni nígbàkan ṣùgbọ́n tí kò mẹ́nu kúrò níbẹ̀, tó ntọ́ka sí oore náà ní gbogbo ìgbà",0,yoruba "Content is not available End of Facebook post, 1 Aarẹ Buhari sọrọ yii ninu ọrọ apilẹkọ rẹ to sọ nibi ayajọ ọjọ ijọba awarawa akọkọ iru rẹ l'Abuja lonii. Aarẹ Buhari Aarẹ Buhari ni ipa ti Abiola ati igbakeji rẹ, Baba Gana Kinjibe ti wọn jọ gbegba ibo lọdun 1993 kii ṣe kekere ninu eto oṣelu orilẹede Naijiria. Ọpọ awọn ajafẹtọ ọmọniyan lo ti n sọ fun ijọba apapọ lati fi orukọ Abiola sọ nnkan kan to jẹ ti ijọba apapọ ko le jẹ iranti nitori pa rẹ ninu eto oṣelu Naijiria. Aarẹ Buhari tun sọ pe ijọba oun yoo gbiyanju lati yọ ọpọ ọmọ Naijiria kuro ninu iṣẹ ati oṣi to n ba ọpọ eeyan finra. Aarẹ sọ pe orilẹede Naijiria lagbara lati yọ ọgọrun miliọnu ọmọ Nigeria ninu iṣẹ laarin ọdun mẹwaa. Aarẹ Buhari tun fikun ọrọ pe ijọba oun yoo tubọ ṣiṣẹ takuntakun si lati rii wi pe eto aabo mọnyan lori, ati pe ijọba tun ọrọ aje Naijiria ṣe sii. Aarẹ tun sọ pe ijọba oun ko ni foju re wo ẹnikẹni to ba fẹ da rogbodiyan silẹ nibi kibi kaakiri orilẹede Naijria ati awọn to ba kowo ilu jẹ. Aarẹ Naijiria sọ pe laarin ọdun mẹrin saa keji ijọba oun, oun yoo jẹ ki ina mọnamọna wa lowo pọọku fawọn ọmọ Naijiria. Ilu Abuja rosomu Ilu Abuja rosomu fun ayajọ ijọba awa ara wa eyi ti Aarẹ Muhammadu Buhari ṣẹṣẹ buwọlu pe ko maa waye ni gbogbo jọkejila oṣu kẹfa dun latoni lọ. Kẹti kẹti ni ero n tu ni gbagede Eagle Square ni olu ilu orilẹede yii, Abuja nibi ti eto naa ti n waye. Aarẹ Buhari Ṣaaju ọdun 2019, ọj ikọkandinlọgbn oṣu ikarun un ni orilẹede Naijiria maa n yẹ si tẹlẹ gẹgẹ bi ayajọ ijọba awa ara wa. Ni ọjọ kẹrindinlogun oṣu karun un ọdun 2019 ni aarẹ Buhari ṣẹṣẹ buwọlu u pe June 12 ti kii ṣe ajoji si gbogbo ọmọ Naijiria ni wọn yoo maa ṣe ayajọ ijọba awa ara wa ni Naijiria. Aarẹ Buhari Pataki rẹ julọ fun iran Yoruba ati awọn ọmọ Naijiria lapapọ to ṣi ranti iṣẹlẹ ọjọ kejila oṣu kẹfa ọdun 1993 ni pe ọjọ naa lọhun ni ti ibo waye ni NAijiria. Ilana idibo gbangba laṣa n ta yii jẹ ki eto ibo naa lọ geerege, ti awọn eeyan si dibo fun oludije to wọn lai fi ti ẹya, ẹsin ati ede ṣe. Agbára wo ni June 12 fún MKO Abiola tó ṣì ń fọhùn lẹ́yìn ikú rẹ̀? Sé o ti rí ère MKO Abiola tuntun? Ilé tó yẹ kí Abiọla gbé, àwọn wo ló ń gbé níbẹ̀? Wọn ka ibo naa de idaji, ni ijọba ologun nigba naa lọhun lai ni idi kan pato kede pe, wọn ko gbọdọ ka esi ibo naa mọ. Ṣugbọn ninu idaji esi ibo ti wọn ka, Oloye MKO Abiọla lo n leke, ti awọn eeyan si gba pe oun lo jawe olubori ninu ibo naa, nitori oun lo ni ibo to pọ julọ. Eyi jẹ diẹ ninu itan to mu ki June 12 ṣe pataki fun iran Yoruba.",0,yoruba "Man City ati Liverpool yoo koju arawọn ninu ipele ko-mọ-ẹsẹ-o-yọ idije Champions League Ẹgbẹ agbabọọlu Manchester City ni yoo koju Liverpool nipele ko-mẹsẹ-o-yọ idije Champions League, quarter-final Liverpool ni ẹgbẹ agbabọọlu akọkọ to na Man city ninu idije liigi ilẹ Gẹẹsi ni saa yii. Ireti ọpọ onwoye ni wi pe ifẹsẹwọnsẹ laarin awọn ikọ mejeeji yii yoo le diẹ nitori atimaasebọ awọn ikọ mejeeji. Liverpool naa Man City pẹlu ami ayo mẹrin si mẹta sugbọn Man City ti kọkọ f'agba han Liverpool pẹlu ami ayo marun sodo ni ipele akoko saa liigi ilẹ Gẹẹsi yii.",0,yoruba "O si dabi ẹni pe ede aiyede to n waye lori ọrọ lọbalọba nipinlẹ Ekiti, eyi to ti n mu ọpọ awuyewuye dani, ko ni pẹ rodo, lọ ree mumi bayii, ta ba wo isẹlẹ to n waye ni aafin Ọyọ lọsan ọjọ Aiku. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Idi ni pe Gomina ipinlẹ Ekiti, Kayode Fayemi ti lọ se ago laafin sọdọ Alaafin tilu Oyo, Ọba Lamide Ọlayiwọla Adeyemi kẹta lọsan ọjọ Aiku. Gbalaja ni Fayemi fi idọbalẹ bẹ fun Alaafin, eyi to n fihan pe ko si aawọ ma. Ninu ikede kan ti ijọba ipinlẹ Ekiti fi sori ayelujara Twitter rẹ, ni a ti ri ọpọ aworan to n safihan bi Alaafin se tẹwọ gba Fayemi tọwọ-tẹsẹ. Fayemi dọbalẹ gbalaja, Alaafin naa si fọwọ mejeeji gbe e dide pe ""kare, ọmọ daada. Dide nlẹ, ma fọwọ ọla tẹlẹ"" Lẹyin naa ni awọn aworan miran tun fi wọn han nibi ti wọn ti jọ joko, n ka iwe kan to jọ lẹta ti Alaafin ti kọkọ kọ si Fayemi, lori ọrọ kan to sọ pe oun yoo rọ awọn ọba Ekiti l'oye. Ko tan si bẹ o, aworan miran tun fi awọn mejeeji han, nibi ti wọn ti n rẹẹrin sira wọn lori ijoko to jọ pe, Alaafin n sọ fun Fayemi pe, ""eeyan o ki n ṣe bayẹn. Ko yẹ ki iwọ naa o sọ pe o maa rọ awọn ọba loye. BBC Yoruba yoo maa mu ẹkunrẹrẹ ijiroro awọn mejeeji wa fun yin laipẹ. Ọọ̀ni Ifẹ̀ la mọ̀ bíi olórí ọba Yorùbá, kí Aláàfin ya ṣo ewé gbéjẹ́ mọ́wọ́ - Ọ́ba Ekiti fárígá Saaju la ti sọ pe Alawe ti ilu Ilawẹ Ekiti, Ọba Adebanji Ajibade Alabi, Afuntade Kinni, ti ba BBC Yoruba sọrọ lati salaye idi to fi kọ lẹta kan si Gomina ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde lori ọ̀rọ̀ Alaafin tilu Ọyọ. Nigba to ba BBC Yoruba, Alawe ṣalaye gbogbo nkan to kọ sinu lẹta ọhun lẹẹkan si, to si ni pe, ọrọ lọbalọba ipinlẹ Ekiti ko le ye Alaafin laelae, nitorinaa ko maa da si ohun ti ko kan an. ''A fẹ ki Gomina Makinde kilọ fun Alaafin wi pe ko maa da aarin awọn lọbalọba ru nipinlẹ Ekiti nitori Ekiti kii ṣe ilẹ Oyo,'' Alawe lo woye bẹẹ. Kabiyesi Alawe ni awọn lọbalọba Ekiti ko ranṣẹ pe Alaafin lati da si ọrọ to n lọ laarin wọn, nitorinaa ko duro si aye rẹ. O ni Alaafin ko le duro si Oyo, ki o maa kọ lẹta ranṣẹ si Ekiti nitori Aguda o jẹ labẹ Gẹeṣi ati wi pe kaka ki kiniun ṣe akapo ẹkun, onikaluku a maa ṣọdẹ tiẹ lọtọọtọọ. O fikun ọrọ rẹ pe, Ọọni Ile Ife, ni gbogbo lọbalọba gba gẹgẹ bi olori nilẹ Yoruba, kii ṣe Alaafin, yoo si dara ki oriade ilu Ọyọ lọ so ewe gbejẹ mọwọ. Alawe ni ''asiko ajẹlẹ ti kọja, ati wi pe Ooni Ile Ife ni a gba si baba nilẹ Yoruba, oun ni kokari.'' ''Kabiyesi Ọọni ni Arole Oduduwa ti gbogbo wa mọ, Ile Ife si ni gbogbo wa ti san wa, kii ṣe Oyo, bẹẹ si ni Ọọ ni ko lee kọ iru lẹta buruku ti Alaafin kọ yii si gomina Fayemi laelae, arifin gbaa ni oun ti Alaafin se naa'' Kabiyesi Alawe lo sọ bẹẹ. Tantra: Ìlànà yìí ló ń kọ́ wa láti fi èémí àti ìṣẹ́po ara gbádùn ìbálòpọ̀ Kabiyesi Alawe ni ọgbọn ati imọ ni Kabiyesi Ọọni fi n to ilẹ Yoruba, Ọọni ko le kọ iru iwe ti Alaafin kọ to fi n bu gomina atawọn ọba alaye l'Ekiti. Àwa ọba Ekiti kìí ṣe Ajẹ́lẹ̀ rẹ̀, máṣe yọnu sí ohun tí kò kàn ọ́ ní Ekiti - Aláwẹ̀ fèsì fún Aláàfin Lẹta ti Alaafin tilu Ọyọ, Ọba Lamidi Ọlayiwọla Adeyẹmi Kẹta kọ si gomina ipinlẹ Ekiti, Dokita Kayọde Fayemi, ti n bi Ige ati Adubi bayii. Idi ni pe ojo lẹta miran tun ti yọju sita eyi ti wọn kọ si gomina Seyi Makinde, amọ to n fun Alaafin lesi pada nipa ọrọ to ba Fayemi sọ lori ọrọ awọn lọbalọba. Ninu lẹta tuntun naa ni alaga igbimọ lọbalọba nipinlẹ Ekiti, tii tun se Alawẹ tilu Ilawẹ Ekiti, Ọba Adebanji Ajibade Alabi, Afuntade Kinni, ti fesi pada fun Alaafin. Ninu iwe oloju ewe marun ọhun, ni Ọba Alabi ti n kesi gomina ipinlẹ Ọyọ pe igbimọ lọbalọba ni Ekiti koro oju si awọn ohun ti Alaafin mẹnuba ninu lẹta rẹ. Fun alaye, Alawẹ ni alaga igbimọ lọbalọba ni Ekiti, ta gbọ pe awọn ọba yoku kọ lati ba se ipade nitori pe wọn ni o kere si awọn ni ipo, ti ko si lẹtọ lati jẹ alaga le awọn lori. Alawẹ ni Alaafin ko lee wa jẹ gaba lori awọn ọba Ekiti nitori Ekiti ko si labẹ isejọba Ọyọ ri, bẹẹ ni ko lee si labẹ Alaafin laelae. Alawẹ wa n rọ Gomina Makinde pe ko da Alaafin lẹkun lori bo se n toju bọ awọn ọrọ abẹle to kan awọn lọbalọba nipinlẹ Ekiti nitori lẹta ti Alaafin kọ yii, lo kun fun didọwọ bo ootọ loju ati agbekalẹ ti ko tọna nipa isẹlẹ to n waye laarin awọn lọbalọba ati ijọba ipinlẹ Ekiti. Lẹta naa fikun pe ""Awọn ọba mẹtadinlogun ni Ekiti lo n tọkasi pe awọn wa lara ilana Pẹlupẹlu ninu igbimọ lọbalọba ni Ekiti, amọ pẹlu akọọlẹ ilana ofin ijọba tọdun 2018, ọba meji pere ni ijọba fọwọsi. Ko si sẹni to tako ijọba gomina Ayodele Fayose nigbanaa, ki wa ni pataki ọba mẹrindinlogun ti Alaafin n tọkasi pe o wa ninu ilana pẹlupẹlu?"" ""Mo si n fi gbogbo ẹnu ati asẹ mi sọ pe Alaafin se asise pẹlu bo se ni lati igba iwasẹ ni awọn asaaju ọba ni Ekiti ti jẹ mẹrindinlogun, eyiun awọn ọba ti ko lee darukọ wọn, amọ okan n dibọn pe oun ko mọ pe iye ọba to wa labẹ pẹlupẹlu koo duro si oju kan."" Alawẹ ni se ni Alaafin kan n feti si gbọyisọyi kiri lai wadi otitọ ko to maa naka aleebu si gomina Fayemi, to si tun kọ lati darukọ awọn ọba to to ni o kere ni ipo, o si n beere pe awọn ọba wo lo n baa wi gan? Alaawẹ, ninu lẹta naa, lo tun ni ko si aniani pe Alaafin maa n mọọmọ da awuyewuye ati rogbodiyan silẹ ni nibi ti ko si, to si n dasi ọrọ ti ko kan, to n gbe wahala to da silẹ fun igbimọ lọbalọba ni ipinlẹ Ọyọ ijọun wa, eyi to da ija agba meji silẹ laarin Alaafin ati Ọọni, ti wọn ko si lee se ipade mọ titi ti wọn fi yọ ipinlẹ Ọsun lara Ọyọ. ""Eyi to wa buru ju nibẹ ni pe igbimọ lọbalọba nipinlẹ Ọyọ ko tii se ipade kankan lati ọdun mẹrin nibiti o ti jẹ alaga wọn, eyi ko si sẹyin bo se nira fun lati jẹ ki alaafia, isọkan ati irẹpọ waye laarin awọn ọba alaye nipinlẹ naa. Bawo lo se fẹ fun wa ni ohun ti iwọ gan ko ni, awa ọba Ekiti kii se Ajẹlẹ Alaafin nitori naa ayọnisọ rẹ si ọrọ abẹle lọbalọba Ekiti ko tọ"" Alawẹ ni awọn ọba Ekiti wa n rọ Makinde lati fewe ọmọ mọ Alaafin leti, ko yee da si ọrọ ti ko kan, paapa lori ọrọ to wa nile ẹjọ. N kò ní ìjà pẹ̀lú Fayemi, ipò mi bíi aláàbò àṣà Yorùbá ní mó ṣe kọ lẹ́tà sí gómìnà Ekiti - Aláàfin Saaju la ti sọ fun yin pe Alaafin tilu Ọyọ, Aba Lamidi Ọlayiwọla Adeyemi Kẹta ti salaye pe agba kii wa lọja, ki ori ọmọ tuntun wọ, ni oun se fi imọran sọwọ si gomina ipinlẹ Ekiti, Kayode Fayemi lori aawọ awọn lọbalọba. Bẹẹ ba gbagbe, a ti kọkọ mu iroyin wa fun yin nipa lẹta kan ti Alaafin kọ si Fayemi lọjọ kejila osu kẹta, ati awọn koko to wa ninu rẹ. Nigba to n salaye siwaju lori lẹta naa, Alaafin ni oun ko ni kọnu n kọhọ kankan si gomina naa, koda inu oun ms si amọ oun gbe igbesẹ naa gẹgẹ bii oludaabo bo asa ati ise Yoruba ni. Alaafin sọ siwaju pe agba ti ko ba kẹhun sọrọ, afaimọ ko ma kẹtan sare, idi si ree ti oun fi n fa Fayemi leti pe ko gbọdọ yi asa ati ise wa pada nipinlẹ Ekiti lọna ti ko bojumu. ""Mo kọ lẹta naa gẹgẹ bii Alaafin Ọyọ, ohun mi si ni ohun gbogbo ọmọ Yoruba. Emi ni mo wa nipo to dara julọ lati tọ ijọba sọna, ki n si gba wọn ni imọran lori awọn ọrọ to nii se pẹlu asa ati isẹse Yoruba nitori Alaafin ni oludaabo bo asa to ga julọ."" ""Ojuse Alaafin ni lati da si awọn ọrọ to ba nii se pẹlu asa to ba suyọ nilẹ Yoruba. Asa atijọ si ni ilana Pẹlupẹlu to jẹ asa awọn ọba alaye ni Ekiti. Taa ba si wo ipa ti awọn Ekiti ko ninu ogun Kiriji, ko yẹ ka fọwọ rọ wọn sẹyin. Awọn ọba mẹrindinlogun to wa ni Ekiti jẹ akikanju ati alagbara ti Yoruba lee gboju le."" Alaafin tẹsiwaju pe ni gbogbo ọna, ohun amuyangan lawọn Ekiti jẹ fun ilẹ Yoruba, paapa lẹka eto ẹkọ, ko si fẹẹ si agboole kan ti wọn ko ti ni ẹni to kawe de ipo Ọjọgbọn. Iwe ti mo kọ si Fayemi jẹ lẹta baba si ọmọ ni, mo si nigbagbọ pe awọn ohun to wa ninu iwe shun yoo ye yekeyeke. Amọ titi di akoko yii, ijọba ipinlẹ Ekiti ko tii sọrọ lori lẹta ti Alaafin kọ si naa.",0,yoruba "Omo ilu Ibadan ni mi, ni agbole Akogun Balogun ni Amunigun. Iran Oshiware ni Opo Labiran ni ati sewa, Bakantari ni aaba wa. #TweetinYoruba",0,yoruba Ẹ̀ṣẹ̀ ni bí o bá gbó ìjọba lẹ́nu ( tako ìjọba ),0,yoruba ÒsìOrientation,0,yoruba Kì í ṣe torí pé ó dùn jù. https://t.co/ghjX8a1MmY,0,yoruba _Lo ìyítumọ̀ mìíràn:,0,yoruba Àgbá rè é l'óríṣìíríṣìí. Nínú àgbà ni ọtí ń gbé. @user @user @user @user @user #Yoruba https://t.co/pBC7yzBxFx,0,yoruba "àwọn iṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba Iyùn - un abẹ́ òkúta òkun jẹ́ ohun tí a ò leè fọwọ́ rọ́ sẹ́yìn nínú àwọn àmúṣọrọ̀ tí ó ń mú ọrọ̀ Ajé Tobago àti àwọn àyíká erékùṣù náà gbòòrò .,0,yoruba "@user: @user Ore mi, oma to ojo meta ke? Se alafia le wa?""""""""Dádá ni o. Iṣẹ́ ń lọ lọwọ́ o",0,yoruba RT @user: October 1st Naija stand up! Seems omoluabi are trending on UK twirrah! Omo ijebu ni mi ooo #yoruba 🇳🇬🇳🇬🇳🇬🇳🇬🇳🇬🇳🇬🇳🇬🇳🇬🇳🇬,0,yoruba "To difa fun eni ti ko toonii Ω̴ą to n dena de eni""""""""""""""""@user: Ajunilo o' le juni paa.""""""""""""""""",0,yoruba Muri Thunder: Àfojúsùn mi ni láti gba Grammy gẹ́gẹ́ bíi olórin Fuji,0,yoruba "Idi ree ti a fi ni ka mu tọ yin wa ohun tawọn ọmọ Naijriria ti n sọ nipa ikede yi. Tolori tẹlẹmu lo ti n da si ọrọ. Ninu awọn to gbaujumọ taa le tọka si ni igbakeji aarẹ ana, Atiku Abubakar. Atiku to jẹ gbajugbaja onisowo to si ni ọpọ ileeṣẹ sọ pe nkan ti Naijria nilo lasiko yi ni pipese iṣẹ lati le jẹ ki ọrọ aje burẹkẹ si. Asiko yi kọ lo yẹ ki ijọba fofin de karakata ti yoo maa jẹ ki owo wọle si ẹka ọrọ aje wa ni ohun ti Atiku sọ. O ṣalaye pe ''o ṣeeṣe ki ijọba mojuto cryptocurrency yi ati bi owo ti se n wọle si Naijiria lai se akoba fun aabo orileede wa.Eyi ṣuwọn ju ki wọn ti i pa lọ'' O tẹsiwaju pe ''awọn ọdọ Naijiria n koju inira airiṣe nitori naa o y ki ijọba pese iṣẹ lati le jẹ ki ẹka ọrọ aje gbooro si'' Ki lawọn ọmọ Naijira miran n sọ? Ẹwẹ awọn ọmọ Naijiria mii ti n da si ọrọ yi. Ninu wọn ni arakunrin Osasu Obayiuwana to sọ pe aini igbagbọ ninu eto ọrọ aje banki apapọ Naijiri lo mu kawọn eeyan ya sidi Cryptocurrency. Mo ṣẹṣẹ nronulati ṣowo Crypto ma ni-Davido Gbajugbaja olorin takasufe Naijiria Davido naa da si ọrọ yi. Loju opo rẹ ni Twitter, OBO ni oun ṣẹṣẹ n gbero lati darapọ mọ owo crypto ni ki ikede ijọba apapọ yi to jade. Ọrọ yi gẹgẹ bi o ṣe sọ fun awọn eeyan miliọnu mẹjọ to n tẹle loju opo rẹ jẹ iyalẹnu Awọn mii to tun sọrọ ati ohun ti wọn wi ree: Wo ìdí tí ìjọba Buhari fi ti àkáúǹtì àwọn tó ń ṣe kátà kárà owó ''cryptocurrency'' pa Gbogbo ẹyin to n ṣe kata kara owo ''cryptocurrency'' ni Naijiria, ẹ jawọ nbẹ tori o lodi sofin orilẹede yii. Banki apapọ ni Naijiria CBN ti paṣẹ fun gbogbo ile ifowopamọ lorilẹede Najiria lati gbe apo ikowosi awọn eeyan to ba n ṣe kata kara owo 'cryptocurrency'' ti pa. Koda CBN paṣẹ fawṣon ile ifowopamọ lati ṣe awari gbogbo awọn onibara wọn to ni apo ikowosi fun owo ''crypo'' ki wọn si ti wọn pa lẹsẹ kẹsẹ. CBN ṣalaye ninu atẹjade kan to fi sita ti ọga ẹka to n ṣe amojuto ni banki naa, Bello Hassan buwọlu pe kilọ fawọn ile ifowopamọ ni Naijiria ewu to wa ninu kiko owo ''crypo'' si banki wọn. Banki CBN sọ ninu atẹjade ọhun pe ile ifowopamọ kankan ko gbọdọ ni ohun kohun ṣe pẹlu kata kara mọ bayii. Banki CBN sọ ninu atẹjade ọhun pe ẹnikẹni to ba tapa si ikede yii yoo foju win ofin. Big breast: Oluwatosin Adegboro, Oluwaseun Amoo, Remi Fatolu: Ẹlòmíì ń fi irú ọyàn wa tọrọ Ẹwẹ, ọgọọrọ ọmọ Naijiria lo ti bu ẹnu atẹ lu igbesẹ banki apapọ Najiria. Awọn ilumọọka lori ayelujara bii Shehu Sani, Reno Omokri, Ben Murray-Bruce, Omoyele Sowore, Debo Macaroni, DJ Switch ati awọn mii lo koro oju si igbesẹ ijọba.",0,yoruba "RT @user: Bí èèyàn bá ṣèṣì kọ Ìkọkúkọ sórí àwòrán Ààrẹ ní Burundi, yóó bá ara rẹ̀ lẹ́wọ̀n ni. Burundi: Kọ Ìkọkúkọ sórí àwòrán Ààrẹ —…",0,yoruba nípa aráyé: ti o nuni ti o nuni ti o nuni ti o wulo.,0,yoruba "Ẹ gba àwọn àbá mẹ́tẹ̀ẹ̀ta yìí, kí ẹ sà á bí oògùn, kí ẹ mú u lò. Ire o! #Abameta #Yoruba",0,yoruba gan wey ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọba lo aye àìlẹ̀.,0,yoruba ọ̀gbọ́n. Alàji lo ni àṣà yorubá eyti o gbe lori àìmọ́ kọ.,0,yoruba àgbékẹ́ọlá pẹ̀lẹ́ tì ẹ ọmọ ìlú wo ni ọ́ tí o ò lọ abúlé rí ó ṣe mí láàánú fún ọ ẹni tó sọ ilé nù so àpò ìyà kọ́,0,yoruba "dídì. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba Àtẹ̀jáde ìtúmọ̀ 14 Èrèlé 2020 18 : 32 GMT,0,yoruba "Eyi ko ṣẹyin bi abadofin naa ṣe kọja ipele kika kẹta ni ile igbimọ aṣofin ipinlẹ naa. Agbẹnusọ fun Ile Igbimọ Aṣofin nipinlẹ Eko, Mudashiru Obasa to fi idi ẹ mulẹ wi pe lootọ ni wọn n gbe abadofin naa yẹwo. Obasa ni ijọba lo kọkọ gbe abadofin naa wa fun wọn, ki ọmọ ile kan to da a laba pe ki awọn obi ni ipin ninu ijiya to tọ si ọmọ, nitori awọn obi naa kọ lati tọ awọn ọmọ wọn daradara. O ni obi gbọdọ ma a mọ ohun ti ọmọ rẹ ba n ṣe ni gbogbo igba, nitori naa ni wọn gbọdọ pin ninu iya. Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo Kinni ofin sọ lori eyi? Ṣe awọn obi yoo fi iṣẹ silẹ ati gbogbo ohun ti wọn ba n ṣe lọna ati ri i pe wọn bojuto ọmọ? Agbẹjọrọ to tun jẹ ajafẹtọ fun awọn ọmọde, Arabinrin Elizabeth Udeh ni ko si ofin kankan to sagbatẹru igbese ti ijọba ipinlẹ Eko fẹ gbe naa. Udeh ni lọpọ igba, awọn obi kii mọ ohun ti awọn ọmọ wọn n ṣe ni ileewe giga nitori naa wọn ko le e pin ninu iya ẹṣẹ ti ọmọ ba ṣẹ. ‘Awọn ọmọ to wa ni fasiti ti dagba to lati mọ iyatọ laarin iwa rere ati iwa buburu.’ Agbẹjọrọ Elizabeth ni: ‘Ki ni yoo ṣẹlẹ si obi to ba n gbe ni jina rere si ibi ti ọmọ rẹ ti n kẹkọ, ṣe iru awọn obi bẹẹ yoo tun fi oju wina ofin ti awọn ọmọ wọn ba ṣẹ?’. ‘Ṣe awọn obi yoo fi iṣẹ silẹ ati gbogbo ohun ti wọn ba n ṣe lọna ati ri pe wọn bojutọ ọmọ? Amọ, Agbẹjọrọ to tun jẹ ajafẹtọ fun awọn ọmọde naa, Arabinrin Elizabeth Udeh fikun un pe idi ti awọn obi fi le jẹbi ni ti wọn ba kọ lati bojuto ọmọ wọn, Abi ti wọn ba fi ẹjọ ọmọ wọn sun pe wọn hu iwa buruku, amọ ti iya gbe lẹyin ọmọ rẹ lai ṣe iwadii to tọ lori ẹsun naa. Ti iru eleyii ba ṣẹlẹ, wọn le fi iru awọn obi bẹẹ jofin nitori wọn kọ lati sa ipa wọn fun awọn ọmọ wọn. ‘Ijọba yẹ ki wọn kọ awọn obi ni ọna ti wọn yoo fi tọ ọmọluwabi lawujọ’ Bakan naa ni AgbẹjọroTaiwo Akinlami naa bu ẹnu atẹ lu igbeṣẹ ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Eko naa to n da a laba lati ma a jẹ ki awọn obi pin ninu iya ti o tọsi ọmọ to ba n ṣe ẹgbẹ okunkun. Taiwo Akinlami ni ẹnikẹni to ba ti ju ẹni ọdun mejidinlogun lọ lẹtọ labẹ ofin lati jẹjọ ẹsun ni ile ẹjọ. Akinlami ni ika to ba ṣẹ naa lo yẹ ki ọba ge, nitori naa ti ko ba ti jẹ obi lo wuwa ibajẹ, obi ko gbọdọ jẹya ẹsẹ ti ko ṣe. O ni kii ṣe obi nikan lo n tọ ọmọ lawujọ, iṣẹ gbogbo eniyan ni, nitorinaa gbogbo wa lo jẹbi. Ti wọn ba ti mu awọn obi naa, wọn gbọdọ mu awọn Alfa, pasitọ, olukọ ati imaamu pẹlu awọn alabagbe ọmọ to ba ti wu iwa ibajẹ lawujọ tabi darapọ mọ ẹgbẹ okunkun. Bakan naa lo fikun pe ijọba yẹ ki wọn sa ipa wọn fun awọn obi nipa lila wọn lọyẹ nipa bi wọn ṣe le tọ ọmọluwabi lawujọ. O ni jijẹ, mimu, ile ati idagbasoke ọmọ ṣe koko, eleyii ti ijọba kọ lati fi ṣe iranwọ fun awọn obi. Amọ, Agbejọro naa fikun wi pe ari iru awọn obi bẹẹ ti ko bojuto ọmọ wọn, iru awọn yẹn le gba idajọ lọwọ ijọba.",0,yoruba "Nigba to n sọrọ lori ireti awọn ara ilu lori iyansipo adele ọga agba tuntun fun ileeṣẹ ọlọpaa, Usman Alkali Baba, ajijagbara kan, Kunle Wizeman Ajayi sọ pe aisi abo ounjẹ ati iṣẹ lo fa eto abo to mẹhẹ ni Naijiria. O ni ti awọn eeyan ko ba jẹun kanu, ti wọn ko si ni iṣẹ gidi lọwọ, ko sẹni ti yoo le sun ninu ile rẹ. Ajayi sọ pe ọrọ ti ọga agba tuntun ileeṣẹ ọlọpaa naa sọ pe oun yoo mu atunṣe nla ba ileeṣe ọlọpaa naa ni gbogbo awọn to ṣiwaju rẹ maa n sọ lai si iyatọ to dantọ ti wọn maa n mu wa. Gẹgẹ bo ṣe sọ, ""oun ti a fẹ gbọ ni pe ki ijọba sọ pe awọn ti n san owo oṣu tuntun fun awọn ọlọpaa gẹgẹ bii ileri ti wọn ṣe fu awọn ọdọ lasiko iwọde #EndSARS."" Kunle Ajayi ni ""ibere to yẹ ki awọn ọmọ Naijiria bere lọwọ ọga agba ileeṣẹ ọlọpaa tuntun ni pe, ṣe wọn ti ko awọn ọlọpaa onijẹkujẹ to n tọrọ owo loju popo kuro nibẹ?"" 'Bí ojú ọ̀nà agbàrá òjò tí ijọba ṣe n'IIorin ṣe ń pa àwọn ọmọ iléèwé wa rèé! Ẹ sàánú wa' ""Ṣe ki n ṣe awọn ọlọpaa funra wọn lo n fi owo ara wọn ra aṣọ iṣẹ si ọrun ara wọn"". Ajijagbara naa ni o di igba ti ijọba ba ka awọn ọlọpaa si eeyan pataki, ki wọn maa tọju wọn daadaa ki awọn eeyan naa to le mura siṣẹ. O pari ọrọ rẹ pe ọga agba tuntun ti wọn ṣẹṣẹ yan ko le ṣe aṣeyọri ti wọn ko ba ṣetọju awọn ọlọpaa to wa labẹ rẹ to n ṣo awọn eeyan ilu. O fi kun pe ijọba apapọ tun gbọdọ pese iṣẹ atawọn ohun amayedẹrun fun awọn ọdọ ti ko niṣẹ lọwọ ti wọn ba n fẹ ayipada rere nipa ti eto abo Naijiria. Àwọn èdè abẹ́ ahọ́n tóo lè fi sọ̀rọ̀ rèé láì tú àṣírí ọ̀rọ̀ rẹ áyé Wo ìpèníjà tí ọ̀gá ọlọ́pàá tuntun ní Nàìjíríà yóò kojú Kii ṣe iroyin mọ pe Aarẹ Muhammadu Buhari ti yan Usman Alkali Baba gegebi adele oga agba olopaa tuntun ni Naijiria. Ohun ti ọpọ n sọ bayii naa ni awọn ipenija marun un to ga ju ti Alkali Baba yoo maa dojukọ lori ipo tuntun naa. Asiko iyansipo ọga agba ọlọpaa Usman Alkali Baba bọ si asiko ti ipenija ọrọ abo lorilẹede Naijiria n peleke sii. Ojojumọ ni iṣẹlẹ ijinigbe iṣigun ji maluu, ikọlu laarin agbẹ atawọn darandaran pẹlu ikolu awọn ileeṣẹ ọlọpaa ati ọgba ẹwọn ni ipinlẹ Imo lẹnu lọwọlọwọ yii. To ba ri bẹẹ, ki wa l'awọn ipenija to wa nikalẹ fun ọga agba ọlọpaa naa? Eekan majẹobajẹ kan lori ọrọ abo lorilẹede Naijiria atawọn agbegbe aṣalẹ ilẹ Afrika, Mallam Kaniru Adamu yannana awọn ipenija marun un ti oga ọlọpaa tuntun, Usman Alkali Baba yoo koju. 1. Mimu atunṣe ba ajọṣepọ laarin olopaa ati araalu Ọpọ aigbọraẹniye ati aini igbẹkẹle ninu ọlọpaa lo wa laarin awọn araalu eyi to nii ṣe pẹlu awọn iṣẹlẹ atẹyinwa pẹlu bi awọn ọlọpaa kan ti sẹ fi iya jẹ alaiṣẹ tabi fi ẹtọ araalu dun wọn at'awọn iwa ritẹ ẹtọ araalu mọlẹ. Ọga ọlọpaa tuntun yii gbọdọ gbe igbesẹ to loorin lori mimu.atunṣe ba eyi. O gbọdọ gbe igbesẹ atunto to yanranti laarin ileesẹ ọlọpaa ki araalu lee mọ pe omi tuntun ti ru ẹja tu tun ti wọ inu rẹ. Bi a ko ba ni gbagbe iwode EndSARS to waye lọdun to kọja ninu eyi tawọn ọmọ orilẹede Naijiria, paapaajulọ awọn ọdọ ti tu sita lati fi ẹhonu wọn han lori iwa familete n tutọ tawọn ọlpọpaa kan n hu. 2. Bakan naa lo tun gbọdọ mojuto igbayegbadun awọn ọlọpaa abẹ rẹ paapaa lori owo oṣu wọn, ayika ti wọn ti n ṣiṣẹ, awọn owo ajẹmọnu gbogbo to tọ si wọn nitori nnkan o ṣe ẹnure fawọn ọlọpaa. Ọpọ si n woo pe oṣeese ko jẹ idi ti pupọ ninu wọn fin hu iwa kotọ kaakiri. Bi a ba fẹ ki ọlọpaa o duro daadaa, igbeaye wọn naa gbọdọ duro daadaa. 3. Ipese awọn ohun ija to ku oju iwọn. O gbọdọ ṣe amulo ẹdawo idagbasoke ileeṣẹ ọlọpaa, Government'sTrust fund lati fi pese awọn ohun ija to yẹ.fawọn ọlọpaa lati fi ṣe iṣẹ wọn bi o ti tọ ati bo ti yẹ. 4. Dida iyi ọlọpaa pada. Yoo ni lati ji giri ṣiṣẹ si dida ogo ati ọla iṣẹ ọlọpaa laorilẹede Naijiria pada. Eyi yoo lee mu ki wọn le ṣe iṣẹ wọn ni ibamu pẹlu ilakalẹ iwe ofin orilẹede Naijiria ki wọn si lee pese abo to yẹ labẹle. Lọwọ ti a wa bayii, eniyan fẹrẹ lee sọ pe awọn ologun lo n ṣe.iṣẹ ọlọpa lorilẹede Naijiria bayii. Nitoeinaa, ọga agba tuntun fun ileeṣẹ ọlọpaa ni Naijiria gbọdọ da ogo ati ọla pada si iṣẹ ọlọpaa lẹyẹ o ṣọka. Eyi ni yoo fun ijọba ni ifọkanbalẹ lati da wọn da iṣẹ abo abẹle laipe awọn ṣọja sii. 'Bí ojú ọ̀nà agbàrá òjò tí ijọba ṣe n'IIorin ṣe ń pa àwọn ọmọ iléèwé wa rèé! Ẹ sàánú wa' 5. Gbigba ọpọlọpọ eniyan si iṣẹ ọlọpaa. Ọga ọlọpaa tuntun, Usman Alkali Baba gbọdọ rii daju pe iye ọlọpaa to to lati mojuto abo Naijiria ni wọn gba sí iṣẹ. Nitori ọpọlọpọ ileeṣẹ alaabo lo n ṣe awọn iṣẹ to fara pẹ iṣẹ ọlọpaa bii ajọ ẹṣọ oju popo ati ajọ abo ara ẹni labo ilu (civil defence) pẹlu. Nitorinaa, ipenija kan to tun wa fun un ni lati wa ọna ati mu ki ajọṣepọ to dan mọran waye laarin awọn ẹka ileeṣẹ alaabo wọnyi. Lakotan, Mallam Kabiru Adamu ṣalaye pe bi awọn ileeṣẹ alabo wọnyi ba lee pa dukuu aarin wọn ti si ẹgbẹ kan naa, ki wọn si fọwọsowọpọ, ohun ija nla ni iṣọkan wọn yoo jẹ lati koju awọn ipenija abo lorilẹede Naijiria.",0,yoruba Alábòójútó fèrèsé rẹ kò ṣàtìlẹ́yìn bọ́tìnì ojú-iṣẹ́ ìfihàn tàbí o kò rọ́ọ̀nùalábòójútó fèrèsé ni.,0,yoruba nìkan. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.,0,yoruba "Aarẹ Muhammadu Buhari gan wa nikalẹ lasiko ti isẹlẹ ọhun waye. Nigba to n fesi lori isẹlẹ yii, ẹgbẹ alatako gboogi ninu idibo to n bọ, PDP, ninu atẹjade kan to fisita ni, o yẹ ko ye ẹgbẹ oselu APC pe ami pe aye ti kẹyin si ẹgbẹ oselu naa, ni isẹlẹ naa jẹ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: PDP ni o yẹ ka kiyesi pe awọn eeyan naa ju oko lu Buhari lẹyin ọjọ kan soso pere ti ipolongo ibo waye nipinlẹ Zamfara, nibi ti Buhari ti n ru awọ̀n eeyan ibẹ lọkan lati dara pọ ẹgbẹ APC ninu ete lati da rogbodiyan silẹ lasiko ibo to n bọ. Ẹgbẹ oselu alatako naa ni, awọn eeyan ipinlẹ́ Ogun ati Naijiria lapapọ ti kọ ijọba aarẹ Muhammadu Buhari, nirori irora, iṣẹ, oṣi, iwa ajẹbanu ati itajẹsilẹ to n waye laarin ọdun mẹrin to fi dari Naijiria. BBC Nigeria 2019: Lekan Kingkong ní a kò fẹ́ ìtàsílẹ̀ àti ikú ọ̀dọ́ lásìkò ìbò Sugbọn loju opo ikansira ẹni lori ẹrọ ayelujara, oju ọtọtọ ni awọn eeyan fi wo isẹlẹ naa. @mynameisgafar loju opo Twitter rẹ ni, oun foju laifi wo iwa awọn eeyan to sọ okuta lu aarẹ Buhari. O ni bi o tilẹ jẹ pe oun ko nifẹ rẹ, sugbọn o yẹ ka bu ọwọ nla fun nitori ipo nla to di mu, ibi ti a sa pe ni ori, ẹnikan kii fi ibẹ tẹ ilẹ. @Chizybae, lero tiẹ ni ohun ti yoo sẹlẹ ree ti eeyan ba ko ilu sinu isẹ ati ọwọn gogo ọja. @kcnaija loju opo Twitter tiẹ ni, o yẹ ka takete si ohunkohun to lee farajọ iwa jagidi jagan lasiko ibo to n bọ, paapa ninu eto oselu wa. Ko si baa ti korira igun keji si, ti a ko fara mọ wọn.",0,yoruba gbogbo ìlérí tí ẹ lé ni kí ẹ sọ di mímú ṣẹ lọ́dún nìí kí ó gòkè àgbà kí ara tù wá,0,yoruba "Ibaṣepọ abo s'abo Ile ẹjọ ti paṣẹ pe kii ṣe itapa si ofin mọ ki ọkunrin ati ọkunrin tabi obinrin ati obinrin maa bara wọ lo pọ. Bisi Alimi: Ìyà mi rò pé n kò leè ṣe ni àmọ́ n kò ní ìfẹ́ abo ni mo ṣe fẹ́ akọ Ṣe ni orilẹede naa kọ ofin to sọ pe ki wọn mu ẹni to ba n ṣe ibalopọ akọs'akọ tabi abos'abo ko si lọ ẹwọn ọdun meje eyi ti wọn ni bo ri labẹ ofin tẹlẹ niyii. Igbesẹ tuntun yii ti ile ẹjọ Botswana gbe waye lẹyin ti orilẹede Kenya ni awọn ko ni yi ofin tiwọn pada lati jẹ ki ibalopọ akọs'abo ba ofin mu. Adajọ mẹta lo jọ fẹnuko lati sọ ọdi ofin pe ki wọn fi aaye gba. Adajọ Michael tilẹ sọ wi pe ofin ti tẹlẹ ti ko fi aaye gba a n gbe lẹyin apa kan ni. Kí ló mú kí àyájọ́ June 12 ṣe pàtàkì ní Nàìjíríà Ta ni Femi Gbajabiamila tó di Olórí tuntun nílé Asojú-sòfin Nàìjíríà? Lati ọdun 1965 ni ofin to lodi si ibalopọ akọs'akọ laye igba ti awọn oyinbo amunisin gbe e wa si orilẹede wọn. Ṣugbọn ni ti eleyi, akẹkọọ kan lo gbe lọ si ile ẹjọ pẹlu alaye pe aye ati ilu gan ti yi pada ti ọpọlọpọ si ti f'ofin gba a kaakiri agbaye. ‘Lóòótọ́ ni ọ̀jọ̀gbọ́n fẹ́ bá mi lòpọ̀’ Awọn ajafẹtọ naa gba ipinu yii wọle ti wọn si juwe rẹ bi igbesẹ pataki lati ni ẹtọọ akọs'akọ nilẹ adulawọ. Lo ba di ofin lorilẹede Botswana!",0,yoruba "Omo mo mo mo mo baba Oni Lu.. 5th and 4th #generational Drummer ... 🥁 “ ti pe ti pe “ Issa longtime thing . . . #yoruba #heritage #fatherandson #royalty @user Winnipeg, Manitoba https://t.co/fYEjGgCgBe",0,yoruba aṣà. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba RT @user: Àgbà òṣèlú Ògbẹ́ni McCain ti fi ojú Ààrẹ Trump gbolẹ̀ ní ìlú Amẹ́ríkà. Wàhálà dé! Ààrẹ ti gbé fone rè kaná. #TweetYoruba htt…,0,yoruba Olóògbé Richard Akínjídé jẹ́ ẹni ọdún méjìdínlọ́gọrin .,0,yoruba "lo mú. Nitori eyi, ara eni lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìwà: ti o ní wúlò fún gbogbo.",0,yoruba orúkọ tí a ma ń pe ọba òsogbo ni àtaọjà ìlú òsogbo the title of the king of òsogbo is àtaọjà of òsogbo ọ̀sun state,0,yoruba o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ẹkọ́: ti o nuni ti o pẹ jú nìlọ̀ ni ọ̀nà tí ẹ̀ọ́ kan máa ń gbé ìyẹ̀ alẹ́.,0,yoruba "àìlẹ̀, Olùwo ri Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba Àmìi kí ni èyí ?,0,yoruba kan. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ àti ìbi tí wọn wà.,0,yoruba "Kẹkẹ alajọwa ni wọn n pe, eyi to jẹ itẹwọgba bayii laarin awọn ọdọ, ti wọn fi n da awọn eeyan kanka laujọ lọla, koda, ileẹkọ nipa rẹ gan ti wa. Nigba to n sọrọ lori agbekalẹ ibudo ikẹkọ kẹkẹ naa fun BBC Yoruba, Lekan Kuyoro tii se oludari ibudo naa ni, bii ere, bii ere lawọn n fi kẹkẹ sere nigba to bẹrẹ, ti awọn ko si mọ rara pe ọjọ iwaju rere yoo wa fun ere naa. O ni o ti di itẹwọgba bayii nitori ko wọpọ laarin awọn eeyan dudu tẹlẹ, to si wa n beere iranwọ ijọba fun ipese ibudo ti awọn yoo ti maa se idanilẹkọ nitori ibi ti awọn wa bayii ko ni aabo to. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Lasiko abẹwo BBC sibi idanilẹkọ awọn ọdọ to n se kẹkẹ alajọwa naa, a ri ti wọn n fi kẹkẹ rin lori igo ti wọn to silẹ, eyi to wu ni lori. Ẹyin naa ẹ wo fidio yi, ori yin yoo wu pupọ nipa awọn ọdọ naa.",0,yoruba ️eni ni ojo eti ojo kejidinlogbon odun ojo ti awa omo yoruba omo karo o ji ire ojo ifi gbe àṣà yorùbá lárugẹ,0,yoruba "@user: @user @user @user isé Gbogbowa ni..Lokùnrin, L'obìnrin..L'omodé àti àgbà""""""""""""""""bẹ́ẹ̀ ni, kówá wa ló kàn",0,yoruba jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò.,0,yoruba "Akọ̀wé ẹgbẹ́ CAN ní ìpínlẹ̀ Ebonyi nígbà kan ri tí wá rọ ọmọ Nàìjíríà láti fi ori jí òun ati pé òun yóò ma kíyèsára ní ìgbà míràn. Ìlúmọọka Olúsọagutan Simeon Ononogbu ní ẹmi ẹ̀tàn ló bàlé òun lásìkò ti òun n sọ àsọtẹ́lẹ̀ nipa ẹgbẹ agbabọọlu Super Falcons. O ni pé àwọn ẹgbẹ́ agbábọ̀ọ̀lù obinrin Nàìjíríà yóó wọ́ ipele tó kángun sí àṣekágbá nínú ìdíjẹ ifé ẹ̀yẹ àgbáyé tawọn obinrin tó n lọ lọ́wọ́ ní France. Gẹ́gẹ́ bi akọròyìn NAN sẹ sọ, ẹni ọ̀wọ̀ Simeon Ononogbu sọ sáa'ju idije ife ẹ̀yẹ àgbáyé pé ikọ Super Falcos yóò de ipele tó kangun si aṣekágbá. Bakan naa lo ni France to ń gba alèjò ayẹyẹ náà wà ni ipò kaàrún tọ jẹ ipele kéta si aṣekágbá. Iná Ibadan: Gbogbo dúkìá tó wà lókè ilé alájà kan náà ló jóná tán Akọ̀wé ẹgbẹ́ CAN ní ìpínlẹ̀ Ebonyi nígbà kan ri tí wá rọ ọmọ Nàìjíríà láti fi ori jí òun ati pé òun yóò ma kíyèsára ní ìgbà míràn. O ní "" ó ṣeni láànú pé asọtẹlẹ̀ mi lóri Super Falcons kùnà, èyí túmọ si pé ìsípaya náà kìí ṣe láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run."" Tomomewo Favour: olóṣèlú kìí ṣe ọ̀daràn tàbí alágbèrè Pasitọ yii ni: ""Ọ̀pọ̀ ẹ̀mi ló n rìn kiri ti yóò ma tan àwọn ènìyàn jẹ ká ti ènìyàn kò bá kíyèsára gẹ́gẹ́ bi irú èyí"" Ononogbu tún tẹnpẹlẹ mọ́ọ pé bi asọtẹ́lẹ̀ nípa Super Falcons tilẹ kùna òun túbọ dúro lóri ipò ti France yóò kangun sí Ó rọ àwọn ọmọ Nàìjíríà láti ma dá oun lẹ́jọ nitori ọ̀rọ̀ yìí nítori pé òun ti sọ asọtẹ́lẹ̀ mẹ́jọ ọtọ̀ọ̀tọ tó ti jási òòtọ́. Widows Day 2019: Mo máa ń sá kiri wá owó ilé ni -Opó Kini èrò ajọ CAN ọmọlẹyin Kristi lori asọtẹlẹ ẹ̀tàn: Ẹ̀wẹ̀, BBC Yoruba kan si ẹgbẹ́ adarí awọn ọmọ lẹ́yìn Kristi (CAN), Ẹni ọ̀wọ̀ Bayo Oladeji lóri èrò wan lóri isọtẹ́lẹ̀ ti kó wá si ìmúṣẹ ỌHUN. Iṣẹ́ ẹmí ẹtan ló bàlemi lasikọ tí mọ so aṣọtẹlẹ̀ pé wọn o wọ ipele aṣekágbá. Oluṣọ agutan naa ni àwọn kìí sọrọ̀ lóri ìrírí olúkulúkù nítori onikaluku lọ mọ apá ibi ti wọ́n ti n gbọ́ ìmísi. O ní ọ̀nà ti àwọn ọmọlẹ́yìn Kristi yóò fi ri ìtójú gbà lọ́dọ̀ ìjọba lo jẹ ajọ CAN lógun jùlọ, èyí si ni àwón maa n múgbọ. Oluṣoagutan yii ni onikaluku lo mọ iru ìpè ti oun gbà ati iṣẹ ti Oluwa ran oun lati ṣe. Ebola Virus: ìdí tí Ebola fi ń tàn kálẹ̀",0,yoruba "Ní ìgbà òde òní, bí ọ̀kín ti gbayì láàárín àwọn ẹyẹ, ni ẹní gbayì ní àwùjọ àwọn Yorùbá. Ẹní di ohun a fi ń dá àrà àti tí a fi ń gbé àṣà Yorùbá lárugẹ nípa fífi ẹní ṣe ẹ̀ṣọ́ ní ibi ayẹyẹ ìṣẹ̀se Yorùbá. https://t.co/kJG3EU6CG1",0,yoruba "Olalekan Jacob Ponle ti gbogbo eniyan mọ si Woodberry to jẹ ọkan lara awọn gbajuẹ ori ayelujara ti awọn ọlọpaa Dubai mu tẹlẹ pẹlu Ramoni Abass Hushpuppi. Ile ẹjọ ilẹ Amẹrika ti da ẹjọ ti wọn pe lodi si ọmọ Naijiria naa, Olalekan Ponle ti gbogbo eniyan mọ si Woodberry ti awọn ọlọpaa Dubai mu fun iwa gbajuẹ ori ayélujára nu. Gẹgẹ bi iwe iroyin abẹle Premium Times ṣe sọ, ile ẹjọ ilẹ Amẹrika ni awọn ko ni ẹsun kankan lodi si Woodberry Ọlọpaa mu Ponle ati Ramon Abbas ti gbogbo eniyan mọ si Hushpuppi ni Dubai ni ọjọ kẹwaa, oṣu keje, ọdun 2020. Lẹyin naa ni wọn ko wọn lọ si ilẹ Amẹrika fun igbẹjọ lori ẹsun iwa 419 ori ayelujara ti awọn Naijiria maa n pe ni Yahoo-Yahoo. Working religious women: Ẹ̀lẹ́hàá kìí ṣe ọ̀lẹ- Aminat Adegoke Awọn iwe iwadii kan to tẹ BBC lọwọ naa fidi rẹ mulẹ pe Adajọ Robert W. Gettleman lọjọ Iṣẹgun paṣẹ pe ki wọn wọgile igbẹjọ naa. Nkan to waye yii kii ṣe ajoji ni ilẹ Amẹrika labẹ ofin iwa ọdaran, ilana 48 maa n faaye gba ijọba da ipẹjọ ti wọn ti kọkọ pe fun eniyan tẹlẹ nu. Sugbọn, eyi ko tumọ si pe Woodberry ti bọ patapata nitori wọn le fi ẹsun miran kan an. Kini ẹjọ Woodberry ti wọn danu yii tumọ sí? Gẹgẹ bi alaye to wa ninu iwe to tẹ BBC lọwọ lati ọwọ agbẹjọrọ orile-ede Naijiria kan, Adetokunbọ Eribake Esq, ọrọ ile ẹjọ yii le tumọ si nkan meji: O ni: 'O le tumọ si pe awọn iha mejeeji n sọrọ lori bi wọn o ṣe yanju ẹjọ naa lai lọ ile ẹjọ, ki ijọba si wọgile ṣiṣe ẹjọ pẹlu Woodberry. Tabi Ki o jẹ pe awọn aṣiri ọrọ miran ti tu sita, ti o si nilo ki wọn wọgile ẹjọ akọkọ lati pe ẹjọ tuntun lodi si Woodberry. Ẹwẹ, koko to wa nibẹ ni pe ijọba wọgile ipẹjọ lodi si Woodberry lai ni ẹta inu, tumọ si pe, ijọba ni ẹsun tuntun ti wọn yoo fi kan an, eyi ni alaye Eribake. Hushpuppi Ramoni Abass gangan n wa n kọ? Gẹgẹ bi iroyin ṣe sọ Federal Bureau of Prison (BOP), Ramon 'Hushpuppi' Abbas ko si ni ọgba ẹwọn Chicago ti wọn fi si tẹlẹ mọ. Ẹwẹ, agbẹjọro Hushpuppi, GalPisseyzky sọ fun awọn akọroyin abẹlẹ pe wọn kan gbe onibara oun kuro ni ọgba ẹwọn Chicago lọ si ti Califonia ni, kii ṣe pe o ti kuro lẹwọn. Ṣé lóòtọ́ ni pé Hushpuppi ti kúrò ní ọgbà ẹ̀wọ̀n l'America? Ẹ wo àbájáde ìwádìí wa Iléeṣẹ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n ìlú Chicago sọ pé Hushpuppi kò sí ní ẹ̀wọ̀n MCC ní Chicago mọ́. Lootọ ni akọsilẹ wa lori itakun agbaye ajọ ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ ilẹ America, FBI, pe wọn ti tu ọmọ orilẹ-ede Naijiria, Hushpuppi ti wọn mu fun ẹsun jibiti, silẹ. Ṣugbọn akọsilẹ ti BBC ri arigbamu rẹ lori itakun agbaye ajọ ọgba ẹwọn nilẹ America, fihan pe Hushpuppi ko si ni ọgba ẹwọn ilu Chicago mọ, koda ogunjọ, oṣu Keje, ni wọn ti tu u silẹ. Amọ o, agbẹjọro fun Hushpuppi, Gal Pissetzky, sọ fun awọn akọroyin nilẹ America pe ko ti i gba itusilẹ, wọn kan gbe e kuro ni ọgba ẹwọn Chicago, lọ si ti California. Pissetzky, to jẹ agbẹjọro nilu Chicago, sọ fun awọn oniroyin pe, wọn ko ti i yọnda rẹ, ati pe oun ṣi ni agbẹjọro rẹ, tako iroyin kan to sọ pe Hushpuppi ti kọ ọ ni agbẹjọro. ""Pe wọn kọ ọ si ori iwe pe wọn ti tu u silẹ, ko tumọ si pe o ti di ominira. Gbogob nkan ti ẹ ba ri lori iwe ile ẹjọ kọ lo maa n jẹ 'otitọ' delẹ. Gal Pissetzky tó ń ṣojú Hushpuppi fẹ̀sùn ajínigbé kan FBI lórí ọ̀rọ̀ Ramọni Abass Ọsẹ diẹ sẹyin ni ọmọ Naijiria naa, ti ilẹ Amẹrika fi ẹsun ṣiṣe jibiti lori ayelujara kan, Ramon Igbalode, ti inagijẹ rẹ n jẹ Hushpuppi yọju sile ẹjọ lonii. Amọ adajọ to n gbọ ẹjọ naa, Jeffrey Gilbert, ẹni to wo igbẹjọ naa lati ori ayelujara ni Chicago kọ lati gba oniduro Hushpuppi. Alaye adajọ naa ni pe o lewu lati gba oniduru afurasi alujibiti ọhun nitori pe o le e fi ẹsẹ fẹ, ki wọn ma ri mọ. Adajọ Gilbert wa paṣẹ pe ki Hushpuppi si maa naju lọ lọgba ẹwọn na, titi ti wọn yoo fi fi oju rẹ ba ile ẹjọ fun igbẹjọ to yẹ, eyi ti yoo bẹrẹ ni California, ki ọdun yii to pari. Awijare agbẹjọro Hushpuppi, Pissetzky: Bi o tilẹ jẹ pe agbẹjọro Hushpuppi, Gal Pissetzky si n tẹnumọ pe ki wọn gba oniduro Hushpuppi, sibẹ ẹbẹ rẹ ko wọle leti adajọ. Pissetzky n rọ adajọ pe ko gba beeli onibara oun, ko si fun laaye lati maa gbe pẹlu ibatan rẹ kan to ni iyawo ati ọmọ, ti wọn yoo si maa tọpinpin rẹ. Agbẹjọro naa ni ""Ẹni ti gbogbo eeyan nifẹ si, ti wọn si n bọwọ fun ni onibara oun, gbajumọ eeyan ni."" Ṣugbọn ikọ olupejọ ni Amẹrika faake kọri lati gba ẹbẹ agbẹjọro naa pẹlu awijare pe Hushpuppi le salọ, ko si tun lọ lu jibiti miran lori ayelujara. Gal Pissetzky tó ń ṣojú Hushpuppi fẹ̀sùn ajínigbé kan FBI lórí ọ̀rọ̀ Ramọni Abass FBI jí Hushpuppi gbé ní Dubai ni- Agbẹ́jọ́rọ̀ Ramọni Igbalode Gal Pissetzky to n ṣoju fun Ramoni Abass Igbalode ba BBC sọrọ lori ohun to n ṣelẹ bayii lori ọrọ Hushpuppi. Loṣu kẹfa ni awọn agbofinro mu Ramoni Olorunwa Abbas lori ẹsun lilu jibiti lori ayelujara. ni orilẹ-ede Dubai. Awọn ọlọpaa Dubai ni wọn ba ogoji miliọnu dọla, ọkọ bọginni mẹtala to to miliọnu meje dọla din ni igba, kọmputa mọkanlelogun, foonu mẹtadinlaadọta ati awọn nkan mii mọ Hushpuppi lọwọ. Ile ẹjọ ni Chicago lo ti kọkọ foju han lọjọ kẹta, oṣu kejila lori ẹsun gabjuẹ. Gal ni oun ko fi bẹẹ mọ nipa ayelujara asiko yii ṣugbọn oun mọ pe wọn n pa owo to pọ lori ayelujara nitori pe awọn ọmọ oun ni oun ti dagba. O ni Hushpuppi ni awọn ero to le ni miliọnu to pọ to n tẹle lori ayleujara ni eyi to n pa owo wọle fun un. Agbẹjọro Pissetzky ni awọn FBI ji Ramoni gbe ni Dubai ni lai tẹlẹ awọn ofin ati ilana to yẹ ni kikun ki wọn to maa gbee bọ ni America. O ni awọn ọdọ pọ lori ayelujara ti wọn nifẹ Ramoni, ti wọn si bọwọ fun un. Àlàyé rèé lórí bí agbẹjọ́rò tó ń ṣojú Hushpuppi nílé ẹjọ́ ṣe pegedé sí Ẹ wo àwọn àmúyẹ ti gbajúmọ̀ agbẹjọ́rò tó fẹ́ ṣojú Hushpuppi nile ẹjọ ní Onileeṣẹ adani ni Hushpuppi, ọmọ Naijriia ti wọn fi si ọgba ẹwọn nilẹ Amẹrika, nitori ẹsun jibiti. Agbẹjọro Hush, Gal Pissetzky, lo sọ bẹẹ fun iwe iroyin Forbes, lasiko ifọrọwanilẹnuwo kan. Ọgba ẹwọn ijọba apapọ nilu Chicago, ni Illinois, lorilẹ-ede Amẹrika ni Ramoni Igbalode, wa lọwọlọwọ. Gbajugbaja ni agbẹjọro rẹ yii, nitori pe o ti ṣoju gbajugbaja akọrin to ti di oloogbe, Michael Jackson ri ninu igbẹjọ kan. Awọn nkan ti a mọ nipa igbeaye Gal Pissetzky Gal Pissetzky ti n ṣiṣẹ amofin fun ogun ọdun. Lati ibẹrẹ pẹpẹ iṣẹ rẹ lo ti nifẹ lati maa gbẹjọro fun awọn ti ijọba apapọ tabi ipinlẹ ba fi ẹsun iwa ọdaran kan. Ọgbẹni Pissetzky ti gbẹjọro bi igba ọgọrun, niwaju igbimọ igbẹjọ ati adajọ. Ọpọlọpọ ẹjọ to ta koko ni Pissetzky ti gba ro nile ẹjọ to gaju lọ nipinlẹ Illinois, ati ile ẹjọ kotẹmilọrun ijọba apapọ. Awọn ti agbẹjọro yii ṣaba maa n ṣoju ni awọn ti wọn ba fi ẹsun jibiti owo, jibiti ori ayelujara ati iwa ibajẹ nidi oṣelu. Awọn ẹsun miran to tun maa n soju fun ni lilu jibiti l'ẹka eto ilera, iditẹ, ipaniyan, rira ati tita oogun oloro, ifipabanilopọ, ati awọn ẹsun miran to l'agbara. Ilu Chicago ni ọfiisi Gal Pissetzky wa, ṣugbọn jakejado orilẹ-ede Amẹrika lo ti maa n ṣoju awọn onibaara rẹ. Awọn ede ti Gal Pissetzky gbọ Hebrew Polish Spanish Awọn ibi ti Gal Pissetzky ti ṣiṣẹ ri Pissetzky & Berliner, LLC (2006 si asiko yii) Meczyk & Associates (2002 - 2006) Cook County State's Attorney's Office (2000 - 2002) Awọn ileewe ti Gal Pissetzky lọ J.D., John Marshal Law School, Chicago (Law, 2000) B.A., University of Illinois, Chicago (Criminal Law and Political Science, 1997) Awọn ami ẹyẹ to ti gba Rising Star Super Lawyer™, 2011 Top 100 Trial Lawyers Association of Trial Lawyers of America, 2010 Top 100 Trial Lawyers Association of Trial Lawyers of America, 2009 Top 100 Trial Lawyers American Trial Lawyers Association, 2007 Cum Laude John Marshall Law School, 2000 Honors University of Illinois, Chicago, 1997 ""10 Best Client Satisfaction"" attorneys by the American Institute of Criminal Law Attorneys ""Top 100 Trial Lawyers: Illinois"" by The American Trial Lawyers Association O si ṣeeṣe k Ramoni Abbas Olorunwa, ko ṣe to ogun ọdun l'ọgba ẹwọn, ti ile ẹjọ ba fi sọ pe o jẹbi awọn ẹsun ti wọn fi kan an. Kemi Dairo: Iṣẹ́ abẹ nínú ọpọlọ àti ẹ̀rọ ni mo fi ń gbọ́ ọ̀rọ̀ báyìí",0,yoruba àlùfáà. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba "Diẹ lara itan ti Gloria Tayelolu Bright ẹni ọdun mẹtalelọgbọn sọ fun awọn oniroyin ree lẹyin to gba itusilẹ pada wale lati orilẹede Lebanon ti wọn tan an lọ ṣe owo ẹru. Ọmọ ilu Eruku ni ipinlẹ Kwara ni Gloria to si jẹ abiyamọ to ni ọmọkunrin kan ati ọmọbinrin kan to wa yọlẹ gbero lati lọ si Lebanon ko lee ko ọrọ jọ. Nigba ti wọn fẹ fa a le ajọ to n ri si igbẹjọ awọn ti wọn nko ṣe owo ẹru (NAPTIP) to wa ni ilu Oshogbo lawọn oniroyin ni anfani ati fi ọrọ wa a lẹnu wo. BBC Yoruba kan si oniroyin ti Gloria ṣipaya ọrọ yii fun o si fi aridaju han pe bẹẹ gẹlẹ lo ṣe ṣalaye nigba toun ni anfani ati fi ọrọ wa a lẹnu wo. Lebanon: Iṣẹ́ tí kòsí ní Naijiria, la ṣe lọ ṣe ọmọ ọ̀dọ̀ ní Lebanon Dipo ki wọn mu lọ si ileewe kan lati lọ maa ṣe olukọni gẹgẹ bi wn ṣe sọ fun mi ki n to kuro ni Ilorin, ọmọ ọdọ ni wọn n fi mi ṣe. ""Ohun to wa buru ju ninu ọ̀rọ̀ temi ni wi pe, ọga mi bẹrẹ si ni ta omi oge si mi. mo ṣe ohun gbogbo lati le e jina si mi ṣugbọn ṣe lo n kara mọ ọ si i. Mo ni lati pe e sẹgbẹ lọjọ kan lati jẹ ko m pe ko si ọkunrin mii to le ba mi lajọṣepọ ayafi ẹni to fun mi ni ilẹkẹ idi mi. O bere pe ki ni yoo ṣẹlẹ bi oun ba dan an wo? Kia ni mo sọ fun un pe ọkunrin to ba ṣe e yoo ya were fun ọjọ mẹfa yo si fo ṣanlẹ ku lọjọ keje. Lara rẹ ba walẹ wọọ fun igba diẹ temi naa si ni alafia"". Gloria ni bayii ni ilẹkẹ idi oun ṣe gba oun silẹ lọwọ ifipabanilopọ. ""Ṣugbọn aye mi ri radarada ti mo si nilo lati wa ọna abayọ ki n ma baa ku si ilẹ ajoji. Ọpẹlọpẹ pe mo ri i pe waya oju opo ayelujara wa ninu ile eyi lo jẹ ki n fi fidio iya to n jẹ mi ranṣẹ ti mo si gbọ pe o tan ka ori ayelujara to bẹẹ ti ajọ Phemic Life Support Foundation ni Ilorin ati olu ileeṣẹ wọn to wa ni Eko ati ilu London wa tu mi silẹ"". Ẹwẹ, a gbọ iroyin pe nigba ti ẹjọ naa kan ijọba ipinlẹ Kwara leti, ajọ NSCDC kan lu agbami iṣẹ iwadii ọwọ wọn si ti tẹ awọn afurasi kana: ara orilede Lebanon to jẹ ẹni ọdun mẹrindinlaadọrin kan. Wafic Hamze ati agbẹjọro kan, Taofeek Sanusi ti wọn si tun ni o ku Joseph kan to wa loke okun titi di ana, ọjọ kẹtadinlogun oṣu kinni. Ijba ipinlẹ Kwara ti fa Gloria le awn obi rẹ lọ́wọ́ ko to di pe aj NAPTIP naa bẹrẹ iṣẹ itẹsiwaju inu iwadii ki wọn to le fi ẹnikẹni jofin. Gloria ni ""mo fẹ gba awọn ọmọ Naijiria mii to ro pe paradise ni lilọ oke okun jẹ ki wọ́n ro o lẹẹmeji ki wọ́n tó kán lù ú"". O leè má mọ̀ bóyá o ní àrùn HIV/AIDS o! Wo àwárí akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ yìí",0,yoruba inú mi dùn mo jí sáyé mo jí sáyọ̀ mo jí síre èdùà kú iṣẹ́ ìyanu o,0,yoruba "Igbagbọ ọpọ ọmọ Yoruba ni pe Ọlọrun lo n se ọmọ, kii se eeyan, agbara iloyun ati ọmọ bibi si wa lọwọ Eledumare ọba to le se ohun gbogbo. Igbagbọ awọn eeyan yii si lo wa si imusẹ ninu aye gbajugbaja osere tiata lobinrin kan, Wumi Toriola. Bi o tilẹ jẹ pe Wumi se igbeyawo alarinrin, to si pẹ diẹ ko to fi inu soyun, ọpọ eeyan lo n lero pe o kan wu bẹẹ ni lai mọ pe isoro nla ni oserebinrin naa la kọja. Toriola, ẹni to bọ soju opo Instagram rẹ lati kede ayẹyẹ ọdun keji ti ọmọ rẹ de ile aye, wa lo anfaani ọjọ ibi naa lati kede fun araye nipa ọpọ isoro to la kọja, ko to di ọlọmọ nile aye. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ninu alaye rẹ, Wumi ni lẹyin ayẹyẹ igbeyawo oun, oun ati ọkọ oun pinnu lati sinmi diẹ naa, kawọn to bẹrẹ owo ọmọ bibi. Amọ nigba ti akoko isismi wọn buse ni wọn ba ko mọ isẹ ọmọ bibi sugbọn gbogbo aisun tọkọtaya naa tọsan toru lo ja si pabo, ti oyun ko si duro rara. ""Laarin osu mẹfa akọkọ ta pinnu lati loyun ni a ko fi gbọ ko amọ n ko tiẹ mọ lọran kankan nigba naa. Amọ nigba to di ọjọ kan, ni eeyan kan sọ fun mi pe se mo lero pe o rọrun lati finu soyun ni, sebi igbeyawo ni mo se yẹ, ki lo de ti n ko se tii loyun, to ba jẹ pe lootọ lo rọrun lati se bẹẹ."" Wumi ni igba yii gan ni oun to mọ ọrọ naa ni nnkan patak, ti oun si gba ile iwosan to wa fun oyun nini ati ọmọ bibi lọlati lọ se ayẹwo pẹlu ọkọ oun. Amọ o ni dokita fidi rẹ mulẹ pe saka ni ara oun ati ọkọ oun da, ti ko si si nkankan to n se idiwọ fun awọn mejeeji lati finu se oyun. ""Amọ sibẹ n ko lyun lẹyin ayẹwo yii, ti mo si tun lọ sibi ti wọn yoo ti se iranwọ lati fi ẹrọ kan gbe atọ ọkọ mi sile ọmọ mi, ti oloyinbo n pe ni Intrauterine Insemination. Ẹmeji ni wọn se nnkan yii fun mi, ti gbogbo rẹ si kuna, n ko gbọ pa, bẹẹ ni n ko gbọ ko. Amọ nigba to ya Ọlọrun lo sisẹ iyanu rẹ, ti mo si loyun, eyi ti mo fi bi ọmọkunrin to pe ọdun meji yii."" Wumi Toriola wa gba awọn ololufẹ rẹ to n woju Ọlọrun ninu igbeyawo wọn nimọran pe kii se awọn nikan lo n la iru isoro naa kọja. ""Aimọye miliọnu obinrin lo n ba isoro airọmọbi yii finra, amọ mase ri ara rẹ bi ẹni ti ko le finu soyun laelae nitori isẹ iyanu rẹ sun mọ itosi."" O tun wa rọ iru awọn eeyan yii wipe ki wọn mase fi oogun wọn sere, ki wọn si maa lọ sile iwosan loore koore, bẹẹ ni ki wọn maa gbadura si Ọlọrun nitori Ọlọrun to ya Wumi Toriola lẹnu, yoo ya awọn naa lẹnu.",0,yoruba BBC News Yorùbá | Fredrick Fasheun jáde láyé lẹ́yìn àìsàn ráńpẹ́ - https://t.co/H0jxyVJkjG,0,yoruba #love and #gratitude 2Things I know to be true🤗💙 Gistas mi ọwọn #ThankYou for making my special day EXTRA special. Mo dupẹ o🙏🏾 A ṣe m'ọdọn #yoruba #birthdaygirl https://t.co/OvSdo1pdtO,0,yoruba "Pupọ ninu awọn olori naa lo bọ sori ayelujara Instagram ati Facebook wọn, lati ki Kabiesi ku oriire, ti wọn si tun lo anfaani naa lati fi imọriri wọn han. Ko si sẹni ti yoo ka ọrọ ikinni naa, ti ori rẹ ko ni wu nipa kiki ati kiki tawọn ayaba naa se, eyi to n yonbo Ọba Adeyemi. Diẹ lara awọn olori to ki ọba Adeyemi ree ati ọrọ ikinni ti wọn fi n ki ọkọ wọn lawọn oju opo ayelujara wọn. Ayaba Mujidat Adeyemi: Aayo mi ni Ọba Adeyemi Ninu ọrọ ikinni tiẹ si Ọba Adeyemi, Ayaba Mujidat Adeyemi ni aayo oun ni Kabiyesi jẹ, ti yoo si ma a jẹ lailai. O ki Kabiyesi lorukọ rẹ ati ti awọn ọmọ rẹ pe - Kabiyesi, Oba Nla, Oba to nfi Oba je, Oba to ngba idobale Oba, Alowolodu bi iyere, afinju Oba ti lo golu. O wa gbadura pe ki Alaafin tubọ lo ọpọlọpọ ọdun lori itẹ awọn baba rẹ. Ayaba Sulat Motunrayo Adeyemi: Ọkọ mi ni ọkunrin to rẹwa julọ Ayaba Sulat Motunrayo Adeyemi sọ pe oun ati awọn ọmọ oun ba ọkunrin to rẹwa julọ, to jẹ oniwa jẹẹjẹ, ati ọlọyaya ku ayẹyẹ aadọta ọdun lori itẹ. O ni Ade a pẹ lori yin, irukẹrẹ a pẹ lọwọ yin, igba ọdun, ao jọ ma lo igba ni."" Ayaba Memunat Adeyemi: Alaafin lo ni kọkọrọ ọkan mi lọwọ Ayaba Memunat Adeyemi sọ pe, Akikanju ni Alaafin jẹ fun oun, ẹni to ni kọkọrọ to ṣi ọkan oun, ọkunrin pataki to ma n da oun lọrun ni gbogbo igba, ati baba awọn ọmọ oun. O ni ọpọlọpọ ayọ ni Kabiyesi ti mu wọ aye oun. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ayaba Folashade Adeyemi: Alekun ara ọkọ mi yoo maa pọ si Ayaba Folashade sọ pe oun ki Kabiesi ku ayẹyẹ aadọta ọdun lori itẹ, o si gbadura ki alekun ilera ati okun pọ si fun baba. Olori Damilola Adeyemi: Ọrọ ikini ti Olori Damilola Adeyemi fi ranṣẹ si Alaafin yatọ diẹ si ti awọn akẹẹgbẹ rẹ. O ni oun ni olori to jẹ oloriire julọ ni aafin Kabiesi, nitori pe wọn ko ti i bi oun nigba ti Alaafin jọba. Ṣugbọn oun ṣoriire pe oun jẹ ara awọn olori rẹ lasiko ayẹyẹ nla yii. ""Mo nireti pe olori rẹ ni ma a tun jẹ ti mo ba tun aye wa."" Ayaba Rukayat Abiodun Adeyemi: Baba to nifẹ ọmọ ati ọkọ to nifẹ aya ni Alaafin Ayaba Rukayat Abiodun Adeyemi ṣapejuwe asiko Alaafin lori oye pe, o ti mu ọpọlọpọ ibukun, idagbasoke ati alaafia wa silu Ọyọ ati awọn ilu to wa ni abẹ rẹ. ""Baba lo jẹ fun mi, ọkọ to ni ifẹ aya, ati awokọṣe fun awọn ọmọ mi."" O gbadura pe ki Allah da ẹmi Kabiesi si ninu ọrọ ati ilera to peye, fun idagbasoke ilu Ọyọ ati agbagbe rẹ. Wo ìdí tí Alaafin fi ṣún ayẹyẹ àádọ́ta ọdún tó gorí ìtẹ́ síwájú Yoruba ni bi ọọdẹ ko ba dun, bi igbẹ nilu n ri, bi ilu ko ba si dun pẹlu, ko si ọmọ talaka ti yoo le rode ẹmu. Bẹẹ lọrọ ri pẹlu isọri keji ọwọja ajakalẹ arun Coronavirus to tun gbode bayii, eyi to n se akoba feto ọrọ aje, to si tun n se idiwọ fun ọpọ ayẹyẹ ni sise. Lọwọ lọwọ bayii, arun naa ti se idiwọ fun Alaafin tilu Oyo, Ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi lati sami ayẹyẹ aadọta ọdun to gori itẹ awọn baba nla rẹ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ayẹyẹ naa, to yẹ ko bẹrẹ lonii ọjọ Aiku ni wọn ti kede pe ko ni le waye mọ nitori awọn idi kan to da lori bi ọwọja arun Covid-19 se n ja kiri ilu. Bi o tilẹ jẹ pe eto lati sami ayẹyẹ aadọta ọdun ti ọba alaye naa gba ade, ti debi to lapẹrẹ, ti wọn si ti fi iwe pe ọpọ awọn eeyan jankanjankan lati peju sibi ayẹyẹ naa, sibẹ ayẹyẹ naa ko lee see se lasiko yii. Atẹjade kan to wa lati aafin Oyo, ti Iku Baba Yeye funra rẹ fọwọsi salaye pe lootọ ni oun ti seto ayẹyẹ idupẹ alarinrin amọ oun fẹ tun ero oun pa lori igbasẹ naa. ""Pẹlu irora nla ninu ọkan mi ati aabo fun ẹmi eeyan, ni mo fi rọ awọn Oyomesi lori idi ta fi gbọdọ sun ayẹyẹ naa siwaju titi di ọjọ mii, ọjọ re, ti arun Coronavirus yoo kasẹ nilẹ. Lara awọn idi ti mo si se gbe igbesẹ irora naa ni lati bọwọ fun ofin itakete sira ẹni pẹlu bi yoo se nira lati gbalejo lati ilẹ okeere , ti wọn si gbọdọ lo ọsẹ meji ni yara iseraẹnilọjọsi ki wsn fara kinra pẹlu ẹlomiran, eyi to le ma see se."" Alaafin wa kede pe aabo ẹmi awọn eeyan lo jẹ oun logun ju ayẹyẹ ki ayẹyẹ lọ, idi si ree ti oun ko fi ni se ayẹyẹ aadọta ọdun ti oun gba ade, ọlọsẹ kan ọhun mọ.",0,yoruba "lòdì Àbẹ́òkúta. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ài: ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi.",0,yoruba ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọmọ lo ojú odò.,0,yoruba "Ona lo jin, eru ni baba. #proverbs #Yoruba",0,yoruba ri pe dara gan wey ti o nuni ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó wáyé.,0,yoruba "Ọ̀pá ò lè pa agogo, abínú ẹni ò lè pa kádàrá dà. Dámidámi ariwo kì í pa alámàlà, ẹnu ayé ò ní pa mí. Mo ṣẹ́gun oṣó. Mo ṣẹ́gun Ajé. Mo ṣẹ́gun aláròká. Mo ṣẹ́gun àìbẹ́gbẹ́pé. Mo ṣẹ́gun gbogbo. Mo di AṢẸ́GUN. Ẹ kú ọjọ́ Ìṣẹ́gun o!",0,yoruba afi ki olohun gba wa lowo won ẹ̀yin ìjọba ẹ yẹ ira yín wò o |,0,yoruba tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tó gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ àti ìbi tí wọn wà.,0,yoruba "gbé lọ yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba Irinkerindo Ninu Igbo Elegbeje - D.O. Fagunwa https://t.co/HNSRfR8Pqj,0,yoruba "Olúṣẹ́gun Ọbásanjọ́ , tí ó jẹ́ Ààrẹ ìjọba ológun àná ( láti ọdún 1976 sí 1979 ) , tí ó sì tún ṣe Ààrẹ ìjọba alágbádá tí ìbò gbé wọlé ( ní ọdún 1999 sí 2007 ) , kúndùn láti máa bu ẹnu àtẹ́ lu àwọn ètò ìjọba Ààrẹ orílẹ̀ - èdè Nàìjíríà tí ó jẹ tẹ̀lé e .",0,yoruba Ilu Eko la fi ikale ajinde odun yii si oya e je ka lo *ijo*,0,yoruba ọrọ̀ àìmọ́. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba "Olùwo lọ. Nitori eyi, ara eni lo ni àṣà yorubá eyti o gbe lori àìmọ́ kọ.",0,yoruba "Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ alága PTF lórí Covid-19, Boss Mustapha ló buwọ́lu ìwé náà tí ó fi gbé nọ́mbà ìwé ìrìnà àwọn ènìyàn náà síta lójú òpó Twitter rẹ. Ó ní àwọn ọgọ́rùn náà ni wọ́n kọ̀ láti tẹ̀lé òfín ìrìn àjò láti ilẹ̀ òkèrè pàápàá jùlọ láti lo oṣẹ̀ kan lẹ́yin ti wọ́n ṣe àyẹwo Covid -19 ki wọ́n tó rìnrìn àjò. Oṣù mẹ́fà gbáko ni wọ̀n kò fi ni le rìnrin ajo, bẹ̀rẹ̀ láti Ọjọ́ Kíní, Oṣù Kíní sí ọgbọ̀n ọjọ́, Oṣù kẹfà, ọdún 2021, èyí túmọ̀ sí pé, àwọn ènìyàn yìí kò ni lé kúro ni Nàìjíríà ní gbogbo àsìkò yìí Ìgbìmọ̀ PTF fikuN pé àwọn ti fi ọ̀rọ̀ náà tó àwọn ti ọ̀rọ̀ kàn létí, àti pé wọ́n kò ni le fi ìwé ìrìnà náà rin ìrìn àjò lọ sí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Ìgbìmọ̀ ọ̀hún ti sọ sáájú pé, àwọn yóò dá ṣẹ̀ríà fún àwọn ti kò bá tẹ̀lé àwọn ìlànà Covid-19 àti pé ọwọ́jà ààrùn Covid-19 ẹlẹ́kèejì ni Nàìjíríà ń bá fíra lọ́wọ́. Lọ́wọ́lọ́wọ́, ọ ti lé ni ẹgbẹ̀rún márùndíláádọ́rùn ènìyàn tó ti ni ààrùn náà ni Nàìjíríà gẹ́gẹ́ bi àjọ NCDC ṣe sọ",0,yoruba ẹkọ́ ṣẹlẹ ni Lagos ti gbogbo eniyan sọ o ṣe pataki. (2024),0,yoruba "Èyí yòó wáyé lẹ́yìn ìpàdé tí wọ́n ti kọ́kọ́ ṣe l'óṣù Kejìlá, ọdún 2016, lásìkò tí Ọba nàá ṣàbẹ̀wò sí Nàìjíríà. Agbẹnusọ fún Ààrẹ Buhari, Garba Shehu tó fi ìkéde nàá síta lójú òpó ìkànsíraẹni Twitter rẹ̀, sọ pé, Ọ̀ba Morocco, Mohammed Kẹfa, ló ránṣẹ́ pe Buhari. Níbi ìpàdé ọ̀hún tí yòó wáyé ní Rabat, nìrètí wà pé , àwọn olórí méjéèjì yòó ti jíròrò lórí ọ̀nà láti ró àdéhùn tó wà láàrin orílẹ̀-èdè méjéèjì, lórí ẹ̀ka tó n pèsè ajílẹ̀, lágbára. Buhari: Sáà kan ṣoṣo loó máa lò látìsinyìí lọ 'Ọpọ̀ ẹ̀mí èèyàn ló bọ́ lọ́wọ́ Abacha láàrín 1993 sí 1998' Ẹ̀wẹ̀, ìkéde nàá tún sọ pé wọn yòó sọ̀rọ̀ lórí ètò ẹ̀kọ́, àti iṣẹ́ àkànṣe afẹ́fẹ́ gáàsì tó pa orílẹ̀-èdè méjéèjì pọ̀. Èyí yòó wáyé lẹ́yìn ìpàdé tí wọ́n ti kọ́kọ́ ṣe l'óṣù Kejìlá, ọdún 2016, lásìkò tí Ọba nàá ṣàbẹ̀wò sí Nàìjíríà. Lára àwọn tí yòó kọ́wọ̀ọ́rìn pẹ̀lú Ààrẹ Buhari ni gómìnà ìpínlẹ̀ Ebonyi, Dave Umahi, àti akẹgbẹ́ rẹ̀ láti ìpínlẹ̀ Jigawa, Abubakar Badaru.",0,yoruba "Atẹjade kan ti akọwe ijọba apapọ, Boss Mustapha fisita lo sisọ loju ọrọ yii pẹlu afikun pe Agbefọba agba fun ijọba ilẹ wa, Dayọ Apata ni yoo maa dari igbimọ to n gba dukia ijọba to sọnu pada naa, titi di ọjọ miran, ọjọ rere. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Akọwe ijọba apapọ ni aarẹ Buhari gbe igbesẹ naa lọna ati fun Obono-Obla ni anfaani lati dahun awọn ẹsun iwa ọdaran to nii se pẹlu iwa ajẹbanu ti ajọ to n tanna wadi iwa ibajẹ ICPC fi kan-an. Bakan naa, Obono-Obla yoo tun jẹjọ lori awọn ẹsun to jẹ mọ sise ayederu iwe ẹri ati ẹsun iwa ajẹbanu lọkan o jọkan eyi ti wọn fi kan-an. Atẹjade naa tun salaye pe, Obono-Obla yoo si maa naju nile naa titi ti ajọ ICPC yoo fi fẹnu ọrọ jona lori iwadi to n se fun-un.",0,yoruba kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ìyá lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó dára púpọ̀.,0,yoruba "RT @user: Kabio osi, Ekun Oko farao! RT @user: Ọba tí kìí sùn. Ọba tó jẹ́ pé bó ti wù Ú ní í ṣolá Ẹ̀.",0,yoruba Kashimawo Laloko: Gbajúgbajà akọ́nimọ̀ọ́gbá eré bọ́ọ̀lù Laloko tó ṣàwárí Mikel Obi àti Osaze dágbére fáyé,0,yoruba "Ẹgbẹ Boko Haram ti fi adooloro kọlu Unifasiti Maiduguri ni ọpọigba lẹyin Bakannaa ẹgbẹ naa si tu awọn iyawo ọlọpa mẹwa to jigbe silẹ leyin igba ti ileese ọtẹlemuyẹ Naijiria ati Igbimọ ICRC ton sẹ iranwọ f'awaọn t'ajalu ba f'ọrọjomitoro ọrọ pẹlu Boko Haram naa . Atẹjade naa sọ wipe aarẹ Muhammadu Buhari lo pasẹ pẹ ki ileesẹ ọtẹlẹmuyẹ Naijiria ko kansi Boko Haram naa. Igbimọ ICRC lo se alarina ijiroro laarin ileese ọtẹlẹmuyẹ Naijiri ati ẹgbẹ Boko Haram naa. Ọgbẹni Garba Shehu sọ wipe awọn eeyan mẹtala ti won tusilẹ naa wa lọwọ ileesẹ ọtẹlẹmuyẹ Naijiria, ati wipe awọn ọmọogun Naijiria tin gbe awọn eniyan naa losi Abuja. Shehu se afikun wipe inu aarẹ Buhari dun si itusilẹ yi, o si ke pe awọn ọmọogun Naijiria ati ileese DSS wipe ki wọn mura si se lati ri wipe awọn akekọbirin Chibok ti Boko Haram jigbe padawa si ile.",0,yoruba "My Philadelphian student just changed his name to #Yoruba. You need to hear how he pronounces his Olúwanífẹ̀ẹ́mi so perfectly. Àwọn ọmọ Yorùbá míìn ò lè dá pe orúkọ wọn o, some still make English names dominant for their children. Èdùà ò ní jẹ́ kó pẹ́ kó tó yé e yín o",0,yoruba ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Alàji lo ni ẹ̀ká àwẹ eyti o gbe lori ọ̀run dídì.,0,yoruba "Kọ orukọọ̀ rẹ sápá òsì, kọ #email sápá ọ̀tún, yan #yobamoodua #BestTopicalBlog Fi ránṣẹ́. Gbẹ̀sì bí o kò bá kópa nínú #nomination tẹ́lẹ̀",0,yoruba nile ka ilú tó ti dá lẹ̀ni nilo.,0,yoruba "Bolsonaro sọ̀rọ̀ báyìí ní ọjọ́ náà pé “ ó yẹ kí o jáde síta láti lọ jẹ koríko pẹ̀lú àwọn alálẹ̀ẹ yín """""""" .",0,yoruba "Olori orilẹede Naijiria tẹlẹ ri, ajagunfẹhinti Ibrahim Babangida ti ṣapejuwe Naijiria gẹgẹ bi orilẹede to ṣoro lati dari. Babangida fọrọ yii lede lasiko tawọn alaṣẹ ẹgbẹ oṣelu PDP kan sii nile rẹ niluu Minna, ni ipinlẹ Niger. Babangida tun lo anfani naa lati kepe awọn aṣofin gbọdọ ṣiṣẹ takuntakun lati rii wi pe orilẹede Naijiria wa ni iṣọkan. O ṣalaye pe, gbogbo ohun to n ṣẹlẹ ni Naijiria ni oun n fi ọkan ba lọ, to si gbe oṣuba kare fawọn alaṣẹ ile igbimọ aṣoju ṣofin l'Abuja, adari ile ati gbogbo ile lapapọ. O rọ wọn wi pe, ki wọn maa kaarẹ ninu akitiyan lati ri wi pe Naijiria toro, nitori oriiṣiriiṣi erongba lawọn ọmọ Naijiria ni eyi to jẹ ko ṣoro fun awọn alaṣẹ lati dari. Babangida fun wọn ni idaniloju pe, oun wa pẹlu wọn ninu igbesẹ wiwa ilọsiwaju fun orilẹede Naijiria. O tun gba wọn nimọran pe, ki wọn mase gbagbe lati mu awọn ileri ti wọn ṣe fawọn to dibo yan wọn lẹkun ti wọn n ṣoju sẹ, nibayii ti wọn ti wa nile aṣofin l'Abuja.",0,yoruba nípa ìwà: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba mo fẹ́ràn àdìrẹ rẹ kọ́ ̀bá meaning i like your patterned skirt pls,0,yoruba Àwọn àmì-ìwé Epiphany,0,yoruba "Nígbà tó kún jú, àwọn ènìyàn ni ó pa Ọmọ lo ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.",0,yoruba "Àgbà ò sí ìlú bàjẹ́, Áwò kú, a gbàgbé ìlànà tí ó là á lẹ̀, a ò rántí bí ìṣàgbẹ̀ ti fa orílẹ̀ èdè Nàìjíríà sókè níjọ́hun àná. #IjoOle",0,yoruba "Bí kò bá fún ẹ ṣe, wà á sì wá obìnrin mìíràn lọ. Àwọn agbélé pawó pọ̀ nígboro, wọ́n ń wá oníbàárà. #marchagainstrape #IWD14",0,yoruba eḳọ nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o nuni ti o nuni ti o nuni ti o pẹ jú nìlọ̀ ni ọ̀nà tí ẹ̀ọ́ kan máa ń gbé ìyẹ̀ alẹ́.,0,yoruba ẹ káàárọ̀ o ọjọ́ ire o,0,yoruba RT @user: @user Eyin ori tabili,0,yoruba "Àwọn Dókítà àti àwọn onímọ̀ ìjìnlẹ̀ sì ń ṣe ìwádìí àti ìfọ̀rọ̀jomitoro - ọ̀rọ̀ lórí ohun tí ó lè jẹ́ orísun àrùn tí wọ́n mọ̀ nígbà náà lọ́hùn - ún gẹ́gẹ́ bí kòkòrò àìfojúrí kòrónà ti Wuhan , tí ó padà wá ṣe okùnfà COVID - 19 , kòkòrò àìfojúrí tó ń mú kí ènìyàn má leè mí sókèsódò tí ó sì ń fa àrùn ẹ̀dọ̀fóró .",0,yoruba "Kábiọ́òsì! Ọpẹ́ pé mo jí ire, ẹsẹ̀, ọwọ́ ṣe é gbé. O ṣeun Baba. Pa ọ̀nà mi mọ́ lónìí àti ọjọ́ gbogbo #amin #ase. Alààyè ni kó #RETWEET èyí.",0,yoruba maa jaye ori mi mi o meyin ola o king sunny ade,0,yoruba "fẹ. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba @user @user Óyá ẹ sọ fún wa o.,0,yoruba "jú, àwọn ènìyàn ni ó pa Ìyá lo ni ìgbà mi owó àkokò, Ìyá lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà.",0,yoruba èrò àti àsà tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa àwọn ènìyàn: ti o nuni ti o ní wúlò.,0,yoruba èkó aṣà. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba # SexForGrades : Ètò Alálàyé - afẹ̀ríhàn tú àṣìírí ìwà ìyọlẹ́nu ìbálòpọ̀ ní àwọn Ifásitìi Ìwọ - oòrùn Ilẹ̀ - Adúláwọ̀,0,yoruba "Oyo local government: ALGON, Makinde sọ ọ̀rọ̀ ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí ọ̀nà àti Awọn alaga naa ni, ijọba Seyi Makinde setan lati san gbogbo owo oṣu ati ajẹmọnu awọn fun iye ọdun to ku, to yẹ kawọn fi pari saa awọn gẹgẹ bii alaga kansu, eyi tii se ara ilana ati pana aawọ naa, ṣugbọn awọn ko fẹ bẹẹ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Lọjọ Ẹti ni iwe kan n fẹ kiri loju awọn opo ikansiraẹni lori ayelujara pe ijọba ipinlẹ Ọ́yọ ti fi iwe ransẹ si agbẹjọro awọn alaga kansu naa, Algon, pe oun setan lati san gbogbo owo osu ati ajẹmọnu wọn, ki wọn si maa ba tiwọn lọ. Alaga ẹgbẹ awọn alaga kansu, ALGON naa, Ọmọọba Abass Alẹṣinlọyẹ, to ba BBC News Yoruba sọrọ ṣalaye pe, kii ṣe owo ni awọn n fẹ bikoṣe titẹle ilana ofin nipa pipari saa awọn to ku, gẹgẹ bii alaga kansu nipinlẹ Ọyọ. Amọ ninu ọrọ to ba ileeṣẹ BBC news Yoruba sọ, agbẹnusọ fun gomina ipinlẹ Ọyọ, Ọgbẹni Taiwo Adisa ni, gẹgẹ bii ijọba ti ko fẹ wahala, to si fi oju woo pe ati tọtun, ati tosi, ọmọ ipinlẹ Ọyọ ni gbogbo wọn, lo mu ki ijọba gbe aba alaafia naa kalẹ. O ni ninu aba naa nijọba ti gba lati san awọn nnkan kan fun awọn alaga kansu naa, nitori ala ti ko lee sẹ ni igbiyanju wọn lati pada si ọọfisi bii alaga kansu, to si ni ki wọn tu itọ rẹ danu pe eyi yoo ri bẹẹ. Bẹẹ ba gbagbe, lọdun 2019 ni ijọba ipinlẹ Ọyọ fa awọn alaga kansu latinu ẹgbẹ oselu APC, labẹ saa ijọba ana lọ sile ẹjọ pe, ki ile ẹjọ ka wọn lapa ko, ki wọn si maa pada si ipo alaga mọ. Fire Eater: Azonto ní àfojúṣùn òun ni láti lọ fi idán iná yìí pa owó lókè òkun Ijọba ipinlẹ Ọyọ ni, eto idibo to gbe awọn alaga kansu naa wọle tako ofin, niwọn igba ti ile ẹjọ ti ni ki wọn nisuuru ki wọn gbọ ẹjọ wọn tan, ki wọn to ṣe idibo ọhun nigba naa. Eleyi ni wọn fa titi, ki ile ẹjọ to gba wọn laye lati lọ yanju ọrọ naa ni tubi inubi laarin ara wọn. Ireti ọpọ ni pe, igbesẹ naa yoo tete mu ki alaafia waye lori ọrọ naa; amọṣa ọrọ ko fẹ jọ bẹẹ bayii, kaka ki ewe agbọn aawọ ọhun si dẹ, ko ko ko lo n le si. Ko si idi meji fun eyi, ju iroyin kan to n lọ kaakiri pe ijọba ipinlẹ Ọyọ ti na ọwọ alaafia si ẹgbẹ awọn alaga kansu naa, ALGON. Ni ọjọ Ẹti lawọn alaga kansu ọhun kọkọ gba ile ẹjọ lọ, lati fi to ile ẹjọ giga ipinlẹ Ọyọ leti pe awọn ti tẹwọgba eto ti ijọba fi silẹ fun yiyanju aawọ naa, ṣugbọn awọn ko tii yiri rẹ wo. Kò sí ǹkan tó ń jẹ́ ọ̀rọ̀ ìgbàgbọ́ tàbí ìmọ̀le nínú àgbékalẹ̀ Amotekun - Alake ti Egba",0,yoruba "Onigbodogi ati Alape ni ọlọkọ to wa Temitọpẹ wa sile aye lọdun 1973, ṣe wọn ni ọmọ Ibadan ti ko ba ni agboole ati oko kii ṣe ojulowo ọmọ Ibadan. Ileewe alakọbẹẹrẹ St Michael Primary School, Yemetu ati I.M.G Primary School, Beyerunka, Alafara Oje ni Temitọpẹ lọ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Lẹyin naa lo gba ileewe girama Ikolaba Grammar School, St Luke's College, Molete ati Alugbo Comprehensive High School, Egbeda lọ, ti gbogbo rẹ ni ilu Ibadan. Sugar gba iwe ẹri olukọni onipo kini ni ileewe ẹkọṣẹ olukọni NCE Federal College of Education, to wa ni Osiẹlẹ nilu Abeokuta, ipinlẹ Ogun, ki o to lọ si ileewe giga fasiti Ibadan lati gba iwe ẹri imọ ijinlẹ akọkọ, B.Sc, ati iwe ẹri imọ ijinlẹ keji. Sugar fara gba ọta ibọn ni lalupọn lasiko idibo lọjọ abamẹta Kansilọ ni ijọba ibilẹ Ọdẹda lo fi bẹrẹ irinajo oṣelu rẹ. Wọn yan an gẹgẹ bii amugbalẹgbẹ fun ijọba ipinlẹ Ogun lasiko iṣejọba Ọtunba Gbenga Daniel. Lẹyin to ti jẹ olori ẹka ọdọ fun ẹgbẹ oṣelu PDP ni ẹkun idibo apapọ aringbungbun ipinlẹ Ogun, lo wa lọ du ipo alaga ijọba ibilẹ Lagelu ni ipinlẹ Ọyọ ni ọdun 2007. Ile iwosan nla UCH ni ilu Ibadan lo ku Ni ọdun 2011, ni wọn fi ibo yan an si ile aṣofin ipinlẹ Ọyọ labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu Accord, ki o to wọle gẹgẹ bii ọmọ ile igbimọ aṣoju-ṣofin to n soju ẹkun idibo Lagelu/Akinyele, labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu APC. Ni ọdun 2018 lo darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu ADP lati du ipo Sẹnetọ ki o to fidirẹmi. Ile iwosan nla UCH ni ilu Ibadan lo ku si ni ọjọ kẹsan oṣu kẹta ọdun 2019, lẹyin ti o fara gba ọta ibọn ni agbegbe Lalupọn lasiko idibo sipo gomina to waye nibẹ.",0,yoruba asa yoruba ni o make itumo ju lo ni gbogbo aye,0,yoruba Fún ìpe pàjáwàrì pe 112 @user RT #Nigeria,0,yoruba "Bí àwọn CNN - FDD ṣe gbé oyè náà ní yẹpẹrẹ tó ipò agbára Nkurunziza gẹ́gẹ́ bí adarí ayérayé tó ga jù ti jẹ́ kí ó nira fún ẹnikẹ́ni láti kọ ohunkóhun tí ó bá yàn láti ṣe , títí mọ́ ìgbésẹ̀ rẹ̀ láti ṣe àyípadà òfin sáà méjì fún ipò adarí tí ó wà nínú ìwé òfin orílẹ̀ - èdè náà .",0,yoruba "Máràfá tún tẹ̀síwájú pé ilé - isẹ́ FCTA tó ń mójútó ètò ẹ̀kọ́ tí pinnu láti bẹ̀rẹ̀ ètò ẹ̀kọ́ nìpa lílo ìmọ̀ ẹ̀rọ ayélujára , tí wọn yóò sí máa lo ẹ̀rọ móhùn - máwòrán láti máa fi kọ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ní ètò ẹ̀kọ́ lásìkò ètò kónílé - gbélé yìí .",0,yoruba "Nígbà tí Ọmọ fè se, Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé.. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..",0,yoruba "Ojú òpó Instagram rẹ̀ ni Oluwo ti Ìlú Iwo ti bu ẹnu àtẹ́ lu bí àwọn kan se da lẹ́bi lórí ìtúká ìgbéyàwó rẹ̀. Ojú òpó Instagram ni Oluwo ti Ìlú Iwo ti bu ẹnu àtẹ́ lu bí àwọn kan ṣe dá a lẹ́bi lórí bí ìgbéyàwó rẹ̀ pẹlu olori naa ṣe túká. Eyi ko sẹyin bi awọn kan ṣe n bu ẹnu atẹ lu ọba naa lori ẹrọ ayelujara lori bi o ṣe tu igbeyawo naa ka pẹlu Chanel Chin. End of Instagram post, 1 Oluwo ni oun gbiyanju titi oun ninu igbeyawo naa, ati wi pe ki iya to jẹ oun jẹ ẹnikẹni to ba da oun lẹbi. O ni bi oun ba ṣe ibi ninu idapọ to ṣẹṣẹ tu ka yii, ki Ọlrun da oun lẹjọ ṣugbọn bi oun ba jẹ olododo ki Ọlọrun jẹ ki oun pẹ titi lae. Laipẹ yii Oluwo ti Ilu Iwo, Ọba Rasheed Akanbi jajatuka pẹlu iyawo rẹ ti awọn mejeeji si taun si ara wọn lori ẹrọ ayelujara.",0,yoruba lo lọ. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó ṣe pàtàkì.,0,yoruba "Atótó Arére! K'éku ilé ó gbọ́ k'ó wí fún t'oko, kí àdán ó gbọ́ 'ó rò fún òdẹ̀ wípé Ààrẹ @user yóò máa fojúrinjú pẹ̀lú àwọn oníròhìn. 1",0,yoruba owo ṣẹlẹ ni Lagos ti gbogbo eniyan sọ o dara. (2000),0,yoruba ise si po nle sugbon a dupe lowo oloun pe a tie ri ojo yii,0,yoruba "Àwọn orílẹ̀èdè mẹ́tà ní wọ́n jọ fọwọ́sowọ́pọ̀ láti buwọ́lú iwé àdéhùn láti ri wí pé wọ́n dá owó náà pádà. Eyi ko ṣẹyin bi ilẹ Amẹrika ṣe fi si oju opo ikansiraẹni ile iṣẹ wọn to wa ni Naijiria. Ọgọọrọ owo naa ni wọn lu ni jibiti nipasẹ ile owo ifowopamọsi to wa ni ilu Jersey, ni orukọ Doraville Properties Corporation, ti wọn fi orukọ ọmọ aarẹ Naijiria nigba kan ri , Ọgagun Sani Abacha gbe kalẹ. Ni ọdun 2014, ile ẹjọ giga ni Washington DC, ni ilẹ Amẹrika gbe ẹsẹ le owo orilẹede Naijiria ti wọn lu ni ponpo lọdun 1993 si 1998, labẹ Ọgagun Sani Abacha. Ọgagun Sani Abacha ati awọn ẹmẹwa rẹ ji owo iluto le ni ọgọrun un miliọnu dọla ti owo ilu lasiko ijọba rẹ, eleyii to ṣe akoba fun ọpọlọpọ awọn ọmọ Naijiria. Awọn ẹbi rẹ pẹlu ọmọ rẹ Ibrahim ati Mohammed Babangida lo parapọ lu owo ilu naa ni ponpo. Lati ilẹ Amerika, Ilẹ Gẹẹsi, Faranse, Germany, Switzerland, Lichtenstein ati Luxembourg wa lara awọn orilẹede ti wọn fi owo ilu ti wọn lu ni ponpo si. Igbesẹ ti awọn orilẹede mẹta gbe naa jẹ ọkan gboogi ti ibaṣepọ laarin Naijiria ati ilẹ okeere yori si,pẹlu bi wọn ṣe mura lati da owo ilu ti wọn lu ni ponpo pada. Bakan naa ni ijọba Naijiria sọ wi pe awọn yoo gbe igbimọ dide lati ṣe ayẹwo awọn eto idagbasoke ilu ti wọn pinnu lati fi owo naa ṣe lẹyin ti wọn ba da a pada. Awọn ile iṣẹ to n ri igbelarugẹ awujọ ko ni gbẹyin lati pese awọn ohun ti ijọba orilẹede Naijiria nilo lati mu ayipada ba awọn ẹka eto iṣẹ akanṣe, imọ ẹrọ, igbogun ti iwa jẹgudujẹra ati lilọ si oke okun ni ọna aitọ.",0,yoruba Òyó. Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.,0,yoruba "gbogbo àwọn ènìyàn wà ní ìbàdandun, àwọn ẹ̀kọ́ ọmọ aláwọ̀ wà níṣẹ̀.",0,yoruba "Amọ eyi ko ri bẹẹ pẹlu isẹlẹ kan to n waye lori ayelujara eyi tawọn eeyan n gba bii ẹni gba igba igba ọti, ti wọn si n tutọ si ara wọn loju lori ọrọ ẹsin. Ohun to sokunfa isẹlẹ yii ni ti ijọ ẹsin Islam kan, Ahbaab li-Islam pẹlu ajọsepọ Markazu Ahbaab Uloomudeen to fẹ se isin oru abiyi taa mọ si lailatul Quadir. Ijọ naa ti Fadheelatul Ustaz Alhaji Habeebulah se alakoso rẹ, lo wa ladugbo Iju Ishaga nilu Eko, ti isin oru abiyi naa yoo si waye ni ọjọ Keje osu karun taa wa yii, laago mẹwa owurọ. Amọ ohun to wa jẹ iyalẹnu fawọn ọmọ Naijiria to ri iwe ipe ti wọn fisita fawọn alejo, ni bi wọn se ni Wolii ati Ojisẹ Ọlọrun Oladele Ogundipe, ti ọpọ eeyan mọ si Wolii Genesis, ni alejo pataki nibi eto naa. Iwe ipe yii ni Suphian Opeyemi Sodiq fi soju opo Facebook rẹ. Bẹẹ ba gbagbe, awuyewuye waye laipẹ yii nipa Wolii Genesis ati ẹsun ti obinrin kan fi kan pe o gba owo lọwọ oun lati fi ra ilẹ amọ ti ko ri owo ati ilẹ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọrọ yii lo di tile ẹjọ, ti wolii Genesi si lo osu meje lọgba ẹwọn, ki wọn to gba beeli rẹ laipẹ yii. Haa, ki ni eleyi si lo n gba ẹnu ọpọ eeyan lori ayelujara to ri iwe ipe naa. Ọpọ ọmọ Naijiria to si fesi lori isẹlẹ naa lo koro oju si igbesẹ pipe wolii wa sibi isin musulumi nigba ti awọn eeyan miran ni ko si ohun to buru ninu rẹ. Ni ero awọn ọmọ Naijiria to da si ọrọ naa, wọn ni igbesẹ naa tako ẹsin Islam pupọ, nitori oru abiyi ni ọwọ ju ọwọ ti wọn fi mu yii lọ. Koda, Rashady Oladele lero tiẹ ni se lo yẹ ki wọn fi iya to jopin jẹ ẹni to se iru eyi, ti awọn miran si lero pe tori owo ni wọn se hu iwa naa.",0,yoruba Davido: Àpètàn orukọ̀ ọmọ tuntun náà ní David Adedeji Ifeanyi Adeleke,0,yoruba ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba "Danjuma , tí ó jẹ olórí àwọn ológun , tí o si tún jẹ́ mínísítà fún ètò abo ní ìgbà kan rí , bu ẹnu àtẹ́ lu ẹgbẹ́ ológun bí wọ́n ṣe ń gbé lẹ́yìn apá kan dá apá kan sí nínú aáwọ̀ tí ó wáyé láàárín àwọn darandaran àti àgbẹ̀ , pàápàá jù lọ èyí tí ó wáyé ní ilée rẹ̀ tí í ṣe ìpínlẹ̀ Taraba .",0,yoruba "Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu baba kan, to de ọmọ rẹ, Ibrahim Lawal, mọlẹ sinu ile rẹ fun odidi ọdun mẹẹdogun gbako. Alabagbele ọmọkunrin naa ni agbegbe Shekar Dan Fulani, nijọba ibilẹ Kumbotso nilu Kano salaye pe, iya ọmọ naa ko gbe pẹlu wọn ninu ile. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Dan Fulani ni gbogbo aayan awọn aladugbo naa lati ẹyin wa, lati doola ẹmi ọmọkunrin naa, lo n ja si pabo. O ni lasiko ti awọn ọlọpaa n doola ọmọ naa, wọn ba ninu yara kan ti ilera rẹ ko si peye, ti wọn si da ounjẹ sinu abọ nla kan fun lati jẹ bii ẹranko. Ibrahim Lawal yii si ni ọmọkunrin keji ti yoo wa ni iru ipo to buru jai bayii, ti ileesẹ ọlọpaa yoo doola ẹmi rẹ laarin ọjọ meji. Agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Kano, Abdullahi Kiyawa salaye pe o ti to ọdun mẹẹdogun ti wọn ti so Ibrahim Lawal naa mọlẹ bii ẹranko, ninu ahamọ kan. Blind DJ: Etu Omotayo kò ríran àmọ́ ó le to irinṣẹ́ eléré pọ̀ láti kọrin láì sí ìrànwọ́ Kiyawa ni awọn ti gbe ọmọkunrin naa lọ sile iwosan fun itọju to peye, ti iwadii lẹkunrẹrẹ si n lọ lọwọ lori isẹlẹ naa. Fidio kan to si n ja ranin-ranin lori ayelujara lo n se afihan ọkunrin kan ti wọn n wọ jade lati inu ile kan, to si n kerora gidi. Kiyawa ni agbegbe Sheka Unguwar nijọba ibilẹ Kumbotso nilu Kano ni wọn ti doola ọkunrin naa. Olori agbegbe naa, Mallam Bello Da'u Sheaka ni awọn mọ pe ọmọkunrin naa, bii baba rẹ, jẹ onimọ nipa ẹsin Islam. Amọ o fikun pe ahesọ ọrọ kan lo n ja nilẹ pe Ibrahim Lawal naa ni arun ọpọlọ , tawọn ọrẹ rẹ si n saayan lati ba tọrọ owo, ki wọn le gbe lọ sile iwosan fun itọju. Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo Basaraken sisọ loju rẹ pe o ti to ọdun mẹjọ si mẹsan ti oun ti fi oju kan Ibrahim kẹyin, to si ni oun ro pe baba rẹ ti mu lọ sile ẹkọ ni. Awọn ọlọpaa ko ba baba ọmọ naa nile lasiko ti wọn lọ doola ẹmi rẹ lọjọ Aiku Ìjọba Kano fi páńpẹ́ òfin mú Ọba àwọn Oṣó lórí ẹ̀sùn jìbìtì Olugbe ilu Kano kan sọ fun BBC bi oun ṣe ko sọwọ awọn oni gbajuẹ naa nigba ti oun ṣe aisan Ọga agba ajọ eleti gbaroye ati igbogun ti iwa ibajẹ ipinlẹ Kano, Muhiyi Magaji ti sọ fun BBC pe, idi ti ajọ ọhun ṣe n ti ilẹkun ṣọọbu awọn babalawo ati ariran ni ipinlẹ naa ni pe wọn n lu awọn eeyan ni jibiti. Gẹgẹ bi ọrọ to sọ, wọn ti fi panpẹ ofin mu awọn ayederu babalawo mẹrin, wọn o si tẹsiwaju titi di igba ti awọn ara ilu yoo dekun ati maa fẹjọ wọn sun. Magaji ṣalaye pe ""A fofin mu okunrin kan ni ijọba ibilẹ Albasu to n pe ara rẹ ni Ọba awọn oṣo, to si jẹwọ fun wa pe ofege ni oun."" O ni ajọ naaa tun mu okunrin miran lagbegbe Makolo to pe ara rẹ ni alaga awọn babalawo ni gbogbo ipinlẹ Kano. Alaga ajọ amuni mu ẹgbo naa ati meji ninu awọn ti ọwọ tẹ Olugbe ilu Kano kan, Sani Ibrahim sọ fun BBC pe oun ti ko sọwọ awọn gbajuẹ naa ri nigba ti oun n ṣe aisan. Magaji sọ pe bi wọn ṣe n tu aṣiri awọn eeyan naa jẹ ara iṣe ajọ ọhun gẹgẹ bi eyii to n gbogunti iwa ibajẹ lawujọ O ni oni jibiti ni awọn eeyan naa, wọn ko ni agbara kankan, ati pe ko yẹ ki awọn ara ilu maa bẹru wọn rara nitori o yẹ ki aye wọn dara ju bẹẹ lọ ka sọ pe lotọ ni wọn ni agbara. Muhuyi kilọ fawọn eniyan pe ẹni to ba n wa ifa naa lo maa n ri ofo ati pe ẹni to ba n wa iwakuwa naa lo maa n ri irikuri. Akure Kidnap: E túbọ̀ ní sùúrù, a máa wá ọmọ náà rí- Alukoro ọlọ́pàá",0,yoruba nípa ìbadandun. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde nìlẹ̀̀ní sáàrí ti nípa ìtànká àti ire ènìyàn.,0,yoruba "Hìn jàre June, jọ̀wọ́ ṣe wá jẹ́jẹ́ Hin ṣere🙏 https://t.co/fsZXr0PVBn",0,yoruba "Lẹyin ti arun naa n fi ojoojumọ pọ si ni Naijiria papaa julọ nipinlẹ Eko, Gomina Babajide Sanwo-Olu ti kede pe ijọba ti fofin de ipejọpọ to ba ti ju aadọta eeyan lọ bayii kaakiri ipinlẹ naa. Sanwo-Olu fọrọ yii lede ninu atẹjade kan to fi sita lọjọ Aiku. Amọ, gomina ṣalaye ninu atẹjade ọhun pe ofin naa ko kan awọn ile ijọsin nipinlẹ Eko ti ijọba ti sọ fun tẹlẹ pe ki wọn ma ju idaji awọn olujọsin to n maa n jọsin tẹlẹ lọ ninu gbọngan ti wọn n lo. ''Inu ijọba ipinlẹ Eko ko dun si bi ọpọ eeyan ti n tapa si ilana ati dena ajakalẹ coronavirus,'' Sanwo-Olu lo bẹẹ. Big breast: Oluwatosin Adegboro, Oluwaseun Amoo, Remi Fatolu: Ẹlòmíì ń fi irú ọyàn wa tọrọ Gomina Sanwo-Olu sọ pe ọpọ awọn eeyan to ni gbọngan ayẹyẹ lo ti n tapa si awọn alakalẹ ofin lori ati dena covid-19. ''Eyi ni lati kilọ gbogbo awọn to ba n ṣe iruẹ lati ki ọwọ ọmọ wọn bọṣọ, bi bẹẹ kọ, wọn o fi oju wina ofin,'' Sanwo-Olu kilọ. Mckinley Erves di ẹni tọ ń ríran rí aàwọ̀ nípasẹ̀ ìrànlọ́wọ́ ọ̀rẹ́ rẹ̀ Sanwo-ọlu ṣalaye pe ''gẹgẹ bi ofin ti Aarẹ Muhammadu Buhari buwọlu, ẹnikẹni ti aje iwa ibajẹ yii ba ṣi mọ lori yoo san owo itanran tabi ko ṣẹwọn oṣu mẹfa tabi ko ṣewọn ko si tun sanwo itanran. Gomina ni gbogbo olugbe ipinlẹ Eko lo gbọdọ maa tẹle alakalẹ ati dena ajakalẹ arun coronavirus bayii. Tolulope Adeleke Aire: Mo wòye pé àwọn ọkùnrin Nàìjíríà kò fi bẹ́ẹ̀ mọ̀ nípa ìtọ́jú ọmọ tu",0,yoruba "Abajade iwadi ọdun márùndínláàdọ́ta ni o se afihan yi Ni ọdun 1968 ni onimọ ijinlẹ kan ninu imọ ẹkọ Psychometrics, Julian Stanley, ṣe alabapade ọmọ ọdun mejila kan ti o n kọ ẹkọ nipa ẹrọ ayarabiaṣa yunifasiti John Hopkins l'orilẹ-ede Amerika. Ọmọ naa ti orukọ rẹ n jẹ Josph Bates mọ iwe daada sugbọn oun ti wọn n kọ ti ṣuu. Idi ni wi pe imọ to ni ti tayọ tawọn akẹgbẹ rẹ. Ayẹyẹ ọdún ìbejì dùn, ó lárinrin nílùú Igbó-ọrà Kí lo fẹ́ mọ̀ nípa D.O Fágúnwà? Odọmọde yi jẹ iwuri fun Stanley, ti o si tori rẹ bẹrẹ iwaadi ti o gba a ni ọdun márùndínláàdọ́ta lori idagbasoke awọn ọmọ ọlọpọlọ pipe lara awọn ti a ti ri Mark Zukerberg ti o da Facebook silẹ ati gbajugbaja akọrin, Lady Gaga. Sergey Brin ti ile iṣẹ́ Google,akọrin Lady Gaga ati Mark Zuckerberg ti Facebook wa lara awọn ọmọ ẹlẹbun to kopa ninu iwadi naa Ki lo wa pada sẹlẹ si Joseph Bates? O se daada ninu ẹkọ rẹ. Joseph Bates naa ti ṣe iwaadi lọpọlọpọ O tẹsiwaju pẹlu ẹkọ rẹ, o si gba oye ọmọwe. O bẹrẹ si ni kọ awọn akekọ fasiti, ti o si jẹ ogunna gbongbo ninu awọn to nimọ nipa ẹkọ atọwọda ti a mọ si ''artificial intelligence"". Stanley bẹrẹ eto kan ni yunifasiti ẹka to n moju to awọn ọdọ to ni ẹbun ni ilu Baltimore, eyi ti wọn pe orukọ rẹ ni ''imọ awọn ọdọ to ja fafa ninu isiro, ti o si se iwadi igbesi aye awọn ọdọ to le ni ẹgbẹrun marun ti wọn pegede. Nipasẹ iwadi yi ni Stanley ti sọ awọn nnkan pataki to yẹ ki eeyan ṣe ti o ba fẹ ki ọpọlọ ọmọ rẹ ji pepe. Akanṣe eto ẹkọ naa a ma fun ọmọ ni anfaani lati tete kuro ni kilasi kan si imi 1) Jẹ ki ọmọ rẹ ni orisirisi iriri Awọn ọmọ to mọwe daada ṣaba maa n nilo iriri tuntun lati tunbọ sọ ọpọlọ wọn ji. Ti eeyan ba si aye silẹ fun ọmọ lati ni iriri l'orisirisi,a ma fun ọmọ ni anfaani lati koju ipenija to ba ba pade. Awọn onimọ ijinlẹ ni lootọ lo dara ki eniyan koju mọ oun to mọ, sugbọn igboya naa se pataki ti ọmọ ba fẹ ṣe nnkan tuntun. O dara ki obi ṣe awari ohun ti ọmọ wọn fẹran, ki wọn si ranwon lọwọ pẹlu rẹ. 2) Ṣe awari ohun ti wọn fẹran ki o si ranwọn lọwọ pẹlu rẹ Bo ṣe ere idaraya tuntun ni tabi kikopa ninu kilasi ere itage,ti ẹ ba fun awọn ọmọ laaye lati dan nnkan tuntun wo, eyi a ma jẹ ki wọn ni ifarajin lọjọ iwaju. Ẹ ma ṣe fi ipa mu wọn lati ṣe ohun ti ko wu ọkan wọn. Jẹ ki ọmọ rẹ se awari ara rẹ 3) Ṣe atilẹyin fun ọmọ rẹ ninu eto ẹkọ rẹ ati awọn ipenija miran to ba n doju kọ. Ilakaka lati ni imọ sii jẹ atọna lati kọ ẹkọ. Awọn ọmọde a ma saba bere ibeere ki wọn to bẹrẹ ile ẹkọ. O ṣeeṣe ki o fẹ su ọ sugbọn, o ṣe pataki lati fi suuru ma dahun gbogbo ibeere wọn. Ọmọ ti ko dakẹ ibeere saba maa n ṣe daada ninu ẹkọ rẹ. O dara pupọ ki ọmọde ma bere ibeere, ki obi si maa da a l'ohun. 4)Ku iṣẹ lo n mu ori oniṣẹ ya Ran awọn ọmọde lọwọ nipa kiki wọn ku isẹ yatọ si mimu abaabọ iṣẹ ni pataki. Awọn ọmọde a ma wo awokọṣe lara obi wọn. Ti ọmọ ba n gbiyanju lati kọ ẹkọ, apẹẹrẹ pe yoo ṣe daada ni yi. O si yẹ ki awọn obi maa mu ori wọn wu. Iriri orisirisi se pataki 5)Ijakulẹ kii ṣe ohun ti o gbodọ maa bẹru. Bi eniyan ko ba ṣina, ko le mọ ọna. A gbọdọ ri ẹkọ kikọ gẹgẹ bi anfaani lati ran ọmọ lọwọ, ki wọn le mọ bi wọn yoo ti ṣe koju ipenija nigba miran. Awọn obi gbọdo fi ọwọ sowọpọ pẹlu olukọ ọmọ wọn. 6) Ẹ ma fi ọmọ kan we ikeji Fifi ọmọ we ọmọ a ma mu ipinya wa laarin awọn ọmọde. Ko da, o le ṣe okunfa ki awọn ọmọ kan ma dunkoko mọ awọn ọmọ miran. A si tun ma jẹ ki wọn fọkan si pe awọn le ṣe aṣiṣe. Ko dara ki a ma fi ọmọ kan yangan niwaju awọn akẹgbẹ rẹ. 7) Ẹ pawọ pọ pẹlu awọn oluko ọmọ yin Awọn akẹkọ ti wọn loye ati imọ a ma nilo iranwọ ohun elo ẹkọ ti yoo mu wọn peregede, yala lati ọdọ oluko tabi obi wọn. Pipawọ pọ nipa ṣiṣe amulo eto ẹkọ to wa ni itosi wọn ṣe pataki. Agbajọwọ laa fi sọya lọrọ ẹkọ awọn ọmọ de 8) Ri wi pe o ṣe idanwọ fun ọmọ rẹ lati mọ bo ti ṣe mowe si Igbesẹ yii le ran obi lọwọ lati beere fun afikun tabi adinku iye iṣẹ ti ọmọ wọn yoo se. Eleyi si le ranwon lọwọ lati mọ awọn ipenija yowu ti ọmọ wọn ba ni. Bawo lo sẹ le mọ wi pe ọmọ jẹ ọlọpọlọ pipe? Wọnyi ni awọn atọna ti yoo jẹ ki o mọ pe ọmọ rẹ ni ẹbun iwe: • Kii gbagbe nnkan • Ki ọmọ tete bẹrẹ si ni kawe • Iru ọmọ bẹẹ yoo yan ere tabi ki o ni imọ ijinlẹ nipa awọn ẹka ẹkọ kan to yatọ si tẹgbẹ rẹ • Ọmọ rẹ yoo nimọ nipa iselẹ jakejado agbaye • Ko ni ye ma bere ibeere • Irufẹ ọmọ bẹ yoo ni ọyaya • Yoo fẹran orin •A maa wu ko le iwaju •A ma ṣe agbekalẹ ọfin tirẹ fun ere idaraya to ba n ṣe",0,yoruba "wo fun ipilẹ̀ ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Ọpọlọpọ awọn ọmọ Naijiria lo fi aidunnu wọn han lori itakun ayelujara, pe abadofin naa ku diẹ kaato. Femi Fani-Kayode to jẹ minisita fun ọrọ ọkọ ofurufu tẹlẹ ri sọ pe, abadofin naa jẹ ọna lati pa awọn ọmọ Naijiria lẹnumọ ni. O ni ""Ẹyin ọmọ Naijiria. Ẹ ma ṣatililẹyin fun abadofin yii o, to ba lee di ofin, ẹ ko ni lanfani lati sọrọ bo ṣe wu yin mọ."" Reno Omokri naa bu ẹnu atẹ lu abadofin ọhun loju opo Twitter, o ni, ""ijọba to gori alefa latari itakun ayelujara wa fẹ maa gbogun ti awọn eeyan lori itakun ayelujara."" Awọn ọmọ Naijiria mii fẹnun tabuku abadofin naa loju opo Twitter. Wọn sọ pe, ti ijọba ba le ṣamojuto eto ilera ati ọrọ abo, ko si ẹni ti yoo raye lati sọrọ kobakungbe si ijọba. Ẹ wo awọn ohun ti awọn ọmọ Naijiria miran tun n sọ lori abadofin yii. Makinde vs Adelabu: Makinde ní ìjọba Ọyọ yàtọ̀ sí ti Ọṣun àbí Ekiti tí APC lé dànù",0,yoruba "Tinubu ni niwọn igba ti ara awọn ọmọ ẹgbẹ oselu alatako naa ko balẹ mọ, o yẹ kawọn ọdọ ninu ẹgbẹ APC bẹrẹ si ni se koriya lati ri daju pe wọn tẹnpẹlẹ mọ eto koriya ti wọn n se fawọn ọdọ lati dibo. Oloye Tinubu kede ọrọ yii lasiko to n ba awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC sọrọ nilu Eko lọjọru. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Bakan naa ni asiwaju ninu ẹgbẹ APC ọhun fikun pe o yẹ kawọn ẹya Igbo dibo fun ẹgbẹ APC nitori ko si igba kankan ti ijọba APC fọwọ rọ wọn sẹyin tabi dẹyẹ si wọn ninu pinpin ere ijọba tiwantiwa. Àyájọ́ èdè abínibí: Onímọ̀ ní èdè Yorùbá kò ṣe é fọwọ́ rọ́ sẹ́yìn, ó rẹwà Tinubu tun rawọ ẹbẹ sawọn ọmọ ẹgbẹ APC lati ko awọn ọmọ ẹgbẹ PDPto n ya wa sinu ẹgbẹ oselu ọhun mọra nitori gbogbo wọn ni wọn ti di ojulowo ọmọ ẹgbẹ. Ẹyin ọdọ, ẹ yago fun jiji apoti idibo - Tinubu Aṣiwaju ẹgbẹ oṣelu APC, Bọla Tinubu ti paroko ikilọ ranṣẹ sawọn ọdọ nipinlẹ Eko pe ki wọn yago fun jiji apoti idibo gbe lasiko idibo aarẹ ati ile aṣofin apapọ to n bọ lọjọ abamẹta. Otinubu ni "" Ẹ ti gbọ ohun ti Buhari sọ nipa jiji apoti ibo gbe. Mi o ran ẹnikẹni lati lọ ji apoti ibo gbe o. Kaadi idibo mi lemi fi n ja nitemi o.bi ẹ ba ji apoti ibo gbe tabi da wahala silẹ tọwọ ba ba yin, mi o lọwọ ninu iyẹn o."" O ni awọn ti tẹwọ gba isunsiwaju idibo naa latọwọ ajs INEC nitori ọdọ ajọ INEC ni ofin fi si lori irufẹ iṣẹlẹ ba waye. Aṣíwájú ẹgbẹ́ òṣèlú APC, Bọla Tinubu kìlọ̀ fáwọn ọ̀dọ́ lórí jíjí àpótí ìbò gbé ""Iro opolopo awon oniroyin po. Eleyi ti mi o so l'ose to koja, won ni mo so, a so niyen"". Olori egbe APC Bola Tinubu ro awon omo egbe pe ki won jade dibo fun Aare Muhammadu Buhari ni idibo ojo Satide. Ninu oro re, o so pe PDP ni awon ba ja. Pe awon o ba ajo INEC ja nitori pe ofin wa leyin won ati pe o sese ki won ni ipenija ni won fi sun idibo naa siwaju. O gba l'adura pe ajo INEC yoo so layo lori idibo yii ti APC yoo si jawe olubori. O benu ate lu egbe PDP wipe won lo d'ogbon lo fina bo'le l'Abia, won pale oko mo ati bee bee lo. O fi orin ayajo Sunny Ade kan ba won wi pelu ijo lese.O gba awon omo egbe n'iyanju pe ki won ma ba enikankan ja. O ni ki won gba awon omo PDP ti won darapo mo egbe APC wole.",0,yoruba ẹ káàbọ̀ o ìyáa wa mojísọlá aláṣọòkè,0,yoruba "Ọba fè joko, Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba Eku odun tuntun #asheintl #nigeria #yoruba,0,yoruba Ọ̀pẹ̀ wọlé dé!,0,yoruba Pa dúrọ́wà yìí je?,0,yoruba oju adan onribi oju awodi onri oran loni ojo aje ire loju wa yio ri gbogbo omo kutuojire eku ojomo oo°˚˚˚°,0,yoruba "Jákè-jádò ilẹ̀ Yorùbá, gbogbo yín ni mo kí. Ẹ má bínú pé ng kò kanlẹ̀ dáákọ yín o. #osogbo #ikire #ila #owo #ire #saki",0,yoruba Ìṣàtòjọ-ètò,0,yoruba adùn tí a ṣe ní ìlànàa ìgbàlódé kò sunwọ̀n fún ara wa èyí gan an ni ńkóbá ojú àti ìmọ́lẹ̀ojú,0,yoruba "ìgbà mi owó àkokò, Ìyá lo aye àìlẹ̀.",0,yoruba àìkú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Bàbá lo ìgbà ọkọ.,0,yoruba ìṣẹ́ tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìwà: ti o ní wúlò.,0,yoruba kakaaki. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ àti ìbi tí wọn wà.,0,yoruba "Ní ti Ọ́fíìsì Abánirojọ̀ , iléeṣẹ́ náà ti kọ́kọ́ gba àbá náà wọlé , ṣùgbọ́n ní kété tí ó di ẹ̀yìn - in ìbò oṣù Ọ̀wẹwẹ̀ ọdún - un 2018 tí ó gbé Ààrẹ Jair Bolsonaro tí kò fi bò wípé òun kórìíra ti ìbílẹ̀ sí orí àlèèfà , àyípadà dé bá ìpinnu ìgbésè ti ó wà nílẹ̀ tẹ́lẹ̀tẹ́lẹ́rí .",0,yoruba obìnrin a yi fi ti o nuni ti o ní wúlò.,0,yoruba Àtẹ̀jáde ìtúmọ̀ 9 Òkúdù 2020 20 : 17 GMT,0,yoruba "Olufunmilayo - """"""""""""""""God gave me joy"""""""""""""""" #enamelpin #pindesign #pingame #Yoruba #olufunmilayo… https://t.co/uLvSUOik3w",0,yoruba níjó òní nípa èkó aṣà ni nfàn ojú kakaaki.,0,yoruba "14. Wọ́n á ní “ajagajígì, ẹni tí ó mi kùkùté mi ‘ra rẹ̀.” Kíni ajagajígì? #ibeere #Yoruba",0,yoruba irúfẹ́ ikán kan wà nígbà òjò á hu ìyẹ́ á máa fò kiiri ó sì ṣe é yanjẹ kíni o,0,yoruba "Tambuwal Olóṣèlú yìí ṣẹ̀ṣẹ̀ kúrò ní ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress (APC) lọ sí ẹgbẹ́ PDP ní ìbẹ̀rẹ̀ oṣù yìí. Ní ìrọ̀lẹ́ ọjọ́rú ni Tambuwal pẹ̀lú àwọn alátìlẹ́yìn rẹ̀ ya wọ olú ilé iṣẹ́ ẹgbẹ́ alátakò náà, Wadata Plaza ní ìlú Abuja. Ó sọ fún àwọn oníròyìn wí pé ó dá òun lójú wí pé àwọn adarí ẹgbẹ́ yóò ṣe ìdìbò abẹ́nú tó yanrantí bí àwọn olùdíje kò bá fẹnu kò lórí olìdíje kan ṣoṣo. Bukola Saraki fẹ́ rẹ ọmọ Nàìjíríà lẹ̀kún ní 2019 Ààrẹ ilé ìgbìmọ aṣofin Bukola Saraki ti fí èròńgbà rẹ̀ hàn láti dupò ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà níbi ìdìbò gbogboogbo lọ́dún 2019. Bukọla Saraki fi èrọngbà han lati di ààrẹ Nàìjíríà O sọ èyí di mímọ lónìí lásìkò tó kàwé àpilẹ̀kọ rẹ̀ níbi ìpàdé pẹ̀lú àwọn ọ̀dọ́ tó ń gbèrò láti dúpò ààrẹ lọ́dún tó ń bọ. Ó ní ' mo fí àsìkò yìí fí èrò ọ̀kàn mi hàn láti díje fún ipò ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà níbi ìdìbò gbogboogbò ọdún tó ń bọ lábẹ́ àsíà People's Democratic Party (PDP). mó ṣe èyí pẹ̀lú àrídájú pé ǹ ó mú ìdàgbàsókè bá orílẹ̀-èdè yìí àti àwọn ènìyàn rẹ̀.' Bukola Saraki 2019: Mo fẹ́ rẹ ọmọ Nàìjíríà lẹ̀kún ní Ètò ọrọ̀ ajá wa ti dẹ́nu kọlẹ̀ tán èyí sì nílò àtúnṣe ní kíákíá kí orílẹ̀-èdè yìí baa lè ni ìdàgbàsókè., Saraki ni ọ̀pọ̀ àwọn ọ̀dọ́ kò rí iṣẹ́, oko-òwò ti di gbígbé ti sps àwọn ènìyàn míràn sì ń pàdánù iṣẹ́ wọn lójoojúmọ. Ààrẹ̀ ilé ìgbìmọ aṣofin àgbà tún fi kún ọ̀rọ̀ rẹ̀ pé pàtàkì ìdí ti òun fi fẹ́ díje ni lati láti dá ògò orílẹ̀-èdè yìí pada nítori ìpinyà ti wàà láàrín àwọn ẹlẹ́yà -mẹ̀yà, láàrin ẹkún kọ̀ọ̀kan, ẹsìn àti ìbáṣepọ̀. Saraki ní òun fẹ́ ki àwọn ọ̀dọ́ máa kó ipa to lààmì-laaka láwùjọ nítori náà ìjọba oun yóò rii dájú pé ààyè to tọ ni wọn yóò wà.",0,yoruba "ìya ìlú. Nitori eyi, ara eni lo je ti ibile.",0,yoruba "Iṣẹlẹ yii waye nigba ti Lady Gaga fẹ pe ọkan lara awọn ololufẹ rẹ, Jack pe ko goke wa. Bi Lady Gaga ṣe fo soke, to si bẹrẹ si nii jo ni ẹsẹ rẹ yẹ lori itage, lo ba ṣubu yakata. Ẹnikan ti iṣẹlẹ ọhun ṣoju rẹ ni ọpọ lo ro pe olorin naa ti ku lẹyin to ṣubu, amọ o jẹ iyalẹnu pe, o tun goke wa pẹlu Jack to fẹ fa soke pẹlu rẹ. Egungun ṣubu, o sọ didan ni Lady Gaga fi ṣe, lẹyin to sọ pe awọn mejeeji fẹran ara wọn debi pe awọn jọ jabọ lati ori itage. O ni ọrọ awọn dabi Jack ati Rose ninu fiimu Titanic. Ko da Lady Gaga ni o yẹ kawọn jọ muti papọ. Ọpọ ololufẹ Lady Gaga lo bẹru fun Lady Gaga nitori o ni nnkan to maa n jẹ ki irora pọ sii lara eeyan ti wọn n pe ni 'Fibromyalgia'. Lọdun 2013, Lady Gaga wọgile erongba rẹ lati lọ kọ orin 'Born This Way' lẹyin to fi itan rẹ ṣeṣe. Ṣugbọn lẹyin iṣẹlẹ naa, Lady Gaga sọ fawọn ololufẹ rẹ pe kokoko lara oun le.",0,yoruba "Ọmọ tuntun, Angel lo oṣu maarun akọkọ aye rẹ nileewosan Iya Angel sọ fun BBC pe omi ọyan ohun ti gbẹ lẹyin ti wọn pin oun niya pẹlu ọmọ naa fun oṣu maarun akọkọ aye rẹ. Iṣẹlẹ ohun jẹ iyalẹnu fun awọn eniyan l'orileede naa, iranlọwọ si dide fun un lati ọdọ awọn ara ilu. Owo itọju naa to jẹ ẹgbẹrun mẹta le ojilelẹgbẹta dọla di sisan lẹyin eto ipolongo to waye fun idile naa. Aarẹ Ali Bongo naa wa lara awọn to da owo fun wọn. Akọroyin BBC nilu Libreville, to jẹ olu-ilu Gabon, Charles Stephan Mavoungou jabọ iroyin pe, wọn fi panpẹ ofin mu oludari ileewosan naa l'ọjọ aje, wọn si fi ẹsun jiji ọmọ ikoko naa gbe kan an, bi o tilẹ jẹ wipe wọn pada fi oju fo ẹsun naa. Ọsẹ yii ni wọn yọnda Angel lati kuro ni ileewosan ọhun to n bẹ lapa ariwa ilu Libreville. Iya ọmọ naa, Sonia Okome, sọ fun BBC bi inu rẹ ṣe dun to, ṣugbọn o salaye pe ibanujẹ ati ayọ ni iṣẹlẹ naa jẹ fun oun: ""Inu mi i dun lati gba ọmọ mi pada. Ṣugbọn, mo tọrọ aforiji pe mi o ni le fun l'ọyan nitori wipe omi ọyan mi ti gbẹ lẹyin oṣu maarun."" O tun fi aidunnu rẹ han lori bi ọmọ naa ko ṣe ti i gba abẹrẹ ajẹsara kankan. Owo ileewosan naa lo jẹ owo iye ọjọ ti ọmọ naa lo ninu ẹrọ ti wọn fi n tọju awọn t'oṣu wọn o pe si nitori wipe ọjọ ibi rẹ ko ti to o ti iya rẹ fi bi.",0,yoruba fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ìyá lo ni àṣà yorubá eyti o gbe lori ọ̀run dídì.,0,yoruba ni ìwájú. Ìyá lo ni iwa rere lojiji.,0,yoruba "A kì í du orí olórí, kí àwòdì gbé tẹni lọ"""""""". Translation: """"""""We should not save someone else's head and neglect ours"""""""". Lesson: Offer help to people, but don't forget yourself. You are important... #learnyoruba #wisesayings #owe #mondaywisdom #yorubalessons #yoruba https://t.co/LE0cJXrp4E",0,yoruba "Yomi Fabiyi lọ ṣe ipade pẹlu awọn agbẹjọro lori ọrọ to n duro le lori lati ọjọ yii eyiun, pataki ẹtọ ọmọniyan lori eyi to fi tun ṣe iwọde ifẹhonuhan pe ki wọn tu Baba Ijesha silẹ pẹlu beeli. Awọn agbẹjọro ti Yomi ba ṣe ipade ni agbẹjọro Adesina Ogunlana Esq. (alaga ẹgbẹ awọn amofin tẹlẹ ni Ikeja), agbẹjọro Ayo Ademiluyi, Comrade Aghedo Kehinde (ajafẹtọ ọmọniyan). Gbogbo igbesẹ rẹ yii da lori ẹtọ akẹgbẹ rẹ, Lanre Omiyinka ti gbogbo eeyan mọ si Baba Ijesha. Oun ni wọn fi ẹsun ifipaba ọmọde lopọ kan to si ti wa lahamọ ọlọpaa lati igba naa tori awọn ile ẹjọ ko tii fopin si iyanṣẹlodi wọn. Ipo ti Baba Ijesha wa bayii Awọn agbẹjọro naa ni nigba ti awọn de agọ Ọlọpaa agbegbe Panti pẹlu akẹgbẹ rẹ Yomi Fabiyi ti awọn jọ lọ lati yẹ Baba Ijesha wo, ""ṣe lo ri ráhun-ràhun, bi ẹni ti iya ti jẹ to ni idamu ọkan to si n tiro lori ẹsẹ kan, ẹsẹ ọtun rẹ"". ""Ẹtọ ọmọ eniyan ṣe koko. Idajọ kankan ko lee dara bi wọn ko ba faaye gba ki awọn tọrọ kan ri sọ tabi ki wọn gbọ tẹnu wọn ki wọn si da abo bo ẹtọ wọn"". Yomi Fabiyi tẹnu mọ ọ pe lai fi ti ohun to n ṣẹlẹ si eeyan ṣe, o yẹ ki ibọwọ wa fun gbogbo eeyan. ""E lee tẹra mọ jija fun ẹtọ eeyan, ẹ lee ni imọlara ati itara si ohun to ṣe eeyan kan amọ ẹ ma ṣatilẹyin fun ohun to ba mu ẹtọ ẹlomiran kuro ati ilokulo ofin"". Ansoogun jagunjagun Iresa Adu Ogbomoso tó máa ń bínú gba ẹbọ- Oloye James Olawale Yomi ni iru nkan bayii maa n dunkoko mọ idagbasoke ati alafia ni. Ẹwẹ, loju opo ayelujara ọkan lara awọn agbẹjọro ti Yomi Fabiyi ba ṣe ipade ti fi ara re han ni agbẹjọrọ Babab Ijesha. O o fi lẹta ti o kọ lorukọ ileeṣẹ rẹ si kọmisọnna ọlọpaa ipinlẹ Eko ninu eyi to ti sọ wi pe ohun gẹgẹ bi amofin ati agbẹjọro to n duro fun afurasi ọdaran to wa lahamọ wọn, Baba Ijesha. Ati wi pe o han gbangba pe lati bii ọsẹ melo kan ti ọrọ yii ti bẹrẹ, aridaju ti hande to si tumọ si pe imọran to yẹ ki wọn gba labẹ ofin bayii ni ki wọn gba beeli rẹ. Ninu iwe ti agbẹjọrọ naa kọ si kọmisọnna ọlọpaa Eko, o ni ""a fẹ ko di mimọ pe fifi afurasi si atimọle ju ọgbọn ọjọ lọ lodi si ofin to ti ẹtọ ọmọniyan lẹyin labẹ ofin Naijiria ti ọdun 1999"". Wọn pe fun ki kọmisọnna ọlọpaa tete wa nkan ṣe si ọrọ yii. Lori lẹta naa la ri ti wọn fi ontẹ ọfiisi kọmisọnna ipinlẹ Eko jan an eyi to tumọ si wipe o ti ri i o si ti tẹwọ gba lẹta naa, amọ ibuwọlu kọmisana la ri, ko tii wa si gbangba sọ ohunkohun.",0,yoruba ó yá kí a gbé ìtàn inú ifá nípa bí alábahun àjàpá ṣe di onígbá lẹ́hìn yẹ̀ wò,0,yoruba Ṣe o dá ojúbọ Ṣàngó mọ̀? #worldsangofestival #Sango #Oyo,0,yoruba Iṣọ́ẹ̀ ìṣẹ́ ni a ní láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó ṣe pàtàkì.,0,yoruba "Obama mọ ọ̀rọ̀ ọ́ sọ kí orí ènìyàn wú, ọ̀gá ńlá sọ̀rọ̀ sọ̀rọ̀ ni. O ti ṣe ìwọ̀n tí o lè ṣe, ó ti wọ àkọsílẹ̀. Ó dìgbòóṣe!",0,yoruba ọ̀ṣun ìlú. Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba ilera ṣẹlẹ ni Eko ti gbogbo eniyan sọ o dara.,0,yoruba iyeni wipe ko ni je tolotolo ni ojo idupe ko si idariji fun tolotolo ni aso villa eiye jije ni e ku,0,yoruba "Nàìjíríà n ṣe àjọyọ̀ ọdún kejìdínlógún tí wọ́n ti n lo ètò ìṣèjọba àwaarawa. Àyájọ́ ọjọ́ nàá jẹyọ lọ́dún 1999, lẹ́yìn tí Nàìjíríà ti wà lábẹ́ ìṣàkóso ológun fún ọdún mẹ́ẹ̀dógún. Bákan nàá ni ti ọdún 2018 n ṣe àmì ọdún mẹ́ta tí ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress, APC, ti wà lórí àga ìṣàkóso Nàìjíríà, lẹ́yìn ọdún mẹ́rìndínlógún tí Peoples Democratic Party, PDP, fi ṣèjọba. Ṣíṣe àjọyọ̀ ètò ìṣèjọba àwa ara wa lọ́jọ́ kọkàndínlọ́gbọ̀n, oṣù Karùn ún ṣábà maa n fa àríyànjiyàn, pẹ̀lú bí èrò kálukú ṣe maa n ṣọ̀tọ̀ọ́tọ̀ lórí pàtàkì ọjọ́ nà. Kín ni àwọn ọmọ Nàìjíríà n sọ? Bí àwọn kan ṣe n rí ọjọ́ nàá bí ànfàání láti ṣàjọyọ̀ àwọ̀n nkan rere tó n jẹyọ lára irú ìṣèjọba bẹ̀ ẹ́, láwọn kan n takò ó pẹ̀lú àríyànjiyàn pé kò sí nkankan tó wú ni lórí, tó n pé fùn àjọyọ̀ ní Nàìjíríà, pàápàá nípa ìjọba rẹ̀. Àwọn kan tilẹ̀ ní àkóba ni ètò ìṣèjọba àwaarawa ju ti tẹ́lẹ̀ lọ. Bákan nàá, ni àwọn mì í tilẹ̀ di ẹ̀bi àwọn ìṣòro tí Nàìjíríà ní ru àwọn ọmọ orílẹ̀èdè ọ̀hún fún ra wọn, tí kií sì i ṣe ètò ìṣèjọba ọ̀hún tó ti mú ìdàgbàsókè bá àwọn orílẹ̀èdè mi í ní àgbáyé, tó sì ti gbá wọ́n kúrò lóko ẹrú, àti ìyà. Ẹ̀wẹ̀, àwọn kan ní ìjọba Muhammadu Buahri kó tì ṣe àsẹyọrí kankan láti ọdún mẹ́ta tó ti wà lórí àga ìṣàkóso, pàápàá lórí ètò ọrọ̀ ajé àti ààbò. Láti ìgbà tí ètò ìṣakóso nàá ti bẹ̀rẹ̀ ní oríṣiríṣi awuyewuye ti n wáyé lórí àwọn ẹ̀jẹ́ tí Buahri jẹ́ lásìkò ìpolongo ìbò tó ṣe ṣáàjú ètò ìdìbò gbogboogbo tó wáyé lọ́dún 2015, pàápàá lórí ètò ààbò àti ọrọ̀ ajé, pẹ̀lú bí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọmọ Nàìjíríà ṣe n sọ pé ìjọba Buhari kò ṣe tó. Èyí n wáyé nítorí ìkọlù tí àwọn darandaran Fulani n ṣe jákèjádò orílẹ̀-èdè yìí, àti ní pàtàkì, ìpínlẹ̀ Benue. Bákan nàá ni tí àwọn ìkọlù tí ikọ̀ Boko Haram n ṣe. Onímọ̀ nípa ètò ọrọ̀ ajé sọ̀rọ̀ lórí ipò tí ọrọ̀ ajé Nàìjíríà wà. Ẹ̀wẹ̀, onímọ̀ kan nípa ètò ààbò, Ọ̀gbẹ́ni Richard Amuwa, sọ fún BBC Yoruba pé, ""ohun tí àwọn ará ìlú n sọ ló yẹ kí ìjọba Buhari fi ṣe òdinwọ̀n àṣeyọrí ìṣàkóso rẹ̀, nítorí pé àwọn ló mọ bí ààbò ṣe wà fún ẹ̀mí àti dúkìá wọn."" Àti pé, ó yẹ kí Buhari ti pàárọ̀ àwọn olórí láwọn iléesẹ́ ètò ààbò Nàìjíríà. Attahiru Jega pe àwọn Asòfin ní olè ""Ààrùn Ebola ti 'wá ni kòkòrò ajokorun""",0,yoruba si ìlú. ti Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba RT @user: Odò tó ńṣàn kì í b'ojú w'ẹ̀hìn. / A flowing stream never looks (or flows) backward. [Be forward-looking; be focused: n…,0,yoruba "Eeyan meji ọtọọtọ l'awọn ero dana sun lagbegbe ASAS ni Molete ati Oke Ado ni ilu Ibadan lọjọ Aje. Agbegbe Oke Ado ni wọn ti kọkọ dana sun ọkunrin kan ki ekeji to waye lagbegbe ASAS ni Molete. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Amọṣa, oniruru iroyin lo n waye lori ohun to ṣokunfa bi wọn ṣe dana sun arakunrin ti wọn pa lagbegbe Oke-Ado. Bi awọn eeyan kan ti isẹlẹ naa soju wọn ṣe n wipe ajinigbe ni Saheed, lawọn miran n wipe kii ṣe ajinigbe, aarẹ ọpọlọ diẹ lo n ṣe e. Awọn to pe e ni ajinigbe ṣalaye pe, Saheed pọn ọmọlangidi ti ọpọ mọ si 'bebi' si ẹyin, eleyii to maa fi n tan awọn ọmọde lagbegbe naa. Olugbe agbegbe naa kan la gbọ pe o pariwo sita nigba to ni oun ri Saheed to n tan ọmọ ọdun mẹrin kan pẹlu erongba lati ji gbe. Bi aladugbo wa ṣe mọ pe Saheed fẹ ji ọmọde naa gbe ni, ko tii si ẹni to le sọ. Eyi ni won pe o mu ki ọpọ ero lagbegbe naa ya bo o. Ọrọ naa tun le sii nigba ti wọn ni wọn ba ẹgbẹrun lọna igba ati aadọta naira lara rẹ. 'Pásítọ̀ ló sọ fún mi pé Ọlọ́run pè mí láti di Olokun tó ń bọ omi' Ẹwẹ, ọkan lara awọn olugbe agbegbe Odo Ọna nibi ti wọn ni Saheed n gbe ṣalaye pe, aisan ọpọlọ lo n ba Saheed finra diẹdiẹ, ati pe kii ṣe ajinigbe gẹgẹ bi wọn ṣe sọ. Ẹni naa ti wọn pe orukọ rẹ ni Bamidele Emmanuel salaye pe, iṣẹ agbaṣe ọkọ fifọ ati agbaru lo maa n ṣe fawọn eeyan lagbegbe naa. O ni iṣẹ dẹrẹba lo n ṣe tẹlẹ ati pe aisan naa de si i lẹyin ti wọn ji ọkọ bọọsi to n wa lọ. Zlatan: Ọ̀rẹ́ ni mo sìn lọ ‘studio’ tí mo fi bẹ̀rẹ̀ orin lẹ́yìn tí mo kùnà ìdánwò WAEC O ni ọlọkọ bọọsi naa ko gbagbọ pe wọn ji ọkọ naa lọ ni, eyi to mu ko fi Saheed sun ni agọ ọlọpaa; lẹyin to kuro ni agọ ọlọpaa naa ni aisan ọpọlọ naa bẹrẹ. Awọn ọlọpaa ni iwadii ti bẹrẹ lori iṣẹlẹ naa Iṣẹlẹ idajọ ọwọ ti di eyi to n fi ojojumọ waye ni ipinlẹ Ọyọ bayii to si nkọ lominu nibẹ. Ileeṣẹ ọlọpaa wa bu ẹnu atẹ lu bi awọn eeyan ṣe n fi idajọ si ọwọ ara wọn bayii, eyi ti wọn ni o ti wa n di lemọlemọ, paapaa ni ilu Ibadan ati ipinlẹ Ọyọ lapapọ. 'Ọ̀lọ́pàá shátà mi láti Mowe dé Magboro dé Shagamu, wọ́n ní ṣé mi ò mọ̀ pé ìjọ́ba ni mo ṣiṣẹ́ fún' Atẹjade kan lati olu ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo ṣalaye pe, kọmiṣọna ọlọpaa ni ipinlẹ naa ti jawe ikilọ ranṣẹ sawọn to kundun idajọ ọwọ nibẹ ati pe ẹnikẹni ti ọwọ ba tẹ yoo kabamọ ṣiṣe bẹẹ. Aráàlú dá iná sun èèyàn méjì n'Ibadan, orí kó ẹni kan yọ Eeyan meji ọtọọtọ l'awọn ero dana sun lagbegbe ASAS ni Molete ati Oke Ado ni ilu Ibadan lọjọ Aje. Amọṣa ori ko eeyan kan miran yọ nigba ti awọn oṣiṣẹ ikọ Amọtẹkun gba a silẹ lọwọ awọn ero to n binu naa. Awọn ọlọpaa ni ko tii si ẹni to lee sọ pato ohun to ṣẹlẹ tawọn eeyan fi da ina sun awọn mejeeji yii. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Iṣẹlẹ idajọ ọwọ ti di eyi to n fi ojojumọ waye ni ipinlẹ Ọyọ bayii,eyi to si nkọ ọpọ eeyan lominu nibẹ. Jude Chukwuka: Wò ó bí òwé Yorùbá ṣe yọ̀ lẹ́nu ọmọ Igbo Eeyan ti ori ko yọ naa ni wọn ṣalaye pe, o ṣi n gba itọju lọwọ nile iwosan awọn ọlọpaa to wa lagbegbe Ẹlẹyẹle ni ilu Ibadan. Ileeṣẹ ọlọpaa bu ẹnu atẹ lu bi awọn eeyan ṣe n fi idajọ si ọwọ ara wọn bayii eyi ti wọn ni o ti wa n di lemọlemọ bayii ni ilu Ibadan ati ipinlẹ Ọyọ. Atẹjade kan lati ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ ṣalaye pe, kọmiṣọna ọlọpaa ni ipinlẹ naa ti jawe ikilọ ranṣẹ sawọn to kundun idajọ ọwọ nibẹ ati pe ẹnikẹni ti ọwọ ba tẹ yoo kabamọ ṣiṣe bẹẹ. Iná ẹ̀lẹ́ńtíríkì pa ọlọ́kadà, obìnrin kan ní Ibadan, àjọ IBEDC ní àwọn ti bẹ̀rẹ̀ ìwadìí Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe opo ina mọnamọna ti wo pa ọlọkada kan ati obinrin kan lagbegbe Iwo road ni ilu Ibadan. Gẹgẹ bi iroyin ṣe sọ, ọlọkada naa ati obinrin ọhun n dunadura lori iye owo ni lasiko ti opo ina naa fi wo luwọn ni ina ara waya ori rẹ si pa wọn. Awọn eeyan agbegbe naa pe orukọ ọlọkada naa ni Kabiru ṣugbọn wọn ni oluyọle ni ọpọlọọ eeyan mọọ si. Awọn ti iṣẹlẹ naa ṣe oju wọn ṣalaye pe olounjẹ ni arabinrin naa, o si wa si agbegbe naa ni lati wa gba ẹgbẹrun kan naira ti ọkan lara awọn ọlọkọ ero lagbegbe naa jẹ ni ki iṣẹlẹ buruku naa to ṣẹlẹ. Ki ni Ileeṣẹina mọnamọna, IBEDC sọ nipa iṣẹlẹ naa? Amọṣa, ileeṣẹ mọnamọna ẹkun Ibadan, IBEDC ti darukọ awọn ti ina gbe naa ti wọn si pe orukọ wọn ni Ọgbẹni Ọladeji Ọlatunji pẹlu Arabinrin Kẹmi Degoke. Wọn lawọn ba awọn mọlẹbi wọn kẹdun. Ninu atẹjade kan to fi sita lọjọ Abamẹta, ọga agba ileeṣẹ mọnamọna lẹkun Ibadan, IBEDC, ọgbẹni Jọhn Ayọdele ni awọn ti n ba awọn mọlẹbi naa jiroro lọna ati tu wọn ninu bi o ti wulẹ o mọ. Bakan naa lo fi kun un pe igbesẹ ti bẹrẹ lori wiwadii bi iṣẹlẹ naa ṣe ṣẹ ati ohun gan to sokunfa rẹ.",0,yoruba Àkójú ọ̀rọ̀ yi kún fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde sí ara ilẹ̀. (Item 39),0,yoruba ẹyọ ẹyọ ni à ń ṣe oǹkà a lè kà á ní ọ̀kọ̀ọ̀kan ní méjìméjì márùnún márùnún,0,yoruba Gbogbo onígbàgbọ́ yóò wọ ìbomúbẹnu lásìkò tí ìsìn bá ń lọ lọ́wọ́ .,0,yoruba "ni ìwájú. Ọmọ lo ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba ọjọ́ kan pẹ̀lú o ọ̀rẹ́ ẹ máa gbádùn lọ,0,yoruba iṣẹ́ ṣẹlẹ ni Lagos ti gbogbo eniyan sọ o ṣe pataki. (1999),0,yoruba fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Bàbá lo tun se lọ.,0,yoruba "ọ̀ṣun. Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "Ìbàdàn. Nitori eyi, ara eni lo ni Nitori eyi, ara eni lo ni ẹ̀ká àwẹ eyti o gbe lori àìmọ́ kọ.",0,yoruba "Muritala Babatunde àti Taiwo Rasak ní wọ́n jọ pa àwọn olólùfẹ́ nàá ni Oriade Adebisi, ọmọ ọdún méjìlélógún kan tó jẹ́ ọmọ fásiti Olabisi Onabanjo tó wà ní Osu, Ipínlẹ̀ Ogun ń lọ kí ọ̀rẹ́ rẹ̀ ní Oru-Ijebu pẹ̀lu olólùfẹ́ rẹ̀ Julian Imaga, nigba tí àwọn mẹéjééji di àwáti. Fún bí ọ̀sẹ̀ méji ni àwọn ọlọ́pàá fi ń wá Adebisi ati Julian to jẹ́ ọmọ ọdún méjìdínlógún. Ṣugbọn lẹ́hin ìwádìí oríṣiríṣi tí ẹka iléeṣẹ́ ọlọ́pàá tí a mọ̀ sí IRT ṣe, wọ́n rí òkú àwọn méjéèji nínú igbó kan ni Oru-Ijẹ̀bu. Ní kété lẹyin ti ọlọpaa rii pe ololufẹ mejeeji ti re ọrun àrèmábọ̀ ni ìwádìí fojú àwọn méji tí wọ́n ní o pa àwọn olólùfẹ́ mejéèji han, tí ẹ̀ka IRT si gbé wọn lẹyẹ o sọka. Olórí IRT fi atẹjade sita ní ọjọ́ Abamẹ́ta, ti wọn fi kede awọn oniṣẹ ibi to pa ololufẹ mejeeji. Wọn ni Muritala Babatunde, to jẹ ẹni ọdún mọ́kàndínlọ́gbọ̀n ni olórí ẹgbẹ́ òkùnkùn tí a mọ̀ sí Black Axe Confraternity ló ṣe ikú pa wọ́n. Bakan naa ni wọn kede afurasí ọmọ ọdúin méjìdínlógun kan, Taiwo Rasak pe oun ní wọ́n jọ pa awọ́n ololufẹ naa. Muritala Babatunde sọ fún àwọn ọlọ́pàá pé inú bí òun sí Adebisi nítorí kò ka òun sí gẹ́gẹ́ bíi ọkan gbòógi nínú ẹgbẹ́ okùnkùn ní agbègbè náà. Ó tún sọ̀ pe Adebisi máa ń fún ẹgbẹ́ kan tó jẹ́ ọ̀tá ti òun ní owó déédéé. Adebisi àti Julian di àwáti l'ọjọ́ kéjìdínlọ́gbọ̀n oṣu karùń ùn, ọdun 2018. Ìwádìí ọlọ́pàá fi hàn pé l'ọjọ́ kéjìdínlọ́gbọ̀n, oṣu karùń ùn tí Adebisi àti Julian dàwáti, ni àwọn onisẹ ibi mẹ́ta ọhun yọ ìbọn sí wọn bí wọ́n ṣe kọrí sí ìyànà Oru, ti wọ́n si fi ipá gbé wọn lọ́ inú igbó. Ẹ̀yin ilé kan tí won kò tíì pari ni wọ́n pa wọ́n sí. Awọn afurasí náà ní póńpó àti ìbọn ni àwọn fi pa wọ́n. Wọ́n ní kí ọjọ́ náà tó dé, àwọn ti n ṣọ ìrìn Adebísí. Àwọn ikọ̀ IRT nínú igbó tí wọ́n ti bá òkú àwọn olólùfẹ́ náà A gbọ́ pé àwọn ọlọ́pàá ri ọkọ̀ Crosstour olóògbé náà, bàtà rẹ̀ àti fónù rẹ̀ gbà lọ́wọ́ àwọn afurasí nàá. Wán sì tún bá ibọn tí wọ́n fi ń ṣọsẹ́ lọ́wọ́ wọn. Wọ́n ti gbé òkú àwọn méjéèjì lọ mọ́ṣúárì jẹ́nẹ́rà tó wá ní Ìjẹ̀bú. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: SARS ti bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ láti yọ àwọn ọ̀bàyéjẹ́ kúro",0,yoruba "ni a ní nípa ire àti ìbàdandun, àwọn ẹ̀kọ́ ọmọ aláwọ̀ wà níṣẹ̀.",0,yoruba ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba "Ààrẹ Buhari ní ó seni láàànù pé ààwẹ̀ ọdún yíi wáyé lásìkò tí gbogbo àgbáyé ń kojú ìpèníjà àjàkálẹ̀ ààrun COIVD - 19 , ní èyí tí ó ti tàn ká igba ( 200 ) orílẹ̀ èdè tó wà lágbàáyé , tí gbogbo orílẹ̀ èdè sì ń pariwo pé kí àwọn ènìyàn yàgò fún ìpéjọpọ̀ , kí wọn sì máa dá gbàdúrà àti ìsírun wọn tàbí pẹ̀lú",0,yoruba "ọ̀pọ́lọ̀ ni ìbàdandun àtọ́wọ́dá, àwọn oníṣẹ́ ìṣẹ́ ni ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa aráyé: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọmọ lo ni ìgbà mi owó àkokò, Ìyá ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò.",0,yoruba ìròyìn kan mòní nípa ìgbà àkerekere ni nfàn ojú kakaaki.,0,yoruba @user @user @user Kòṣééfowórà ni ìyá jẹ́. Wúrà iyebíye. Ọlọ́run á dá wọn sí o.,0,yoruba Ọlọ́pá YouTube naa ní ègé olóótọ fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa aráyé: ti o nuni ti o ní wúlò.,0,yoruba ìgbòkègbodò òṣùwọ̀n edidi làásìgbò how to play save the image on your phone mark the words with blue or any colour of your choice ink when you are done upload the answer as a reply to the post bí a ṣe lè kópa ẹ gba àwòrán yìí sórí ẹ̀rọ yín kí ẹ sì falà sí,0,yoruba "RT @user: Ètò kan tí í máa larinrin jù níbi Igogo ni Udan Olughare, tí àwọn ọ̀gọ̀ṣọ́ omidan tó ṣẹ̀ṣẹ̀ bàlágà yóò jòó láì róṣọ mọ́yà,…",0,yoruba "kún jú, àwọn ènìyàn ni ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa iṣẹ́: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ àti ìbi tí wọn wà.",0,yoruba "ìgbà kan. Nitori eyi, ara eni lo ni ìgbà mi owó àkokò, Alàji lo tun se se.",0,yoruba "Bí ó ti wù kí ó rí , pẹ̀lú ẹ̀gàn ni ó jẹ́ pé ọ̀ràn - an àhesọ àti ọ̀rọ̀ ìkórìíra kan Lai àti El - Rufai gẹ́gẹ́ bíi ìṣòro ààbò orílẹ̀ - èdè Nàìjíríà .",0,yoruba wa ni abọ́jú irúngbọ ni nfàn ojú kakaaki.,0,yoruba wúlò. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọba lo tun se joko.,0,yoruba "Ogundiya: Àṣìṣe Dókítà ló sọ mi di aláàbọ̀ ara lórí kẹ̀kẹ́ Oṣu Kinni ọdun ni wọn ṣe iṣẹ abẹ fún gbajugbaja agbabọọlu naa.Pọgba sọ fun ikọ̀ agbohunsafẹfẹ Manchester United pe oun ko ti i la iru nkan bẹẹ kọja ri lati igba ti oun ti n gba bọọlu jẹun, sugbọn oun gba kadara.O ni: ""Mi o ro pe awọn eniyan mọ nkan to ṣẹlẹ si mi gan-an."" Pogba ṣalaye pe: ""Mo fi ẹsẹ mi ṣẹṣẹ lasiko ti a n gba bọọlu pẹlu Southampton ni ọjọ kọkanlelọgbọn, oṣu Kẹjọ. Eyi jẹ ibẹrẹ ṣaa, mo si mu u mọra fun igba pipẹ; mo n lọ fun igbaradi, mo si tun n gbiyanju lati fi gba bọọlu. Lẹyin ti mo dawọ gbogbo eyi duro ni mo sakiyesi pe egungun mi ti yẹ̀. Ogbontarigi agbabọọlu naa tẹsiwaju pe: ""Wọn ba mi fi nkan we e nileewosan. Sugbọn lẹyin asiko diẹ, egungun naa tobi si i, ni mo ba tun pada ṣenu isẹ. Ifẹsẹwọnsẹ pẹlu Watford ati Newcastle ni mo gba kẹyin ninu oṣu Kejila, ti mo tun fi n ni inira."" Ṣugbọn lẹyin isẹ abẹ ti wọn ṣe fun mi, ara mi ti ya. Mo si ti ṣetan lati pada ṣenu isẹ.""Ọjọ kẹta, oṣu Kẹrin ni wọn kọkọ sun idije Premier league siwaju, lẹyin naa ni wọn tun sun un ni ọgbọnjọ, oṣu Kẹrin, nitori ajakalẹ arun coronavirus to n gba ẹbọ lọwọ gbogbo agbaye yiii. Yoruba Culture: ọjọ́ méje ni wọ́n fí n rẹ ẹ̀kú Danafojura kó tó jáde",0,yoruba Ogun Church Kidnapping: Agbébọn ń bèèrè N6m lórí èèyàn mẹ́ta tí wọn gbé ní ṣọ́ọ́ṣì,0,yoruba "Bóo ni ṣe àlàáfíà lẹ wà, gẹ́gẹ́ bí èmi náà ti ṣe wà. https://t.co/0sDTVIpWZs",0,yoruba obirin naa di màálu níyèn tí o jè pe wòn a mà mùn òmu àyà rè gbigba tí wòn fun wàrà aiyè òmu lòbírí,0,yoruba ẹkọ́ ṣẹlẹ ni Ibadan ti gbogbo eniyan sọ o ṣe pataki. (1993),0,yoruba fẹ. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba "Aisha Buhari tutọ sókè fojú gbà à, ó ní kí Garba Sheu kọ́we fipolẹ́ Ninu ọrọ ti Aisha Buhari sọ ninu atẹjade kan loju opo Twitter rẹ, o ni Garba Sheu ti gba abọde ti o si tọ ki o kọwe fiposilẹ. End of Twitter post, 1 Aisha Buhari sọ pe nkan ti wọn ni ki ẹlẹmọṣọ Garba Sheu sọ kọ ni o gbaju mọ ti o si yapa adehun to ṣe lati ba aarẹ Naijiria ṣiṣẹ tọkantọkan. Yatọ si ẹsun yi, Aisha Buhari tun fi awọn ẹsun miran kan Garba Sheu ṣugbọn koko nkan to jẹ yọ ni pe Garba Sheu nikan kọ ni Aisha n sọko ọrọ ba. Ninu atẹjade naa o sọ pe: Akure Kidnap: Àwọn abiyamọ fẹ̀hónúhàn lórí ọmọ tí wan jígbé nílé ìjọsìn Akurẹ Ọkùnrin tó yí orúkọ padà sí Muhammadu Buhari ṣ'ayẹyẹ ìsọmọlórúkọ ní Kano Kìnìhún fa èèyàn kan ya ní Nairobi, àdúgbò dàrú Má ṣe fi ọkọ̀ rẹ gbé àgùnbánirọ̀ lẹ́yìn aago mẹ́fà ìrọ̀lẹ́- FRSC Àwọn agbébọn ṣekúpa akẹ́kọ̀ọ́ tó wà nípele àṣekágbá ní fásítì Kogi Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ileeṣẹ iroyin BBC Hausa gbiyanju lati ba Garba Sheu sọrọ lori nkan ti iyawo aarẹ sọ ṣugbọn ko gbe ipe rẹ. Ni kete ti a ba ti ri esi tirẹ gba lori ọrọ yi la o fi to yin leti. Lẹnu lọọlọ yi, ǹkan ko ṣẹnu re laarin iyawo Aarẹ Naijiria atiwọn kan to n naka si pe wọn ko jẹ ki aarẹ ṣe ijọba fun ra rẹ.",0,yoruba "Ààye wà fún àgunbanirọ láti wọ sòkòtò lábúlabú- Ọ̀gá àgbà O ní àwọn alásẹ lé gbójú kurò nínú irú ìmúra bẹ́ẹ̀ sùgbọ́n ko ni fi ojuure wo ẹnikẹni to ba lọ ran síkẹ̀tìì láti fi rópò sòkòtò ti wọ́n pèsè. Òwò ẹrú ọmọdé àti obìnrin lórí ayélujára Èyí jẹ́ ìdáhun si ìdí ti wọ́n fi le àwọn agùnbánirọ méjikan ni ìpínlẹ̀ Ebonyi làsìkò ti wan de ìbi ìpàgọ́ ìlànilọ́yẹ ọlọsẹ mẹta ti wọ́n máa n ṣe fun ẹni to ba lọ sìnrú ìlú. Ìdí ti a ko fi le gba yẹ̀rì Brig. Ibrahim sọ pé àra ìdí ti awọ ko fi le gbà ki agùnbánirọ wọ síkẹ̀tì ni pé, ko le ṣe yan bí ologun eyí to maa n wáye ni gbogbo igba fún ọ̀sẹ̀ mẹ́ta náà, àti pé ofin àkọsílẹ̀ ni fún ètò agùnbanirọ, èyi si maa n jẹ ki wọ́n ṣe sámusámú Ààye wà fún àgunbanirọ láti wọ sòkòtò lábúlabú- Ọ̀gá àgbà Oludari ọun ni lóòtọ àwọn ngba ki wọ́n lo Hijabu láti yan bi ologun sùgbọ́n orí àti ọrun nikan lo ń bò. Ètò agunbanirọ jẹ kànpa fún gbogbo ẹnikẹni to ba kàwé gboye jáde fasiti tabi poli, ti ìwé eri rẹ si jẹ ọkan pàtàkì láti fi wá iṣẹ́ lọ́jọ iwáju, èyí túmọ si pé àwọn meji ti wọ́n lé yìí ko ni ni ànfani láti ṣe iṣẹ́ ìjọba lọ́jọ́ ìwáju, bákan náà ni wan ko le gba ipo ijọba kankan lẹ́yìn wá ọ̀la. O wá fi kún pé ààye wà fún àwọn méjèèjì láti pada wá ti wọ́n ba setan láti tèlé ìlànà ti àjọ agùnbanirọ̀ là sílẹ̀ Kìí ṣe ìgbà akọkọ rèé ti irú èyí ma n ṣẹlẹ, ni ọdun 2018, wan le Tolulope Ekundayo kuro nio ogba aguibaniro Sah=gamu fun idi kan náà. Ọpọ awọn ọmọ Naijiria lori àtẹjiṣẹ́ twitter ti wa kede pe níwọ̀n ìgbà ti wan ba ti n gba mùsùlùmi láàye láti wọ ijabu nitori ẹ̀sìn, ó pọ́n dàndàn láti gba àwọn oni síkẹ̀ti náà láàye nitori o lodi si ẹ̀sì ti wọ́n náà ni Awọn agunbanirọ meji ni wọn ti fowọ osi juwe ile fun nitori wọn kọ lati wọ ṣokoto ti wọn pese fun wọn ni ipagọ ilanilọyẹ ọlọsẹmẹta nipinlẹ Ebonyi. Awọn obinrin meji ọun ṣalaye pe ṣokoto wiwọ lodi si ẹsin wọn ti wọn si kọ lati wọọ. Ninu alaye ti awọn obinrin agunbanirọ naa ṣe, awọn obinrin naa sọ pe nitori igbagbọ lo jẹ ki awọn wọ sikẹẹti dipo sokoto to jẹ alakalẹ ajọ NYSC. Alukorofun ajọ NYSC nipinlẹ Ebonyi, Ngozi Ukwuoma ṣalaye pe oludari ipagọ, Isu Josephine ri awọn mejeeji nigba ti o n ṣe abẹwo. Oludari naa ni o fi orukọ awọn mejeeji lede ti wọn n jẹ OkaforLove pẹlu nọmba idanimọ EB/19C/0523 ati Odiji Oritsetsolaye EB/19C/0530. Ni kete ti wọn mu wọn ni awọn agunbanirọ naa ti ṣalaye pe, awọn ko le wọ ṣokoto funfun pelebe ti ajọ naa fun wọn nitori pe ko ba igbagbọ awọn mu lati wọọ. Gbogbo akitiyan alaṣe ati adari ajọ naa lati mu wọn ri idi ti o fi yẹ fun wọn lati wọ ṣokoto naa lo ja si pabo. Kete ni ile ẹjọ ti o wa fun awọn agunbanirọ ni ipagọ naa dawọn lebi titapa sofin ati fifi ọwọ pa ida alakalẹ ajọ NYSC loju ti wọn si fi ọwọ osi juwe ile fun wọn lẹyin ọ rẹyin.",0,yoruba @user Lílo èdè abínibí ṣe pàtàkì púpọ̀. Ṣé Yorùbá ni wọ́n nsọ ní àjọ won àbí Gẹ̀ẹ́sì? :)),0,yoruba wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o nuni ti o ní wúlò.,0,yoruba "Ọba ri Nitori eyi, ara eni ni nfàn ojú kakaaki.",0,yoruba Ìyalẹnu ti wa ni ọjọ yẹn ti gbogbo eniyan sọ nípa ilera.,0,yoruba ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò.,0,yoruba "Awọn olugbe ilu Mogadishu naa n bẹru awọn ikilọ ikọ Al-Shabaab Nibayii ko din ni ogun papa isire to ti tẹle ikilọ yii Gẹgẹ ohun ti awọn ileesẹ iroyin lorilẹede naa n sọ, awọn asiwaju ẹgbẹ alakatakiti Al-Shabaab se ipade pọ pẹlu awọn alakoso awọn papa isire kan lolu ilu orilẹede Somalia, Mogadishu. Nibi ipade ọhun ni iroyin sọ wi pe ẹgbẹ alakatakiti naa ti tẹẹ mọ awọn to wa nibẹ leti wi pe ki gbogbo awọn papa isire aladani nibẹ lọ ti papa isire wọn pa ni kiakia. Ikọ alakatakiti Al-Shabaab sepade pẹlu awọn alakoso papa isire nilu Mogadishu Bi o tilẹ jẹ wi pe ko si ẹni to fẹ sọ ohunkohun lori ọrọ yii lati iha ijọba tabi awọn alakoso papa isire aladani ni orilẹede Somalia, sugbọn iroyin fi idi rẹ mulẹ wi peko si papa isire kan bayii ti wọn ti n gba bọọlu lorilẹede Somalia, bẹẹni ibẹru bojo ko jẹ ki awọn olugbe ilu Mogadishu. Bakanaa ni iroyin ti sọ siwaju wi pe gbogbo awọn olugbe agbegbe mẹta ti ọrọ naa kan ni wọn gba ikilọ latọdọ ikọ alakatakiti Al-Shabaab pe wọn ko gbọdọ maa tan ina iwaju ile wọn silẹ ni alẹ mọ nitori o seese ki awọn ikọ naa o maa fẹ ki lilọ-bibọ wọn lalẹ o maa di mimọ. Ni ọdun 2014, ikọ alakatakiti Al-Shabaab ṣe irufẹ ikilọ yii to rọ mọ ẹrọ ibanisọrọ alagbeka ti wọn kede nigba naa wi pe ko saye lilo ohun elo ayelujara nibẹ titi di akoko yii. Ikọ Al-Shabaab n gbimọran ati sefilọlẹ ijọba ẹsin Islam ni Somalia Ikọ ọmọ ogun ijọba lo n sakoso ilu Mogadishu, sugbọn awọn olugbe ilu naa bẹru awọn ikilọ ikọ alakatakiti yii eyi ti wọn sọ wi pe o ni ọpọlọpọ alami laarin awọn eeyan ilu naa. Ikọ alakatakiti Al-Shabaab n gbimọran ati sefilọlẹ ijọba ẹsin Islam lorilẹede Somalia lati kọ ipakọ si ohun gbogbo to ba rọ mọ ti oyinbo nibẹ. Ọpọlọpọ eniyan ni wọn si ti pa lori ẹsun pe wọn n ba awọn ohun to nii se pẹlu oyinbo tabi ijọba orilẹede naa ti wọn n sọ wi pe o n ba oyinbo se pọ. Awọn iroyin ti ẹ le nifẹ̀ si:",0,yoruba Jẹ́ kí àwọn ojú-ìwé wẹ́ẹ̀bù sọ ní pàtó àwọn _ìrísí-lẹ́tà wọn,0,yoruba ẹkọ́ ṣẹlẹ ni Eko ti gbogbo eniyan sọ o ṣe pataki. (2015),0,yoruba @user Ọ̀rọ l'ẹnù Mandiba! #Africanlanguagesmatter #yoruba #duolingo https://t.co/A4mZPs02rL,0,yoruba "Baba mí fí ọwọ́ sí Folarin gẹ́gẹ́ bíi Gómìnà, ọ̀rẹ́ tímọ́tímọ́ àwọn méjèèjì- Ọmọ Alao Akala",0,yoruba ọ̀run dídì. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "Ṣe wọn ni iku ogun nii pa akinkanju, iku odo nii pa omuwẹ, oju ija, iyẹn lori papa ni Samuel Okwaraji ku si ninu ifẹsẹwọnsẹ fun ati kopa ninu idije ife ẹyẹ agbaye ti yoo waye ni ọdun 1990. Ifẹsẹwọnsẹ naa waye ni ọjọ kejila oṣu kẹjọ ọdun 1989 pẹlu orilẹede Angola ni papa iṣere to wa ni Surulere niluu Eko. Ti o ba wa laye ni, Okwaraji ko ba ti pe ọmọ ọdun mẹrinlọgọta lati ọjọ kọkandinlogun, oṣu karun ọdun 2020 yii. Ọpọ ọmọ Naijiria papaajulọ awọn ololufẹ ere bọọlu afẹsẹgba lo n ṣe iranti ẹni 're to lọ lori ayelujara. Ajọ to n ri si ere bọọlu afẹsẹgba ni Naijiria, NFF naa ko gbẹyin, niṣe ni NFF gboṣuba rabandẹ fun ẹni ire to lọ. Ọjọ kọkandinlogun, oṣu karun ọdun 1964 ni wọn bi agbabọọlu naa Ajọ ni ohun ko le gbagbe ipa ribiribi ti Okwaraji ko ninu ere bọọlu ni Naijiria. NFF ni titi lai loun yoo maa ṣe iranti akọni agbabọọlu to re iwalẹ asa. Ǹjẹ́ o tilẹ̀ mọ Samuel Okwaraji, agbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà tó 'ṣubú lójú ìjà? Odu agbabọọlu orilẹede Naijiria ni Samuel Sochukwuma Okwaraji jẹ ni igba aye rẹ, o si ṣoju orilẹede Naijiria fun ọpọ ifẹsẹwọnsẹ. Agbẹjọro to kawe gboye ni o si tun ni iwe ẹri imọ ijinlẹ keji ninu imọ ofin ajọṣepọ ilẹ okeeere, (Masters in International Law) Ọjọ kọkandinlogun, oṣu karun ọdun 1964, ni wọn bi Sam Okwaraji ni ilu Orlu ni ipinlẹ Imo, o si gba bọọlu jẹun lawọn ẹgbẹ agbabọọẹu to lorukọ ni ilẹ Yuroopu bi AS Roma (1984-1985), NK Dinamo Zagreb (1985-1986), Austria Klagenfurt (1986-1987), VfB Stuttgart (1987-1989) ati SSV Ulm 1846 (loan) (1987-1988) Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ni ọdun 1988 ni Samuel Okwaraji kọkọ gba bọọlu fun orilẹede Naijiria ninu idije ife ẹyẹ Afrika ninu eyi ti o ti gba ọkan lara awọn goolu to yara wọle ju lọ ninu itan idije naa. Ka ni Okwaraji ko ku ni, oni yii, ni ko ba pe ọmọ ọdun marundinlọgọta lori oke erupẹ.",0,yoruba ibile. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba ojúmọ́ ire ni o èní tí í ṣe ọjọ́ ẹtì gbogbo ilẹ̀kùn ayọ̀ àti ìdùnnú tọ́tá ṣe bí àwọn tì di sísí láṣẹ bàbá lókè,0,yoruba òmìrán = giant òmìránbìnrin yìí ṣe aláàbò ọba dahomey rí this giantess was a security of the king of dahomey,0,yoruba "Biṣọbu Adepọju lo n ṣakoso daosisi ijọ naa to wa lẹkun Iwọ oorun Ekiti ni ipinlẹ naa. Gẹgẹ bi lẹta ti awọn ileeṣẹ iroyin abẹle kan ni wọn kọ ṣọwọ si Biṣọọbu naa lati fi pe ko lọ rọọkun nile, Wọn ni Biṣọọbu Adepọju ""jẹwọ pe lootọ loun ba iyawo alufaa to wa labẹ oun sun"" Bisọọbu yii lo n dari ijọ Anglican to wa ni Iwọ oorun Ekiti ni Amọṣa, Biṣọbu Adepọju ko tii sọrọ kankan lori iṣẹlẹ yii. Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsèjẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọ",0,yoruba @user @user @user @user @user Mo kí gbogbo yín oooo! Ẹ̀yin èèyàn mi rere.,0,yoruba "pa Alàji lo ni ìgbà mi owó àkokò, Olùwo ri Nitori eyi, ara eni lo ni àṣà yorubá eyti o gbe lori àìmọ́ kọ.",0,yoruba "tó kún jú, àwọn ènìyàn ni ó pa Bàbá lo tun se mú.",0,yoruba Òyó. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò.,0,yoruba "mú, Nitori eyi, ara eni lo ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba Àìmọ́ ni ó pa Ọba lo ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba """Gbogbo ija wa, ori bẹẹdi ni yoo ti bẹrẹ, ori bẹẹdi naa si ni yoo ti pari. A o ki n joko ro ẹjọ ara wa fun mọlẹbi kankan tabi ọrẹ"". Idile Benjamin Awoyẹmi ti wọn ti ṣe igbeyawo fun odindi ọgọta ọdun gba BBC Yoruba lalejo ni ile wọn. Olu Jacobs àti Joke Silva yan orúkọ ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀, àmọ́ wo ohun tó mú ìgbéyàwó wọn dúró 'Bíríkílà ni ọkọ mi, kò lọ síléèwé, àwọn ọmọ mi ti ń bímọ àmọ́ èmi fúnráàmi fẹ́ di tísà' Iwa nabi tu igbeyawo ọgbọn ọdun ka Tẹgbọn-taburo se igbeyawo ni Anambra 'O yẹ ki dokita ọpọlọ yẹ ọpọlọ mi wo' Baba Benjamin ni lati igba ti awọn fẹ ṣe iyawo lawọn ti wo bi igbesi aye ẹda ṣe maa n ri ti awọn si ti kọ iwa ara awọn lati mọ bi wọn ṣe lee ba ara wọn gbe. Afọkansi ati igbọraẹniye ṣe pataki ninu igbeyawo gẹgẹ bi baba ati mama Benjamin ṣe sọ ọ. Gbogbo ohun ti iyawo mi ba ti ṣe, a jọ mọọ ni, ko sohun to jọ pe ki n ma mọ nipa nkan ti iyawo mi ba ṣe. Ni ti mama Benjamin, o ni oun ṣa n gbadura pe ki Ọlọrun tọ oun sọna nigba ti baba Benjamin kọ inu ifẹ si i, Ọlọrun si lo tọka rẹ si i ti oun ṣe fẹ ẹ. ""Ó kéré ó tóbi, ko si iru igbeyawo teeyan le ṣe ti ko ni ni iṣoro"". Amọ Iyaafin Benjami ni bo ba ṣe n yọju ni Ọlọrun n mu ọna abayọ ati ojuu wa. Iriri awọn mejeeji yii kọja ohun ti eeyan le lọ san owo lati jokoo si kilaasi maa kọ. Ẹkọ pọ ti ẹ le kọ ti gege wa o ni lee kọ tan afi ki ẹ wo o ninu fidio naa.",0,yoruba "Sunday Igboho: N kò fẹ́ oyè ọ̀gá àgbà páta fún ikọ̀ Amotekun nílẹ̀ Yorùbá Ibeere to n ja kaakiri ree bayii lẹyin ipade apapọ awọn gomina ipinlẹ ilẹ Yoruba to waye lọjọ Aje nilu Akurẹ, tii ṣe olu ilu ipinlẹ Ondo. Sunday Igboho lo bọ si agbami ojutaye iroyin lẹyin to gbe gbedeke ọjọ meje kalẹ fawọn Fulani nilu Igangan lagbegbe Ibarapa laipẹ yii. Igboho ni ki awọn ọdaran Fulani naa ko aasa wọn nitori iwa ifipabanilopọ, ijinigbe, idigunjale ati ipaniyan ti wọn n hu. Awọn eeyan kan to sunmọ Igboho bi iṣan ọrun, la gbọ pe wọn lu awo ọrọ naa si awọn akọroyin leti. Amọ nigba to n fesi lori ahesọ ọrọ naa fun awọn akọroyin, ti BBC Yoruba wa lara wọn, Sunday Igboho ni oun ko fẹ ipo oludari patapata fun ikọ Amotekun yika ilẹ Yoruba, ti wọn n yọ ọ naa. O ni oun to jẹ oun logun bayii ni bi awọn ọdaran Fulani yoo se fi ilẹ Yoruba silẹ, ti alaafia yoo si jọba pada. Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik ""N ko nilo ipo olori Amotekun tabi owo lọdọ ẹnikẹni tabi oloselu kankan. Alaafia fun awọn Yoruba lo jẹ mi logun lasiko yii, kii se ipo rara."" Sunday Igboho wa rọ awọn gomina to n daba iyansipo naa lati mase fi oun jẹ oye naa. Lootọ ni awọn kan lara awọn alatilẹyin Sunday Igboho ko fọwọ si igbesẹ naa, amọ sibẹsibẹ ọpọ wọn lo ti gba aba naa wọle gẹgẹ bi a ṣe gbọ. Ikọ Amọtẹkun lawọn ijọba ẹkun iwọ oorun gusu orilẹede Naijiria gbe kalẹ lati koju gulegule awọn Fulani darandaran to n da omilẹgbẹ ọran kaakiri ẹkun naa. Ẹ̀rú kò bà mí lórí ìkéde ọ̀gá ọlọ́pàá láti gbé mi sí àhámọ́ - Sunday Igboho Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe Ajafẹtọ ọmọ Yoruba to lewaju lori ọrọ aawọ to da lori gulegule awọn Fulani si ẹya Yoruba, Sunday Igboho ti sọ pe, oun ko bẹru ihalẹ atimọle ti awọn alaṣẹ n daba rẹ. Ninu fọnran fidio kan to lu ayelujara pa ni o ti sọ ọrọ yii, to si tun dupẹ fawọn agbaagba Yoruba fatilẹyin wọn. Igboho sọ pe ''awọn darandaran ko le le wa kuro lori ilẹ wa, oju wa ti ṣi bayi, ayafi ti wọn ba fẹ pa wa lo ku'' O wa kesi awọn alatilẹyin rẹ lati mase kọ ẹnu eebu sawọn ọba alade ilẹ Yoruba. Bakan naa ni Igboho n fọwọ gbaya pe ẹru ko ba oun rara lori asẹ ọga agba ọlọpaa to ni ki wọn mu oun wa. ''Ẹ maṣe tẹnbẹlu awọn ọba Yoruba wa tabi ki ẹ bẹnu atẹ lu wọn. Mo fi ogun bura, inu awọn naa ko dun si ohun to n sẹlẹ yii. Wọn ti n sọrọ soke bayii'' O ni ""idi ree ti gbogbo wọn ati awọn olori ilẹ Yoruba fi dide pe ki wọn ma ṣe mu Sunday Igboho."" ''Ohun to bani ninujẹ ni bi wọn ṣe n ṣe wa baṣubaṣu, ti wọn n pa awọn ọmọ obinrin wa, ti awọn afurasi apaayan darandaran yii tun n fipa bawọn lo pọ.A ko le lọ si oko mọ, a ko le lọ sodo.O to gẹ!'' Bi a ko ba gbagbe laipẹ yi ni ọga patapata ọlọpaa Naijiria paṣẹ ki Kọmisana ọlọpaa ni ipinlẹ Oyo mu Sunday Igboho wa si Abuja lati wa jẹjọ. Eyi waye lẹyin to lọ si Ibarapa lati lọ sọ fun olori awọn Fulani nibẹ pe ki wọn kuro nilẹ awọn laarin ọjọ meje. Sunday Igboho sọ̀rọ̀ fún ìgbà àkọ́kọ́ lẹ́yìn àbẹ̀wò rẹ̀ sí Igangan Eekan ọmọ Yoruba nni, Oloye Sunday Adeyẹmọ, ti ọpọ mọ si Sunday Igboho, ti sọrọ fun igba akọkọ lyin to sabẹwo silu Igangan lọjọ Ẹti. Sunday Igboho ṣalaye pe asiko to fawọn alakoso iṣejọba ni ilẹ Yoruba lati mọ pe, bi wọn ba kuna lati mojuto abo araalu to dibo fun wọn, ko si igba ti araalu o ni gbe ara wọn nija. Oloye Sunday Igboho ṣalaye eyi ninu awọn atẹjade kan to fi sita loju opo Twitter rẹ, @SundayIgboho2 Igboho ni o ṣeni laanu pe awọn iwa ti aye rẹ o si fawọn ọmọ Yoruba to tẹdo si agbegbe miran lorilẹede Naijiria, ni wọn n fi n lọ Yoruba lori ilẹ won. Oloye Igboho ni omilẹgbẹ awọn eekan ọmọ Yoruba lo ti jade laye nipasẹ awọn agbebọn darandaran Fulani, ninu eyi to ti darukọ gbajugba oniṣegun ibilẹ ni, ti ọpọ mọ si ọkọ Oloyun ati Ọmọwe Aborode. ""O ko lee ri ọmọ Yoruba ko lọ maa paniyan ni ipakupa nilu Kano. Bi ọmọ Yoruba ba gba Hausa/Fulani loju, wọn lee tori rẹ bẹ ẹ lor,i ka to wa sọ pe ko ba nnkan oko jẹ"" O ni ko si nnkan ti ijọba tii ṣe lori gbogbo awọn ti awọn afurasi Fulani darandaran pa nilẹ Yoruba, sibẹ ojojumọ l'ẹmi n ṣofo si. Igboho ni gbogbo awọn to n sọ ahesọ ọrọ kiri pe nitori owo, ipo abi gbajumọ loun se gbe igbesẹ naa, ko mọ iru eeyan ti oun jẹ ni. O fikun pe gẹgẹ bi ọmọ agbegbe Oke Ogun ni ipinlẹ Ọyọ, asiko kan wa sẹyin to jẹ pe ifọkanbalẹ l'awọn eeyan fi n gbe aye wọn lagbegbe naa eleyii ti kori bẹẹ mọ bayii. ""L'awọn igba naa a maa n pada lati oko nibii agogo kan oru laisi ibẹru tabi ikayasoke pe ẹnikan le e kọlu wa."" O ni nnkan o fara rọ mọ lagbegbe naa nitori gulegule awọn kọlọransi darandaran Fulani kan. Sunday Igboho wa fi ọwọ gbaya pe idunkooko ileesẹ ọlọpaa ko le da jinni-jinni bo awọn eeyan ipinlẹ Oyo nitori o gba oun ni akoko ati igbaradi ki oun to gbe igbesẹ to lagbara yii, eyi to jẹ ipinnu to bọ sasiko. O fikun pe igbesẹ́ naa waye nitori ara wa ati ọjọ ọla iran to n bọ.",0,yoruba alífábẹ́ẹ̀tì Odùduwà tuntun náà .,0,yoruba ibile. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.,0,yoruba "Rochas Okorocha: Buhari yoo s'ọrọ lori ibo 2019 laipẹ Okorocha sọrọ yi ni ọjọbọ lẹhin ti oun ati awọn gomina ẹgbẹ rẹ yoku ṣe ipade pẹlu Aarẹ Buhari nilu Abuja lalẹ ana. Ninu ifọrọwanilẹnuwo ranpẹ pẹlu awọn oniroyin lẹhin ipade naa, Okorocha sọ pe awọn wa lati bẹ Aarẹ Buhari pe ki o jọwọ gbe'gba ibo lọdun to n bọ. ""A sọrọ lori ọpọlọpọ awọn ọrọ ti o niiṣe pẹlu eto orilẹede yi lapapọ, nipa ẹgbẹ o'selu APC ati eto idibo fun ọdun 2019."" Gomina ipinlẹ Imo naa salaye siwaju sii wi pe, ""Ohun ti agbajọpọ awọn gomina ẹgbẹ oṣelu APC n fẹ ni ki Aarẹ Buhari o du ipo aarẹ lẹẹkan sii nitori iṣẹ takun takun rẹ ti o ti ṣe lati ọdun diẹ sẹyin. A ni igbagbọ pe bi o ba tẹsiwaju, orilẹede yii yoo dara sii. "" O tun sọ pe Aarẹ Buhari ti beere pe ki awọn gomina ""fun oun ni akoko diẹ lati ronu sii, ati pe oun yoo ba awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria sọrọ laipẹ ti oun yoo ba dupo"". Awọn gomina ẹgbẹ oṣelu APC ti n ba Aarẹ Buhari sọrọ lati gbe'gba ibo Awọn gomina ẹgbẹ oṣelu APC ti n ba Aarẹ Buhari sọrọ lati gbe'gba ibo. Wọn ṣe ipade pẹlu rẹ ni ọsẹ to kọja ni ilu rẹ ni Daura lori ọrọ yii bakanna. Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si:",0,yoruba "Ala ti ko lee ṣẹ ni ''server'' ti oludije ipo aarẹ fẹgbẹ oṣelu PDP, Atiku Abubakar n beere fun. Atiku n beere esi idibo ibo aarẹ orilẹ-ede Naijiria to waye ninu oṣu keji, ọdun 2019. Kọmiṣọna ajọ eleto idibo INEC, Festus Okoye lo ṣalaye ọrọ naa nigba to ba BBC sọrọ lọjọ Ẹti. Ọgbẹni Okoye sọ pe esi ibo aarẹ ko si ninu ''server'' INEC tabi ẹrọ kọmputa nibi kankan. O ṣalaye pe ofin eto idibo lorilẹ-ede Naijiria ko sọ pe ki ajọ INEC ko esi idibo aarẹ sinu ''server'' kọmputa INEC. Okoye ni ọwọ ni wọn fi kọ esi ibo ni gbogbo ibudo idibo kaakiri orilẹ-ede Naijiria, eleyi ti gbogbo awọn aṣoju ẹgbẹ osẹlu to wa nibẹ foju ri ti wọn si ni ẹda rẹ. O sọ pe awọn esi ibo yii ni wọn fi ṣọwọ si ajọ INEC lawọn ipinlẹ to fi de olu ile iṣẹ INEC nilu Abuja. Ẹwẹ, l'Ọjọbọ ni ajọ INEC ṣi aṣọ loju ọrọ yii nigba to sọ fun igbimọ igbẹjọ ibo aarẹ l'Abuja pe oun ko ni ''server'' ti Atiku ati PDP n beere fun.",0,yoruba Osun..... Ire wo le de...,0,yoruba "Won peyin lole etun gbe omo eran jo, bi Ebora Owu se ba Yar'Adua soro ti oko Nijeria si ijogbon. @user e ba wa soro ni ero amowun maworan https://t.co/nhFJGEz7Va",0,yoruba "Manchester United ti n gbaradi de lilọ Paul Pogba kuro lọdọ wọn. Wọn si ti fẹ ẹ fi ẹnu ko lori rira agbabọọlu orilẹ-ede Serbia, Sergel Milinkovic-Savic, ni aadọrin miliọnu Pọnun. (Mirror) Amọ ṣa, o ṣeeṣe ki Pogba o ṣi lo ọdun kan si i ni Old Trafford, eyi to le mu ifasẹyin ba rira ti wọn fẹ ra Milinkovic-Savic. (Express) Bakan naa ni o ṣeeṣe ko di dandan fun Manchester United lati wa ọgọrin miliọnu Pọnun ti wọn yoo fi ra agbabọọlu England, Harry Maguire lẹyin ti Eric Bailly fi orunkun ṣeṣe lasiko idije ọlọrẹsọrẹ pẹlu Tottenham ni Ọjọbọ. (Mirror) Akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu Liverpool, Jurgen Klopp ti ni ko si n to o jọ rara pe oun fẹ ẹ ra Gareth Bale lati ọwọ Real Madrid. O ni afojusun oun ni lati kọ ẹgbẹ agbọọlu to dantọ, kii kan ṣe lati ko eniyan jọ saa. (Independent) O dabi ẹni pe ko si bi agbabọọlu iwaju fun Juventus ati Portugal, Cristiano Ronaldo ṣe mọ idunna-dura a ṣe to, ko ni le fi ọrọ yi atamatase Paris St-Germain, Neyman lọkan pada lati darapọ mọ idije Serie A, nitori o da bi ẹni pe Neyman ti pinnu lati pada si Barcelona. (Star) Borossia Dortmund naa ti n duna-dura lati ra ọmọ orilẹede Brazil, Malcom ni miliọnu mejilelogoji Euro. (Goal) Akọnimọọgba Napoli, Carlo Ancelotti ni ọkan oun balẹ bi omi inu amu pe ẹgbẹ agbabọọlu oun ni yoo ra James Rodriguez lati ọwọ Real Madrid. (Marca) Everton naa ti sọ fun Crystal Palace pe awọn ṣetan lati san ọgọta miliọnu Pọun fun rira atamatase orilẹ-ede Turkey, Cenk Tosun ni igba kan naa pẹlu Wilfred Zaha. Amọ aya wọn ṣi n ja pe o ṣeesẹ ki Chelsea o ja a gba mọ wọn lọwọ. (Telegraph) Atamatase ni, Moussa Dembele naa yoo wa lara awọn to ṣeeṣe ki wọn o ta Romelu Lukaku. (Sky Sports) Ẹgbẹ agbabọọlu Wolves naa ti n ba Real Madrid sọrọ lati ra Jesus Vallejo fun saa kan, nigba ti Real Madrid naa ti n sunmọ bebe ati fẹnuko lati gba miliọnu mẹtadinlogun Pọnhun lọwọ AC Milan lati ra atamatase, ọmọ orilẹede Italy Patrick Cutrone. (Mail)",0,yoruba "o pataki. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa òkè: ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba àkerekere. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè.,0,yoruba ẹkọ́ ṣẹlẹ ni Eko ti gbogbo eniyan sọ o dara. (2018),0,yoruba àìmọ́. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó ga jù.,0,yoruba Leicester Cityvs Manchester United: Iheanacho lu Manchester United bí aṣọ òfi kúrò nínú ìdíje FA Cup,0,yoruba "Bẹẹ ni ọrọ ri nibi eto idanilẹkọ ọlọdọọdun, ikejila iru rẹ, ti wọn gbe kalẹ lati sami ọjọ ibi asaaju ẹgbẹ oselu APC, Asiwaju Bola Tinubu nilu Kano. Idi ni pe ọpọ awọn eeyan jankan jankan to yẹ ko peju sibi ayẹyẹ naa ni ko le lọ nitori oju ọjọ ti ko dara. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Oju ọjọ to mẹhẹ naa lo se idiwọ fun baalu wọn lati fo lọ silu Kano nibi ti idanilẹkọ ọjọ ibi naa ti n waye. Onpetu Ijeru: Akala ní torí Aláàfin kò ṣúgbàá òun fún sáà kejì, ló ṣe ní kí pín ipò alága Lara awọn eekanlu ti oju ọjọ sediwọ fun lati peju sibi ayẹyẹ naa ni igbakeji aarẹ Yemi Osinbajo, Minisita fọrọ abẹle, Rauf Aregbesola ati olori ile asojusofin nilẹ wa, Femi Gbajabiamila. Awọn yoku ni akọwe fun ijọba apapọ Naijiria, Boss Mustapha, Minisita feto iroyin ati asa, Lai Muhammed atawsn eeyan jankan jankan miran. Nigba to n fidi isẹlẹ yii mulẹ ni oju opo Twitter rẹ, agbẹnusọ fun igbakeji aarẹ, Laolu Akande kede pe ori ayelujara ni aarẹ ati igbakeji rẹ yoo ti wo eto naa. O ni aarọ yii lo yẹ ki Yemi Osinbajo tẹ baalu leti lọ silu Kano fun idanilẹkọ ti wọn fi sọri ọjọ ibi kọkandinlaadọrin Asiwaju Bola Tinubu. Amọ Akande tẹsiwaju pe oju ọjọ ti ko dara lo se idiwọ fun igbakeji aarẹ lati peju sibi eto naa. Buhari kò ṣèlérí pé Naira kan yóò bá Dọ́là kan dọ́gba - Iléeṣẹ́ ààrẹ Ileesẹ aarẹ Naijiria ti sọrọ lori ọrọ kan to gba igboro kan pe owo Naira ilẹ wa yoo ba owo Dọla kan dọgba ni kete ti Muhammmadu Buhari ba gba akoso. Ọrọ yii ni awọn eeyan kan sọ pe Buhari fi se ileri lasiko ipolongo ibo rẹ lọdun 2015. Amọ nigba to n fesi lori ọrọ ọhun, Oludamọran fun aarẹ Buhari feto iroyin, Femi Adesina salaye pe aarẹ ko figba kankan seleri bẹẹ fawọn ọmọ Naijiria. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Adesina, lasiko to n kopa lori eto ori tẹlifisan kan nilu Eko fikun pe ayederu ati iroyin eke ni ọrọ bẹẹ, ko waye ri . ""Iru ọrọ bayii ko waye ri. Ayederu iroyin ni, ti ko le see se."" Onpetu Ijeru: Akala ní torí Aláàfin kò ṣúgbàá òun fún sáà kejì, ló ṣe ní kí pín ipò alága Bẹẹ ba gbagbe, o ti to ọjọ mẹta tawọn eeyan kan ti n ni aarẹ Buhari niran nipa awọn ileri to se lasiko eto ipolongo ibo rẹ lọdun 2015. Ileri pe Buhari ni Naira kan yoo fi ẹgbẹ kẹgbẹ pẹlu Dọla kan lọdun 2015 si ni wọn n gba bii ẹni gba igba ọti lawọn oju opo ayelujara gbogbo. Lọwọlọwọ bayii, lẹyin ti aarẹ Buhari ti lo ọdun mẹfa lori aleefa, ọrinlenirinwo naira ni wọn fi n se pasipaarọ fun dọla kan bayii. 'Òde ìnáwó làwọn èèyàn ma ń rò bí wọ́n bá rí Ankara, ìgbà tí wọ́n rí i lára àga tí mo ṣe, ẹnu wọn ò padé mọ́' Idi si ree ti awọn ọmọ Naijiria fi n lọgun pe isẹlẹ naa tako ileri ti aarẹ Buhari se fun awọn lọdun 2015 to fẹ dije. Iná ṣẹ́yọ lẹ́bàá mọ́ṣálááṣí Anabi ní Medina Ina ṣẹyọ lẹgbẹ mọṣalaaṣi Anabi Mohammad ni Medina ni orilẹede Saudi Arabia. Oriṣiiriṣii fidio to lu ori opo Twitter pa ṣe afihan bi ina ọhun ṣe n jo ile kan, to wa lẹgbẹ mọṣalaaṣi Anabi ti eefi ṣi gbalẹ nibẹ. Ko si ẹni to kọkọ mọ ohun to ṣe okunfa iṣẹlẹ ọhun. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Amọ, wọn ti pada pa ina ọhun to n jo bi ina sufuru tẹlẹ. Haramain Sharifain to fi awọn fidio naa lede loju opo Twitter rẹ sọ pe, kete tawọn oṣiṣẹ alaabo Civil Defence de ibi iṣẹlẹ naa ni wọn pana ọhun. Gbogbo bi iṣẹlẹ naa ti waye kawọn panapana to de lo wa ninu fidio ti Sharifain fi soju opo Twitter rẹ.",0,yoruba "Mi o loye ohun to ṣẹlẹ - mo ba wo oju opo ikansiraẹni Facebook ati Twitter mi, ọpọ lẹta ni mo ti gba ti gbogbo wọn n bere ọrọ kan naa lọwọ mi pe ṣe emi ni ""Michelle Damien"", akọroyin iroyin aburu kan to n da wahala silẹ ni gbogbo Senegal? Lọkan ninu awọn to fọrọ raṣẹ ba ni "" ẹsun iwa ibajẹ kan n mi orilẹede mi titi, wọn si ti darukọ rẹ"". "" Akọroyin ọmọ orilẹede Senegal ni mi mo si ni lati ba ọ sọrọ"" Eyi ṣẹlẹ ni o ku ọsẹ diẹ ṣaaju idibo aarẹ ni Senegal bẹẹ si ni ẹni ti iroyin naa n ba wi Ọgbẹni Sonko jẹ ọkan lara awọn to n gbena ibo yii woju aarẹ Macky Sall. Bi o tilẹ jẹ pe gẹgẹ bi oniroyin aṣewadii, mo ti kọ ọpọlọpọ iroyin nipa Senegal atawọn ileeṣẹ epo. Gbogbo wọn fẹ mọ boya emi ni mo kọ iroyin kan ti akọle rẹ jẹ ""Ipenija lilo awọn nkan alumọni ilẹ Afirika lọna aitọ"" eyi ti wọn gbe jade loju opo ayelujara ileeṣẹ iroyin kan ni Ghana lọjọ kẹsan oṣu kinni ọdun 2019. Iroyin naa n fẹsun ka oludije fun ipo Aarẹ ẹgbẹ alatako lorilẹede Senegal, Ousmane Sonko pe o gba abẹtẹlẹ gọbọi lọwọ ileeṣẹ epo ilẹ Yuropu wọn si gbe e jade pe ""Michelle Damsen"" lo kọ ọ"", lẹta meji pere lorukọ yii fi yatọ si temi - Michelle Madsen. Badagry Historical Wells: Omi inú kànga Wawú ló ń kó ọpọlọ àwọn ẹrú lọ Ẹwẹ, akọroyin abẹlẹ bii ọtẹlẹmuyẹ lai gbowo oṣu ni mi, aimọye iroyin ti mi o kọ ni wọn ti forukọ mi si - mo mọ pe emi kọ ni mo kọ eleyi ti wọn n sọ yii ṣugbọn awọn koko iroyin to jade ninu rẹ gan mi mi titi bo ṣe wa di pe wọn lọ ọ mọ mi lẹsẹ ko ye mi. Kia ni awọn to n fi koko ọrọ ṣe ọfintoto ṣafihan pe iroyin ofege ni. Ileeṣẹ kan ti wọn darukọ ninu rẹ Oxfam sọ fun mi pe awọn ko gba owo kankan lọwọ ileeṣẹ epo ṣugbọn awọn ti ṣagbatẹru sisanwo ri fun idanilẹkọ kan fun Ọgbẹni Sonko. Ootọ eleyi lasan lee jẹ ki awọn eeyan gba iroyin naa gbọ. ""Gbogbo ọṣẹ ti mo ngbiyanju lati fi wẹ mọ, pabo lo n ja si"". Onimọ kan sọ fun mi pe awọn to lee ri anfani lara iru iroyin bayii ni ijọba Senegal tabi awọn ileepo. Ọdun kan kọja, sibẹ mi o ri ẹnikankan to n jẹ ""Michelle Damsen"" boya mi o si ni mọ ọ lailai. Mo ṣaa fẹ mọ ẹni to n jẹ Michelle Damsen yii, mo tun wadii kiri . Nigba ti aṣiri maa fẹ tu, mo tọpasẹ iroyin naa titi de ileeṣẹ iroyin akọkọ to gba a, a pe nọmba ẹni to mu u wa lo ba di ti akọroyin Senegal kan ṣugbọn to n gbe ni Amẹrika, Baba Aidara - ọrẹ mi ree e. Ẹwẹ, Aidara ni o ti, oun kọ lo kọ ọ. O ni oun gbero pe wọn lo ọna ipa lo nọmba oun ni oun si fura si ijọba orilẹede Senegal. Michelle n sabewo sawon oju opo kan lori erọ kọmputa Awọn oniroyin Senegal ni iroyin ofege ti gbilẹ lẹnu perete ki idibo waye. Awọn ikọ akọroyin fun aarẹ kọ lati ba mi sọrọ. Gbogbo eyi da bii iji lile fun awọn oniṣẹ iroyin to si waye laarin ọjọ diẹ. Bí wọ́n ṣe kó mi mọ́ rògà ìròyìn òfégè kan tó leè kóbá olùdíje Ààrẹ ẹgbẹ́ alátako Nigbẹyin gbẹyin, gbogbo iroyin ofege ni wọn ti yọ kuro nita ti wọn si ti tun un kọ. Ṣugbọn abawọn naa ṣi wa nibẹ - eyi si lo le ju to si buru jai nipa titan iroyin ayederu kalẹ paapaa to tun wa bọ si asiko idibo. Bakan naa pẹlu gbogbo ohun ti mo la kọja, o to ki eeyan fi sọkan pe igba mii ti ""Michelle Damsen"" ba tun jẹ jade ninu iroyin, iroyin naa ati ipa rẹ yoo rin jina gan.",0,yoruba "Lati ẹnu ọna afin ni ipele ipele ati isọri isọri awọn eeyan agbaye ti n ko okiki Ọba tuntun to gori itẹ gẹ́gẹ́ bi ọdọ. Ọba Oloyede Akinghare lo gba ade gẹgẹ bi ọba to kere julọ nilẹ Yoruba. BBC Yoruba lọ ṣe Kaabiyesi rẹ ni aafin Ọba Oloyede nilu Okelusẹ gẹgẹ bi Ọbalayé tó kéré jùlọ nílẹ̀ Yorùbá, Oloyede Akinghare tó gbadé . Lootọ, o ṣeeṣe ki iru eyi ti waye ri lawọn ẹya orilẹede Naijiria mii ṣugbọn ko wọpọ, nilẹ Yoruba, ipinlẹ Ondo ni Ọba to kere julọ ti kọkọ ṣẹ wa. Oloyede Akinghare gun ori itẹ gẹgẹ bii Kabiyesi Arujale Ojima ti ilu Okelusẹ ni ijọba ibilẹ Ọsẹ, ni ipinlẹ Ondo. Lẹyin ọdun mẹta ti baba rẹ waja lo gori itẹ. To fi mọ awọn ọmọ ileẹ̀kọ́ rẹ lo wa tilu tifọn ti wọn n yẹ ọba wọn si. Gẹgẹ bi ọkan lara oun ti a mubọ, Ọba Oloyede ṣi wa lẹnu ẹkọ rẹ, o ni ipo ti oun wa ko fa idiwọ kankan fun ẹkọ oun. ""Ọlọrun maa ran wa lọwọ, nkan ti mo ba ti sọ naa ni ilu maa tẹle ti wọn maa gba bẹẹ́"". Ẹwẹ, Kabiyesi Akinghare ni ko tii si ọrọ fifẹ iyawo lọrọ oun o!",0,yoruba ibile. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá.,0,yoruba "Baba Ijesha, Olanrewaju Omiyinka: Wo ibi tí ọ́rọ́ ìgbẹ́jọ́ Baba Ijesha dé dúró báyìí láti osù kẹrin, ọdún 2021",0,yoruba egbe agbaboolu arsenal tun fidi remi nirole yii o ga o,0,yoruba Ìwádìí ti fi ìdíi rẹ̀ múlẹ̀ wípé òkúta iyùn ní ń gba ìdá 90 etídò Tobago sílẹ̀ - lọ́wọ́ ọ̀gbàrá tí ìgbé omi ń fà .,0,yoruba "Ní ìlú kan, Ìyá ni olùkó. ìrìn ìròyìn. Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba "Mo sa ipá mi ni NIMC gẹ́gẹ́ bii ọmọ Nàìjíríà rere ṣùgbọ́n mo fẹ́ tẹ̀siwaju ninu ìran míràn Oyinlọla kọwe ìfipòsílẹ̀ náà ránṣẹ́ sí Aarẹ Buhari lọjọ kẹsan an osù karùn-ún. Ó ní ""Aarẹ, mo dúpẹ́ pé mo ni oore ọ̀fẹ́ láti sin ilẹ̀ baba mi gẹ́gẹ́ bi ipò ti mo dìmú. Mo ṣiṣẹ́ bi mo ṣe ni agbára to láti ṣee, ṣùgbọ́n o di dandan fún mi láti fipò yìi sílẹ̀, ki n lè gbájúmọ́ iṣẹ́ òṣèlù ti mo fẹ́ tọrun bọ̀ bayii. Emi kò jẹ́ dalẹ̀ ọga mi lẹ́nu iṣẹ́, ṣùgbọn mo fẹ́ tọ ipa ti ọkàn mi fẹ́ lásìkò yii ninu òṣèlu. Idí niyii ti mo ṣe gbọ́dọ̀ fi ipò mi silẹ̀ ni NIMC. Inú mi dùn fún bi ẹ ṣe gbàmi laaye láti sin ilẹ baba mi. Ní bayii, àsìkò ti tó fún mi láti sin àwọn ènìyàn mi lọna miran"". Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọ̀tẹ̀ tó pa wọ́n pọ̀ náà ló ń tu wọ́n ka Wàyí ò, ẹgbẹ́ òsèlú PDP, tó jẹ́ ẹgbẹ́ òsèlú alátakò gbòógì ní ilẹ̀ Nàíjíríà, ti fèsì lórí ìsẹ̀lẹ̀ yìí. Ọ̀gbẹ́ni Diran Odẹyẹmi, to jẹ́ oluranlọwọ alukoro ẹgbẹ́ òṣèlú PDP sàlàyé pé, ìgbésẹ́ Oyinlola yìí kò ya ẹgbẹ òṣèlú PDP lẹ́nu nitori pe kìí se ara wọn tẹ́lẹ̀-tẹ́lẹ̀. Ó fi kún pé ọ̀tẹ̀ tó pa wọ́n pọ̀ náà ló ń tu wọ́n ka. Oyinlọla kọ̀wé fipò rẹ̀ sílẹ̀ ni NIMC Odẹyẹmi sọ̀rọ̀ lori àìsí agbára òfin lòdì sí ki àwọn ènìyàn maa ṣe aṣẹ́wó òṣèlú lati égbẹ́ òṣèlú kan si ìkejì. O yẹ ki wọn maa padanu ipò wọn ti wọn ba ti kuro lati inu ẹgbẹ òṣelu kan si omiran ni.",0,yoruba "àkóbì asin. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "fè joko, Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba yi ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn yì í tún ṣe àwọn iṣẹ́ tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó wáyé..,0,yoruba ti o nuni ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó wáyé.,0,yoruba ShankhaNidhi । Èyí ni ilé ọgọ́rùn - ún ọdún sẹ́yìn mìíràn ní Dhaka .,0,yoruba "Ṣẹ́ẹ mọ̀ pe Yoruba ni ""bi wọn ṣe n ṣe nilee wa, eewọ ibomii ni lo mu oriire ba Imaamu Nuru Khalid to sọrọ si aarẹ Buhari to si tori rẹ gba idaduro ni Mọṣalaṣi. Imaamu Mọṣalaṣi to wa ni agbegbe Apo Legislative Quartres ni Abuja eyi to ṣẹ gba idaduro iyẹn Sheik Nuru Khalid ti riṣẹ mii bayii. Iroyin ni awọn alaṣẹ ati oludari Mọṣalaṣi Jumaa tuntun kan ni Area 11 ni ẹyin Banki apapọ Naijiria ti ni ko bẹrẹ iṣẹ lẹsẹkẹsẹ ni Jumaa ọjọ Jimoh to n bọ, ọjọ kẹjọ oṣu Kẹrin. Ìjọba pàṣẹ fún àwọn iléeṣẹ́ ìbánisọ̀rọ̀ láti fi òfin de ìpè lórí fóònù àwọn tí kò so NIN mọ́ nọ́mbà wọn A máa ń lọ yọjú wo Yinka Quadri tó bá ń ṣe fíìmù ládùúgbò wa - Ẹ wo bí Dejo Tunfulu ṣe bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ Tíátà Khalid gba idaduro lẹyin to sọ ọrọ alufansa si Aarẹ Muhammadu Buhari nitori ikọlu si ọkọ oju irin to ṣlẹ lọjọ Aje to kọja ni ọna Abuja si Kaduna. Ẹwẹ, oun funrarẹ ṣapejuwe idaduro rẹ gẹgẹ bi ara ifarada to oun ni lati la kọja pe oun ni imọlara iya to n jẹ awọn araalu ati pe o sọ otitọ. Khalid fi ọrọ sita pe ""nipa ore-ọfẹ Ọlọrun, n o maa dari awọn olujọsin mi ni ọjọ Ẹti yii, nitoripe gẹgẹ bii adari ẹsin, a nilo ibi kan lati maa darapọ mọ"". Bí wọ́n ṣe yọ ìmáàmù Mọ́ṣáláṣí Apo, Sheik Nuru Sẹnetọ Saidu Dansadau to jẹ alaga igbimọ Mọṣalasi Apo, niluu Abuja ti sọ pe awọn ti da Sheik Muru Khalid duro lẹyin ti wọn ti kọkọ ni ko lọ rọọkun nile ṣaaju. Sẹnetọ Dansadau ṣalaye fun BBC pe awọn gbe igbesẹ naa lẹyin ti Imaamu ọhun kọ lati tuba lẹyin awọn ọrọ to sọ ninu waasi rẹ lọjọ Ẹti. Ninu iwe idaduro ti wọn fi ranṣẹ si Imaamu naa, wọn ni awọn ṣawari pe ko kabamọ ohun to ṣe lẹyin ti wọn ni ko lọ rọokun nile, eredi ree ti ijiya rẹ fi gbe pẹẹli si. Lẹta ọhun ka pe ""Sheik, iwọ funra rẹ mọ ohun ti ẹsin Islam sọ nipa ibọwọfun ati eto."" ""Amọ iha ti o kọ si bi a ṣe ba ọ wi lori awọn ọrọ ti o sọ fihan pe o ko kabamọ ohun ti o ṣe."" Ki ni ẹṣẹ Sheik Nuru Khalid? Ọjọ Ẹti, to jẹ ọjọ kinni, oṣu Kẹrin, ọdun 2022 yii ni Imaamu naa sọrọ nipa ikọlu ọkọ oju rin to waye ni ipinlẹ Kaduna. Ninu waasi naa lo ti sọrọ tako ijọba apapọ lori ikuna rẹ lati bojuto eto abo to mẹhẹ ni Naijiria. Ti ẹ ko ba gbagbe, ọjọ kejidinlọgbọn, oṣu Kẹta ni awọn agbesumọmi kọlu ọkọ oju irin naa to n lọ lati ilu Abuja si Kaduna, nibi ti wọn ti pa eeyan mẹjọ, ti wọn si tun ti ji awọn mọkanlelogun mii gbe. Amọ lọjọ Aje, Imaamu naa sọ fun ileeṣẹ iroyin BBC pe oun ko kabamọ ọrọ ti oun sọ. O ni o dun oun lọpọlọpọ pe alaga igbimọ to gba iṣẹ lọwọ oun yii jẹ ọmọ bibi ipinlẹ Zamfara, nibi ti ko si abo kankan nibẹ. Sheik Muru Khalid fi kun pe Ọlọrun nikan lo maa n gbe eeyan de ipo giga ati pe oun ko ni dẹkun lati maa sọ ootọ. Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin? Awuyewuye ti n waye lori ayelujara lẹyin ti awọn alaṣẹ mọṣalaasi kan ni Apo, nilu Abuja da imaamu mọṣalaṣi naa duro. Ọjọ Ẹti ni iroyin sọ pe Sheikh Nuru Khalid sọ ninu waasi rẹ pe ko dara bi aarẹ Buhari ṣe kọ lati lọ si ipinlẹ Kaduna lẹyin ikọlu awọn agbesunmọmi si ọkọ reluwe. Kaakiri loju opo ayelujara ni ọrọ yi ti n mu iriwisi ọtọọtọ wa ti awọn ọmọ Naijiria si ni o ku diẹ kaato pẹlu bi wọn ṣe da imaamu yi duro. Ikọlu to mẹnu ba ninu iwaasu rẹ jẹ eleyi to n kọ awọn araalu lominu nitori iye ẹmi to ba lọ. Nilu Kaduna ni awọn agbesunmọmi ajinigbe ti da ọkọ reluwee lọna ti wn si sọ ado oloro si oju irin. Ninu ikọlu yi, o kere tan eeyan mẹjọ ni ijọba sọ pe o padanu ẹmi wọn ti awọn ọpọ si farapa. Titi di ba ṣe n sọrọ yi awọn eeyan kan wa ti wọn ko mọ ibi tawọn ajinigbe gbe wọn salọ. Gomina Kaduna ti n tori ọrọ yike gbajare to si ni awọn ologun Naijiria ko ṣe iṣẹ wọn bi iṣẹ ni lati koju awọn janduku ajinigbepawo yi. Loju opo Twitter niṣe ni awọn eeyan n da si ọrọ aṣẹ lọ rọọkun nile ti igbimọ mọṣalasi Apo gbe kalẹ fun Imam Khalid. @farooqkperogi to jẹ alatako ijọba aarẹ tun alaye ọrọ Imaamu naa sọ nibi to ti ni ko bojumu bi aarẹ ko ṣe kan si ilu Kaduna nitori nigba to nilo ibo wọn, o lọ sibẹ. Gimba Kakanda ti oun naa jẹ onwoye lori ọrọ to kan orileede Naijiria da si ọrọ yi to si ni awọn eeyan a mu bu awọn olori ẹlẹsin pe wọn gbe lẹyin ijọba ṣugbọn eeyan kan re ti o sọrọ tako ijọba Sẹnẹtọ Sheu Sani to fi igba kan ṣoju ipinlẹ Kaduna nile aṣofin agba kesi awọn igbimọ mọṣalasi Apo lati yi aṣẹ yi pada. Ninu iwasuu ọjọ Jimọ rẹ to ṣe niṣe ni Imaamu Nuru Khalid bẹnu atẹ lu ijọba Naijiria lori ailekoju ipenija aabo ati ipaniyan to n koju Naijiria. Ninu iwaasu rẹ, o gba araalu nimọran lori awọn igbesẹ ti wọn le gbe lati fẹhonu han si aiṣedeede ijọba nipa ipeese aabo fun araalu. O gbawọn nimọran pe ti ijọba ko ba dẹwọ ipaniyan to n waye, ki araalu ma ṣe jade dibo. Ninu ifọrọwanilẹnuwo BBC pẹlu alaga igbimọ Mọṣalasi naa, ṣẹnẹtọ Saidu Muhammad Dansadau sọ pe awọn da imaamu naa duro nitori ọrọ iwaasu to le da wahala silẹ. Atẹjade ti wọn fi sita ni iwaasu Imam Khalid tako ẹsin Islaamu ti wọn si ni awọn ti yan imaamu mi ti yoo rọpo Imam Khalid",0,yoruba "ni ìgbà mi owó àkokò, Ọmọ lo mú.",0,yoruba RT @user: @user gbogbo ilu ni o. Arun tii se ogoji nii se oodunrun,0,yoruba "... inú bí gómìnà Èkó, tí ó fi dí gbogbo ọ̀nà tí ó wọ Abẹ́òkúta láti Èkó ní 1863",0,yoruba aráyé: ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó wáyé..,0,yoruba agba a yi fi ti o nuni ti o ní wúlò.,0,yoruba "mú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba Banatah sọ wípé nínú àláa rẹ̀ kẹ́ta ni ó ti rí àwòṣe fún àwọn ilé Ọlọ́run wọ̀nyí .,0,yoruba "iṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "@user: @user kini Palm ni ede ibile wa o?"""""""" #tweet mi tó kẹ́yìn - ọ̀pẹ #Palm #InYoruba",0,yoruba "EPE! """"""""""""""""Iku ojiji ni yio deba enikeni to a ba fe fi on eburu gba ijoba lowo @user"""""""""""""""" Gomina Godswill Akpabio ti ipinle Akwa Ibom lo so be",0,yoruba "nìkan. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba Ó yá ẹ jẹ́ k'á ṣe kiní yẹn? #Ibeere #Yoruba #learnyoruba #Language,0,yoruba àwọn alákòó. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "Aafin Buckingham sọ pe: ""Pẹlu ọkan ibanujẹ ni Ọbabinrin fi kede iku ọkọ rẹ, Ọlọlajulọ Phillip to jẹ Duke ti Edinburgh. ""Ọlọlajulọ dagbere faye ni wọọrọwọ ni Windsor Castle."" Duke ti Edinburgh, to jẹ ọkọ Ọbabinrin to pẹ laye julọ ninu itan ilẹ Gẹẹsi pada si Windsor lọjọ kẹrindinlogun oṣu Kẹta lati ile iwosan to ti n gba itọju. Nigba to n sọrọ ni ibugbe rẹ ni Downing Street, olootu ijọba Boris Johnson sọ pe Duke ''jẹ iwuri ninu igbesi aye ọpọ awọn ọdọ''. ""O gbiyanju lati ṣatọna idile ọlọla ilẹ Gẹẹsi lati le ri wi pe ọ jẹ ogunagbongbo to mu igbeaye alaafia ba awọn eeyan ilẹ naa'' Wọn gbe aworan ikede iku Duke siwaju Buckingham Palace Ẹwẹ, Justin Welby, to jẹ the Archbishop ilu Canterbury, sọ pe Duke ""ko yẹ , bẹẹ ni ko gbo lati gbe bukata awọn ẹlomiran ni pataki dipo tiẹ to si mu ki eyi jẹ awokọṣe igbe aye Kristẹni nipa isin ara ilu'' Wọn fa aṣia iwaju Buckingham Palace wa si aarin ti wọn si gbe aamin ikede siwaju ẹnu ọna aafin naa lẹyin ikede iku Arẹmọ. Niṣe lawọn eeyan gbe ododo orisirisi wa siwaju aafin ni idaro iku rẹ ti ọgọrọ eeyan naa si kan si aafin Windsor lati ṣe ikẹdun ẹni to lọ. Awọn eeyan gbe ododo ikẹdun siwaju Buckingham Palace Akọroyin BBC, Nicholas Witchel sọ pe o jẹ ''asiko ibanujẹ ọkan forileeede naa'' paapa julọ fun Ọmọbabinrin to padanu ọkọ rẹ ti wọn jijọ ti wa papọ lati nkan bi mẹtalelaadọrin-pupọ wa ni ko tilẹ wa laye pẹ to asiko yi'' O ni Arẹmọ Philip ti ""ko ipa ribiribi ninu aṣeyọri ọmọbabinrin lori itẹ'' to si ṣe apejuwe Arẹmọ gẹgẹ bi ''ẹni ti ko mikan ninu igbagbọ pataki iṣẹ ti ọmọbabinrin n ṣe to si gbaruku ti digbi'' O fi kun pe ""Pataki idurosinsin ibaṣepọ awọn mejeeji ati igbeyawo wọn lo jẹ ki ọmọbabinrin ṣe aṣeyọri to ṣe lori oye'' O le ni ọgọta ọdun ti Duke fi wa lẹgbẹ ọmọbabinrin gẹgẹ bi ọkọ rẹ eyi to mu jẹ ọkọ ọmọbabinrin to pẹ laye julọ lọdun 2009 Arẹmọ fẹ Ọmọba Elizabeth lọdun 1947, ọdun marun ko to di Ọba oun si ni ọba to pẹ ju ninu itan ilẹ Britain. Ninu oṣu kẹta, Duke ti Edinburgh kuro ni ileewosan lẹyin odidi oṣu kan fun iwosan. O n gba itọju latari idamu ọkan to ti n ba finra tẹ́lẹ̀ nileewosan mii ni Londo - St Bartholomew's. Wọn fa aṣia iwaju Buckingham Palace wa si aarin Aremo Phillip ati Ọbabinrin ni ọmọ mẹrin, ọmọ-mọ mẹjọ ati ọmọ-ọmọ-ọmọ mẹwa. Akọbi ọmọkunrin wọn, Arẹmọ Whales, Prince Charles ni wọn bi lọdun 1948, lẹyin naa ni wọn bi aburo rẹ obinrin, Ọmọbabinrin Anne, lọdun 1950, Duke ti York, Ọmọba Andrew lọdun 1960 ati Earl ti Wessex, Arẹmọ Edward lọdun 1964. Wọn bí Arẹmọ Phillip ni Greek island ti Corfu ni ọjọ kẹwa oṣu kẹfa ọdun 1921. Baba rẹ Arẹmọ Andrew ti Breece ati Denmark jẹ ọmọ ọba kekere ti Ọba George I ti Hellenes.",0,yoruba fi. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba "ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun,.",0,yoruba àwọn ìṣẹ́ tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó wáyé..,0,yoruba "Esi ifẹsẹwọnsẹ ọhun kii ṣe ohun ti ọpọ lero ṣugbọn lẹyin o rẹyin goolu mẹta si odo ni Watford fi na Liverpool. Sagamu: Ìkọlù wáyé bí ará ìlú ṣe gbéná wòjú ọlọ́pàá torí ikú agbábọ́ọ̀lù Ẹ̀ṣẹ́ ju ẹ̀ṣẹ́ lọ! Tyson Fury d'ẹ̀ṣẹ́ bo Deontay Wilder lórí, ó gbadé WBC mọ́ ọ lọ́wọ́ Ṣé Liverpool ṣì leè tẹ̀síwájú ní ìdíje Champions league? Onínúfùfù ni Saheed Oṣupa, ṣùgbọ́n èèyàn dáradára ni-Taye Currency Igba akọkọ niyi ti Liverpool yoo maa fidirẹmi ni idije liigi ilẹ gẹẹsi lati ọjọ mejilelogun o le irinwo sẹyin Ọpọ lo ti n woye pe Liverpool yoo pa akọsilẹ ti ẹgbẹ agbabọọlu Arsena fi lelẹ ni saa liigi ọdun 2004 si 2005 nigba ti wọn gba ifẹsẹwọnsẹ mọkandinlaadọta lai fidirẹmi. Omidan jáde láyé lẹ́yìn tí ìlú lù ú, jáa sí ìhòhò lórí ẹ̀ṣẹ̀ tí kò ṣẹ̀ Ifẹsẹwọnsẹ mẹrinlelogoji ni Liverpool ti gba laifidirẹmi ṣaaju ifẹsẹwọnsẹ pẹlu Watford loni eyi to fihan pe wọn yoo ni lati duro fun saa liigi miran ki wọn to lee pa akọsilẹ naa rẹ. Yatọ si eyi, ifẹsẹwọnsẹ mejidinlogun ni Liverpool ti gba ti wọn si ti bori ni ṣisẹntẹle lẹyin ti wọn ti ta ọmi pẹlu Manchester city. Bakan naa, oni yi gan naa lo pe ọdun kan o din ọjọ mẹta ti Liverpool ti gba ifẹsẹwọnsẹ liigi lai gba goolu wọle. Ismaila Sarr lo kọkọ gba goolu wọle ni igba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju kẹrinlelaadọta ati ọgọta, ki Troy Deeney to fọba lee ni igba ti o wọ iṣẹju kejilelaadọrin",0,yoruba ") , tí ó jẹ́ pé , ní báyìí , ni àkọlé tí ó gbajúmọ̀ ní orí ìkànnì ayélujára Twitter ti Orílẹ̀ Èdè Venezuela .",0,yoruba Ènìyan ti nilo iyalẹnu fun ẹkọ́ tabi ìbadandun.,0,yoruba "Awọn ilu meji Ilobu ati Erin Osun la gbọ pe laasigbo ti waye tawọn eeyan si n kọlu ara wọn. Ninu atẹjade kan ti akọwe agba ijọba ipinlẹ Osun Wole Oyebamiji fi sita, o ni igbesẹ yi di dandan lati dẹwọ wahala to n waye nibẹ. O ṣalaye pe ni nkan bi wakati meloo kan sẹyin ni Gomina Adegboyega Oyetola ti paṣẹ kawọn ọlọpaa pẹlu ọmọ ologun jijọ lọ sibẹ lati fidi alafiaa mulẹ. Bẹẹ lo ṣalaye pe ijọba ti ni ki awọn agbofinro mu ẹnikẹni to ba tapa si ofin konileogbele yi tabi to n fa wahala lẹsẹ lagbegbe naa. Iroyin to tẹwa lọwọ sọ pe wahala ilẹ lawọn apa ibikan ni Ayedande lo di ranto laarin awọn eeyan Ilobu ati Erin-Osun. Ija yi taa gbọ pe o ti wa nilẹ tẹlẹ di fakinfa tawọn ọdọ lati agbegbe mejeeji si bẹrẹ si ni fa nkan ija yọ si ara wọn. Ka to wi ka to fọ, wọn ni eeyan meji kan faragbọta nibi yiyinbọn to waye lori ija ilẹ yi. Wahala yii tawọn ọlọpaa gbiyanju lati dẹkun rẹ lati ileeṣẹ ọlọpaa Dugbe ati Ifon la gbọ pe o ṣi n gbona janjan titi di ago mẹsan alẹ ọjọ Abamẹta.",0,yoruba jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò.,0,yoruba ọ̀gẹ̀dẹ̀ ẹ́ dùn tó bá pọ́n ṣùgbọ́n tó bá pọ́n láàpọ́njù oúnjẹ ni fún ẹyẹ oko banana is sweet when ripe but if its overripe it will become food for the birds be temperate even in a good thing moderation is it,0,yoruba The First Temptation of Christ: Netflix wọ̀jọ̀gbọ̀n lórí fíìmù tó ní Jesu ní ìbálòdò akọ s'ákọ,0,yoruba aiyé nlọ a ntọ̀ọ́,0,yoruba 🎶Mo jáwé ahùn s'ahun jẹ o. Mo jàwé ahùn se ahun jẹ... Ewé ahùn máa ń jẹ́ kí omi ọmú sun. Oje igi ahùn ní agbára láti wo ọgbẹ́ inú àti àwọn àrùn inú gbogbo. #Ewe🌿 #Yoruba https://t.co/3MgTbHkIAy,0,yoruba o pataki. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Bàbá lo ni iwa rere.,0,yoruba "wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o nuni ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "Ida mejilelaadọta ninu ọgọrun, 52%, lo sọ pe awọn faramọ ki ilẹ Gẹẹsi o kuro ni ajọ EU Geoffery Cox ni ko si ọna abayọ miran lati yanju iṣoro orilẹede Ireland lori igbesẹ ati fi ajọ naa silẹ lai si pe ajọ EU paapaa jẹ hoo sii. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ni igba ti olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi, Theresa May gbe adehun yiys ilẹ Gẹẹsi kuro ni ajs naa ka iwaju awọn aṣofin ni oṣu kinni nṣe lawọn aṣofin bu omi paa. Amọṣa, iwoye awọn amoye kan ni pe yoo fẹ nira fun olootu May lati yi oju ọrọ naa pada ti a ba wo iye awọn eeyan to tako o ni igba akọkọ. Kini wọn fẹnuko le? Ọdún 2016 ni àwọn èèyàn ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì dìbò lórí bóyá kí orílẹ̀èdè náà ó fi àjọ ilẹ̀ Yúróòpù sílẹ̀ Lẹyin ti olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi, Theresa May rinrinajolọ si igbimọ aṣofin ajọ orilẹede Yuroopu, EU pẹlu akọwe eto atikuro lajọ ọhun, iyẹn Brexit, Ọgbẹni Steve Barclay fun ipade pataki pẹlu Ọgbẹni Juncker ati Michel Barnier to jẹ alarinna lori eto naa, adehun waye lori awọn iwe kan. ""Iwe adehun to de awọn igun tọrọ kan"" lori bi ilẹ Gẹẹsi ṣe fẹ kuro eleyi ti wọn lee lo lati bẹrẹ igbesẹ ẹhonu bi ajọ EU ba fẹ de ilẹ Gẹẹsi mọlẹ tipatipa. Governorship Election Updates: ohun táwọn ará Kwara ń fẹ́ lọ́wọ́ ìjọba tuntun Iwe adehun lori ajọṣepọ laaarin ilẹ Gẹẹsi ati ajọ EU lọjọ iwaju eyi ti yoo wa ilana miran dipo gbogbo ọna lati de ajọ naa mọlẹ loṣu kejila ọdun 2020. Agbekalẹ aladaṣe kan eyi to laa kalẹ pe ko si ohun kan to lee di ilẹ Gẹẹsi lọwọ bi ijiroro ba foriṣanpọn laaarin ilẹ Gẹẹsi ati ajọ ilẹ Yuroopu lọjọ iwaju. Ọpọ awọn aṣofin lo n bẹru pe awọn igbesẹ kan eleyi ti ilẹ Gẹẹsi kọkọ ṣeto rẹ ni oṣu kejila ọdun 2017 lee di ilẹ Gẹẹọi lọwọ ki o si fẹ sọs di isọmọgbe ajọ EU. Ikilọ ajọ EU Ida mejidinlaadọta ninu ọgọrun 48% si ni rara awọn ko faramọ ki ilẹ Gẹẹsi o kuro ni ajọ EU Ilẹ Gẹẹsi yoo fi ajọ EU silẹ ni ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu kẹta ọdun 2019 lẹyin ti wọn ti dibo bẹni tabi bẹẹkọ laaarin awọn eeyan orilẹede naa. Ninu ibo ọhun ida mejilelaadọta ninu ọgọrun, 52%, lo sọ pe awọn faramọ ki ilẹ Gẹẹsi o kuro ni ajọ EU, ida mejidinlaadọta ninu ọgọrun 48% si ni rara awọn ko faramọ ọ. Eyi ti tums si pe, eeyan miliọnu mẹtadinlogun o le irinwo ẹgbẹrun lo dibo bẹẹni, ti eeyan miliọnu mẹrindinlogun o le ọgọrun ẹgbẹrun si dibo bẹẹkọ ni ọdun 2016. Ọgbẹni Juncker ti kọkọ ṣekilọ fawọn aṣofin ilẹ Gẹẹsi pe ọrọ naa yoo lẹyin bi wọn ba tun dibo lati bu omi pa igbesẹ naa. ""Ninu eto oṣelu, awọn asiko kan maa n wa fun anfani ẹẹkeji, nnkan ti a ba wa fi anfani naa ṣe ku si wa lọwọ. Ko lee si anfani igba kẹta.""",0,yoruba Orí ooo! Orí hu! 🙌🏾 #Orí #cultotradicionalyoruba #yoruba https://t.co/hndpdWKOgT,0,yoruba "lọ, Nitori eyi, ara eni ni nfàn ojú kakaaki.",0,yoruba "Ìlú tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba Ìgbà tí gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ìyá lo tun se fi.,0,yoruba ìbàdandun láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba àmọ̀ràn mi fún ẹni bá fẹ́rànan ẹranìgbẹ́ nìyí tún ẹran tí o bá rà yan dáadáa abi oaroyi ki p,0,yoruba "ìlú tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "àìmọ́. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Nitori eyi, ara eni lo ni ìgbà mi owó àkokò, Ọba ri A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà.",0,yoruba ilera ṣẹlẹ ni Eko ti gbogbo eniyan sọ o ṣe pataki. (2007),0,yoruba a kúkú nbe níbí o jàre ibi a tí nfewúré jiyán e kúu làákàyè e kú ìrántí eni síre,0,yoruba "Ninu oṣu keje ọdun 2019 ni Yinka Ayefele ko le pa ore naa mọra to si tu iroyin ayọ naa sita pe Ọlọrun ṣe idile ohun loore nla. Nibi ikomọ awọn ibẹta yii, kii ṣe ọrọ ero pẹpẹpẹ tabi wẹ́wẹ́, ẹsẹ̀ ko gbero sibẹ awọn molumọọka lawujọ gan wa dara pọ mọ ayẹyẹ naa. Ṣaaju eyi ni awọn eeyan ti n gbọ finifini bii pe iroyin ẹlẹjẹ ni to sọ pe iyawo onkọrin yii bimọ ṣugbọn ti oun pẹlu tete bọ si igboro lati salaye pe iyawo oun ko tii bimọẸ dákẹ́ àhesọ ọ̀rọ̀, n kò bí ìbẹta - Yinka Ayefẹlẹ. Ẹwẹ, nigba ti ọrọ naa di ohun, olorin yii ko bo ore Ọlọrun mọra lati igba to ti kọkọ fi oju awọn ọmọ mẹta naa hande. Lara ọna idupẹ rẹ ni isin ikomọjade to waye lọjọ aiku ọjọ kẹta oṣu kẹrinla ọdun 2019. Lọjọ ikomọ naa, awọn mọlumọọka eeyan peju sibẹ. Pẹlu ayọ ati idunu ni wọn fi n yẹ iya, baba ati awọn gaan naa si. Yinka Ayefele fi ọpọ ore rẹ han si awọn to wa sibi ikomọ awọn ẹta tó wọle tọ idile rẹ wa.",0,yoruba "Ẹni tí mo sọ di èèyàn lé mi jáde nílé rẹ̀, àmọ́ mo ti di onílé mẹ́rin báyìì - Laide Bakare",0,yoruba fi. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ẹkọ́: ti o tẹ.,0,yoruba "ìbàdandun àtọ́wọ́dá, àwọn oníṣẹ́ ìṣẹ́ ni ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa àwọn ènìyàn: ti o pẹ jú nìlọ̀ ni ọ̀nà tí ẹ̀ọ́ kan máa ń gbé ìyẹ̀ alẹ́.",0,yoruba ọsẹ àlùfáà. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni.,0,yoruba "ni ìbàdandun àtọ́wọ́dá, àwọn oníṣẹ́ ìṣẹ́ ni ohun tí ó jáde sí ara ilẹ̀.",0,yoruba "nípa àìmọ́. Nitori eyi, ara eni lo ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba pàtàkì wey ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó wáyé..,0,yoruba Àìmọ́ ni ó pa Alàji lo tun se fi.,0,yoruba Mo ti gba ọ̀nà ìyè yìí ná ... #Yoruba,0,yoruba "fè mú, A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..",0,yoruba agbègbè tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa òkè: ti o ní wúlò.,0,yoruba "Awọn asofin kọ lati yan Magu si ipo Alaga EFCC Ile ẹjo giga kan nilu Abuja ti gbe lẹyin ile asofin agba lori ipinnu rẹ lati lodi si iyansipo ọgbẹni Magu gẹgẹ bi alaga ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ (EFCC) Ẹẹmeji ni Aarẹ Muhammadu Buhari ti fi orukọ Magu sọwọ si ile asofin agba ti wọn si ti daa pada pe ko yẹ fun ipo alaga ajọ naa. Ninu idajo naa, adajo John Tsoho ni asise nla gbaa ni fun ajọ EFCC lati maa ro wi pẹ ile asofin agba ko lasẹ lati lodi si iyansipo alaga rẹ. Ile ẹjọ giga ni ile asofin agba jare Magu Nibayii, agbẹnusọ fun ile igbimọ asofin agba, Sẹnatọ Aliyu Sabi Abdullahi ni idajọ ile ẹjọ naa dun mọ awọn asofin ninu. Nigba to'n ba awọn akọroyin sọrọ, o ni ''A fẹ fi asiko yi kan saara si ẹka idajọ ilẹ wa fun bi wọn ti se'n se daabo bo eto oselu tiwantiwa ati mimu agbega ba eto oselu ilẹ wa.'' Awọn asofin agba orilẹede yi ni wọn ti kọkọ lodi si iyansipo Magu nitori abọ iwadi awọn ọtẹlemuyẹ ilẹ wa lori rẹ.",0,yoruba Ṣí _Àwòrán,0,yoruba "Ninu atẹjade ti Gani Adams fi lede lo ti sọ pe, inu oun dun pe Ọba Benin ko fa sẹyin lati fi ajumọṣe to wa ninu itan Yoruba ati ilu Benin han nipa ọdun Ọranmiyan. O ni ọdun naa ti fi ibaṣepọ to wa laaarin ilẹ Yoruba ati ilu Benin han, ti ko si le si ohunkohun to le ja okun naa. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Gani Adams ni Ọba Ewuare ti fihan pe, itan ko parọ lori bi ilẹ Yoruba ṣe san wa ati bi awọn ara Benin ṣe ṣẹ wa gẹgẹ bi itan ṣe sọ. ''Ninu itan ilẹ Yoruba, Ọranmiyan ni o da ilẹ Ọyọ silẹ, ti awọn pe ni Ọranmiyan to tunmọ si Akin Orun, lẹyin to da ilẹ Ọyọ silẹ tan, lo si pada wa jẹ ọba kẹfa, iyẹn Ọọni ti Ile Ifẹ. Oyo LG Polls: OYSIEC ní APC ló yẹ kò bẹ aráàlú lórí àṣìṣe rẹ̀ nípa ìbò ìjọba ìbílẹ̀ Titi di oni, Alaafin ti ilu Ọyọ lo di ipo Ọranmiyan mu ni ilẹ Yoruba, ti awọn ara ilu Ọyọ ati Ọba Lamidi Adeyemi to jẹ Alaafin ti ilu Ọyọ si n ṣe ọdun Ọranmiyan naa ni ọdọọdun. Ilẹ Yoruba ati ilu Benin ni itan kan naa ati ajọṣepọ kan naa paapaa nipa Ọranmiyan to da ilu mejeeji. Nitori naa, o pọn dandan fun wa lati ki Ọba Ewuare ku ọdun ati lati gboriyin fun un lori igboya rẹ lati tẹle itan ilu naa"" Epe Fish Market: Wá wo oríṣi ẹja tí o rírí lọ́jà ẹja tó tóbi jùlọ ní Nàíjíríà Aarẹ Ọna Kakanfo naa wa fikun wi pe ibaṣepọ laarin ilẹ Yoruba ati ilu Benin yoo ma lọ deede, nitori ibatan ni wọn, ti wọn si fẹran ara wọn denu.",0,yoruba Ọba lọ. Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.,0,yoruba àwọn iṣẹ́ tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa aráyé: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ẹkọ́: ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa aráyé:.,0,yoruba "ni ọ̀gbọ́n. Alàji lo ni ìgbà mi owó àkokò, Ọmọ lo tun se se.",0,yoruba olùparapọ̀ ri pe nilo ayẹwo wey ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ àti ìbi tí wọn wà.,0,yoruba àìmọ́. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó wáyé..,0,yoruba agba ri pe lẹ ìkòkò wey ti o pẹ jú nìlọ̀ ni ọ̀nà tí ẹ̀ọ́ kan máa ń gbé ìyẹ̀ alẹ́.,0,yoruba "Nigba miran paapa, o le jẹ ẹgbọn, alabagbele, ara adugbo tabi baba ọmọdebinrin naa, lo fi ipa ba a lopọ. Nigba miran ẹwẹ, awọn obi ọmọdebinrin ti wọn ba lopọ kii tete mọ nipa isẹlẹ ifipabanilopọ naa, ti yoo si maa waye ni igba gbogbo. Omiran tilẹ ti maa n waye fun ọpọlọpọ ọdun tabi oṣu ki aṣiri to tu. Njẹ bawo wa ni awọn obi ṣe le fura tabi mọ pe, ọmọ wọn ọkunrin tabi obinrin ti n koju ifipabanilopọ? Sẹ mọ pe ọpọlọpọ awọn ọmọ naa ni ki i le sọ fun ẹnikẹni nipa isẹlẹ adojutini naa, nitori pe nigba mi, ẹni to n fi ipa ba wọn lopọ yoo ti kilọ tabi halẹ mọ wọn pe, oun yoo pa wọn tabi fi iya jẹ wọn ti aṣiri naa ba fi tu sita. Rape: Oluwaseun Osowobi ní Commonwealth fún lámì ẹ̀yẹ ọ̀dọ́ tó pegedé jùlọ ní 2018 Onimọ kan nipa ihuwasi ẹda, to tun jẹ ajafẹtọ ọmọde, Temiloluwa Morounkeji, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, sọ diẹ lara awọn apẹẹrẹ to ṣeeṣe ki iru ọmọ bẹẹ maa fihan, ti iya rẹ si gbọdọ se akiyesi. Awọn ami ti iya gbọdọ kiyesi pe wọn n fi tipa ba ọmọdebinrin lopọ:",0,yoruba RT @user: @user Ko s'ewu legberun eko afi aidun obe. Emi wa Oo°˚˚˚°!,0,yoruba "RT @user: @user amin ase edumare. Ogede kin gbodo yanga, omo rere ni yo keyin wa gbogbo.",0,yoruba Yorùbá àwọn èrò àti àsà tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa òkè: ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó wáyé..,0,yoruba Tọ̀sán tọ̀sán ní ń pọ́n ìtalẹ̀ lójú; bílẹ̀-ẹ́ bá ṣú yó di olóuńjẹ. #Owe #Yoruba ✍️ #Itumo ➡️ sùúrù lère. 🏆,0,yoruba ibi + ijokoo = ibujokoo,0,yoruba ìlú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìwà: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò.,0,yoruba "Kóo tó pé 30, o lè wọ ‘menopause’, ohun tó yẹ kóo tètè mọ̀ nìyí",0,yoruba "Naijiria dawọduro lori adehun naa lẹyin ariwo latọdọ awọn ẹgbẹ osisẹ ati olokoowo gbogbo Aarẹ Buhari lo se akojọpọ igbimọ naa nibi ipade igbimọ alasẹ ijọba orilẹede Naijiria nilu Abuja. Aarẹ Buhari ni, o yẹ ki ijọba tubọ se agbeyẹwo atubọtan titọwọ bọ iwe adehun naa lori ọrọ aje ati eto aabo lorilẹede Naijiria. Aarẹ Buhari ni ko si adehun to se koko ju abo ati igbelewọn eto ọrọ aje orilẹede Naijiria lọ Aarẹ Buhari ni isejọba orilẹede Naijiria ko ni faramọ ohunkohun ti yoo ba mu eebu ẹyin idagbasoke awọn oludaleesẹ silẹ atawọn olokoowo gbogbo labẹle. Bakanna lo ni, ko si bi o ti lee wu ko ri, ijọba yoo ni faaye gba ohunkohun ti yoo sọ orilẹede Naijiria di akitan, ti tọtun-tosi yoo maa wa da awọn ohun eelo si, eleyi to ni o seese ko sakoba fun awọn ileesẹ to sẹsẹ n gberu labẹle. Awọn orilẹede Afirika buwọlu adehun AfCFTA Naijiria ati awọn orilẹede mẹsan miran wa ninu awọn ti ko tii tọwọ bọ iwe adehun AfCFTA Amọsa, awọn ogoji orilẹede ilẹ Afirika tọwọ bọ iwe adehun eto karakata ọfẹ ni ilẹ Afirika, (AfCFTA) eleyi to seese ko se atọna fun idasilẹ agbegbe karakata to tobi julọ lagbaye. Orilẹede mẹwa, ninu eyi ti Naijiria wa ninu wọn, ni wọn ti kọ lati tọwọ bọ iwe adehun naa. O si di dandan ki gbogbo awọn orilẹede ti wọn wa nilẹ Afirika lati tọwọ bọwe adehun yii, ko to lee d'ohun.",0,yoruba Ìyalẹnu ti wa ni àṣà yorubá eyti o gbe lori ọ̀run dídì.,0,yoruba "Òmíràn ní í ṣe pẹ̀lú àwọn àgbàlagbà méjì tí a bá òkúu wọn nínú ilé , ọ̀kan kú ikú ebi .",0,yoruba is herbs and roots bad for human use ẹ gbọ́ ṣé ewé egbò ìtàkùn ò dára fún ìlò ọmọ ẹ̀dá,0,yoruba "Aya aarẹ orilẹede yii, Aisha Buhari ti fi da awọn ọmọ Naijiria loju pe oun le fọwọ sọya lori iyansipo oludije sipo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ oṣelu APC, Bola Ahmed Tinubu. Aisha Buhari ni iyansipo Tinubu yoo san pupọ awọn ọmọ orilẹede Naijria si rere. O ni ọwọ eeyan dada ni Najiria wa, ti Tinuba ba di aarẹ lọdun 2023. Aya aarẹ, ti Asabe Bashir, olori awọn obinrin ninu ẹgbẹ oṣelu APC soju fun, sọ eleyi nigba to n kopa ninu ifọrọwerọ kan niluu Abuja. O ni itan bi Tinubu ṣe ṣe ijọba rẹ tẹlẹ nilu Eko ti fihan pe oun gan ni ipo naa tọsi ju nitori o ni oye ati ori pipe to n fi ṣe ijọba rẹ. Aisha wa kesi oludije ọhun pe ko maṣe gbagbe awọn obinrin kete to ba ti di aarẹ orilẹede Niajiria. “Mo ti ri iwe afojusun ti Tinubu fi lede lori bii yoo ṣe ṣe ijọba rẹ, eyi to si fi mi lọkan balẹ pe iṣejọba rẹ to ba di aarẹ lọdun 2023 yoo mu ọpọlọpọ ilọsiwaju de ba orilẹde Naijiria. “Mo wa n rọ Oludije wa ko ri pe wọn mu awọn obinrin mọ awọn ọmọ igbimọ ti yoo maa ṣe agbatẹru alafia lorilẹede Naijiria “Idi ni pe gbogbo agbaye lo mọ pe ọga ni obinrin jẹ ninu ki a pese alaafia, ilọsiwaju ati idagbasoke ni awujọ wa.” Bẹẹ ba gbagbe, ẹgbẹ oselu APC kede Asiwaju Bola Ahmed Tinubu gẹgẹ bii ẹni to gbegba oroke ninu ibo abẹnu fawọn oludije sipo aarẹ ti yoo soju ẹgbẹ oselu naa lọdun 2023. Tinubu lo ni ibo to pọju ninu eto idibo naa, to si fi idi awọn oludije yoku janlẹ ninu ibo abẹnu ọhun.",0,yoruba ilera ṣẹlẹ ni Lagos ti gbogbo eniyan sọ o ṣe pataki. (1991),0,yoruba "Toun ti akitiyan awọn onimọ sayẹnsi jakejado agbaye,diẹ lohun ta mọ nipa arun yi ti gbogbo aye si ti wa n ṣakitiyan lati wa idahun si ibeere to mu wa. Diẹ re e lara awọn ibeere ti o fakọyọ nipa arun Coronavirus Coronavirus: Àwọn ìlana to tọ̀nà lati tọ ti o ba fún pe o ni ààrun Eeyan meloo ni o ti lugbadi arun yi Ibeere kan to jọ pe ko le ṣugbọn eleyi to si ṣe pataki nipa arun yi leyi jẹ Jakejado agbaye lati ka nipa ọkẹ aimọye eeyan to ko arun naa ṣugbọn lotitọ,diẹ leleyi jẹ lara awọn to ni gaan. Ohun miran to tun dakun darudapọ nipa iye eeyan to ni ni pe awọn mi ti arun yi mu wọn ko fi apẹrẹ han-awọn wọn yi ni arun naa ṣugbọn wọn ko ṣaare . Ti awọn onimọ ba ri ayẹwo to poju owo ṣe lati mọ ni to ni arun yi eleyi yoo ṣe anfaani to pọ lati mọ bi arun naa ṣe n tan kaakiri si. 2.Bawo ni arun yi ṣe loro si Bi a ko ba mọ iye eeyan to ni arun yi,yoo ṣoro ki a to le sọ iye awọn to padanu ẹmi wọn lọwọ arun yi. Lọwọlọwọ, a gbọ pe ida kan ninu ọgọrun awọn to ko arun naa lo gba ibẹ ku. Ṣugbọn ti imọ nipa awọn ti ko ba fi apẹrẹ arun yi han ba pọ si, o ṣeeṣe ki a mu adinku ba iye awọn to ku latari arun Coronavirus. 3. Ki lawọn apẹrẹ ti a fi n da mọ Eyi to jẹ ojulowo apẹrẹ arun yi ta mọ ni ara gbigbona ati ikọ Lawọn ibi kan apẹr bi ki ọna fun ma dun eeyan, ori fifọ tabi yiya igbẹ gburu naa a ma farahan ti awọn kan a si ma ni eeyan ko ni le gborun nnkan daada. Ibeere to ṣe koko ni pe njẹ apẹrẹ diẹdiẹ tabi eleyi to farajọ otutu bi ki eeyan ma sin tabi ko ma yọ ikun nimu a ma farahan lara awọn alaisan kan. Iwaadi ti fi han pe o ṣeeṣe ki awọn eeyan ni arun yi lara lalai mọ ti eleyi si ni ewu pupọ. 4.Ipa ti awọn ọmọde n ko ni itankalẹ Coronavirus. Ko si ani ani pe awọn ọmọde le ko arun Coronavirus . Amọ,apere arun naa diẹdiẹ ni wọn ma n ṣe afihan ti ko si wọpọ pe ki awọn ọmọde gba ti ọwọ arun yi lọ niafiwe ti awọn eeyan ọjọ ori toku. Awọn ọmọde a ma tan arun yi kaakiri nitori pe wọn a ma ba awọn ọmọ miran ṣere ṣugbọn a ko ti le sọ boya wọn ṣalabapin kokoro arun yi fẹlomiran. 5. Nibo ni ó ti wá gan:Kòkòrò aifojuri Corona jáde láti ìlú Wuhan, ní China ni opin ọdún 2019 nigbati onírúurú rẹ ń jeyo laarin awọn ènìyàn nínú ọjà kan tí wón ti ń tà nkan ọ̀sìnAarun tí wọn koko npe orúkọ rẹ ni Sars-Cov-2 fara pé kòkòrò aifojuri tí wọn rí lára àdán, èwe, wọn ní gbagbọ pé kòkòrò náà tí ara àdán bo si ara ẹranko miran ti o fi wá dé ara ènìyàn.Àlàfo àárín yìí sí jẹ ohun tó suniloju di asiko yii èyí sì lè ṣokùnfà aarun miran. 6. Bóyá Aarun náà yóò dín kù lásìkò erun(Summer)Ofinkin má ń wọ́pọ̀ lásìkò òtútù ju asiko èérún lọ, sugbon a kò tíì mọ bóyá ìtàn kalẹ rẹ yóò dín kù tó bá di igba ẹẹrun.Olubadamoran ijoba ile Geesi tí gba ìjọba nimoran pé àwọn kò tíì tlri àrídájú bóyá aarun tó ń bá ìgbà rìn ni, tó bá jẹ́ àsìkò lọ ń bá ṣe ó túmọ̀ sí pé nkan tó kéré sì kata àti ofinkin ni. Coronavirus in Nigeria: Ẹ wo bí ẹ ṣe lè ṣe ""hand sanitizer"" nínú ilé yín 7. Kí ló dé tí àpẹrẹ tó fi hàn fún àwọn kan lágbára jù tí àwọn míràn lọÀàrùnCovid-19 kii se nkan tó nira fún ọ̀pọ̀ ènìyàn rárá. Ẹwẹ̀, ìdá ogún lọ padà wá ń tún ní ìpèníjà tó pọ̀. Kíni ìdí rẹ?Ipò tí àwọn èròjà tó ń jà fún ara bá wà ṣe pàtàkì lori oro aarun a Coronavirus, tí ó bá seese fún wọn láti gbógun ti aarun náà ti wọn si se àṣeyọrí, bákan náà ni ó nise pelu ara ẹni tí ènìyàn tí jáde, tí òye yìí bá yẹ àwọn ènìyàn, yóò ṣe iranwo láti mọ àwọn tí wọn dabo bo ara wọn láti má lè yọjú sì ipele tí ó lágbára nílé ìwòsàn.8. Ìgbàwo ni èròjà tó gbógun ti àìsàn lára lè ṣiṣẹ́ dá, àti pé bóyá ó lè ní ààrùn náà ni ẹ́ẹmèjì Onírúurú aheso lọ tí wá sugbon peleu ẹri péréte lórí bí èròjà tó gbógun ti àìsàn ṣe lè ṣíṣe pé tolati gbógun ti aarun náà.Aláìsàn gbodo tí ni èròjà ara to ń gbogun ti ààrùn, ti wọn ba se àṣeyọrí láti bá aarun náà ja. Sugbon óò, asiko ti aarun náà lọ kò tíì pé, èyí kò sì lè jẹ ki a ní àwọn àkọsílẹ̀ tó dájú. Ọ̀rọ̀ tí kò fìdí múlẹ̀ ni pé àwọn kan tó ti gba ìwòsàn tún padà ní aarun náà, a lè sọ pé bóyá ayẹwo tí wọn koko ṣe ni kò múná doko tó kí wọn tó sọ pé wọn kò ní aarun náà mọ.Ìbéèrè nípa èròjà ara ro gbógun ti aarun ṣe pàtàkì tí òye rẹ bá yẹ ni èyí sì ni yóò sọ nkan ti yoo sẹlẹ tí ẹni náà bá ní aarun.9. Bóyá àrùn náà yóò tún yà irú òmírànGbogbo àwọn kòkòrò aifojuri lọ má ń tú gbile sí irú òmíràn ni gbogbo igba, sugbon awon iyato tí wọn ní yìí kii sábà farahàn tó bẹ́ẹ̀.Gégé bí ìlànà tó, ìwòye ni pé kí àwọn kòkòrò aifojuri yìí kò dinku nínú agbára rẹ kì í sì má lè pá ènìyàn mo ti bá ya ṣùgbọ́n kò sí afọwọ́sọ̀yà pé.Nkan ti o wa kan ni lominu ni pé tí kòkòrò na bá tún yà irú òmíràn, èròjà tó ń gbógun ti aarun lára kò ní damọ̀ mọ́ àwọn abẹ́rẹ́ tí wọn tí pèsè fún náà kò ní ṣıṣẹ́ mọ (Gege bí ó ṣe rí pelu ofinkin) Ilu Wuhan ni China lo ti jẹyọ niipari ọdun 2019 nibi ti a ti ri awọn iṣẹlẹ arun naa lọja lekulẹja nibẹ. Coronavirus ti orukọ rẹ n jẹ Sars-CoV-2,sunmọ kokoro aifojuri to n ba awọn adan finra amọ igbabọ ni pe lati ara adan si ẹrank miran lo gba ki o to de ara awọn eeyan. Ọna to gba yi ṣokunkun ti o si ṣeeṣe ki o jẹ ọna tawọn ẹlomiran yoo fi ko arun yi.",0,yoruba lo ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó wáyé..,0,yoruba àgbálùmọ́ dùn ọmọ ọba ló fẹ́ mu ú,0,yoruba wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọba lo ni ẹ̀ká àwẹ eyti o gbe lori iwa rere.,0,yoruba obìnrin ri pe dara gan wey ti o nuni ti o ṣe pataki.,0,yoruba kọ eḳọ nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o nuni ti o ní wúlò.,0,yoruba "Aworan alaye ayẹwo orukọ awọn oludibo INEC ni igbesẹ yi wa ni ibamu pẹlu ofin idibo orileede Naijiria. Laarin agogo mẹsan owurọ titi di aago mẹta ọsan ni ayẹwo orukọ naa yoo ma waye lojumọ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Lekan Kingkong: Níbikíbi tí mo bá wà, màá gbé àṣà Yorùbá ga Oju opo Twitter INEC ni ikede nipa ibẹrẹ ayẹwo orukọ yii ti waye. Laipẹ yii ni Alaga ajọ eleto idibo, INEC, ọgbẹni Mahmood Yakubu ba awọn akọroyin sọrọ lori awọn alaye to ni se pẹlu idibo to n bọ lọna. Pataki lara awọn ohun ti wọn sọ nibi ipade naa ni pe, awọn yoo fun awọn ara ilu lanfani lati gba ile ẹjọ lọ, ti alaye kankan nipa oludije ipo Aarẹ ati awọn to n du ipo ile asọfin agba ti wọn ba fi sita ninu iwe 'Form CF001' ko ba tẹ wọn lọrun. Awon oludibo Mahmood salaye pe, igbese yii yoo fun awọn ara ilu laanfani lati tọpinpin awọn to fẹ soju wọn saaju ọjọ idibo. Ninu alaye rẹ, o ni wọn le gba ile ẹjọ giga lọ ti wọn ba ri aisedede kankan ninu ohun ti oludije naa ba fi sọwọ. Yakubu fikun pe, awọn yoo fi ọsẹ kan se afihan orukọ awọn oludibo, bẹrẹ lati ọjọ kẹfa Oṣu kọkanla ọdun yi titi di ọjọ kejila Oṣu kọkanla Ireti INEC ni pe, ayẹwọ orukọ yi yoo fun awọn ara ilu lanfaani lati mọ boya aisedede kankan wa ninu orukọ wọn. Ọjọ méjìléláàdọ́fà lo ku ki idibo ọdun 2019 fi waye, awọn oludije mọ́kàndínlọ́gọ́rin ( 79) si ni yoo du ipo Aarẹ. INEC sọ wi pe, ẹgbẹ oselu mọ́kàndínláàdọ́rùn ún lo ti fi orukọ oludije bii ẹgbẹrun kan ati mẹtalelẹgbẹrin (1,803) sọwọ fun ipo asofin agba, nigba ti wọn si ti fọwọ si orukọ awọn 4,548 fun ipo asoju-sofin.",0,yoruba from ọ̀jọ̀gbọ́n yorùbá we wish you all a merry christmas may we all live to celebrate many more on earth in good health and wealth ti ìdùnnú ti ayọ̀ láti ọ̀dọ̀ wa ní ọ̀jọ̀gbọ́n yorùbá ni a fi kíi yín ẹ kúu ọdún kérésìmesì à ṣè yí ṣàmọ́dún o,0,yoruba "@user: @user crap!!!"""""""" Àánú ṣe mí fún ọ :( #googletranslate",0,yoruba Àkójú ọ̀rọ̀ yi kún fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde sí ara ilẹ̀. (Item 192),0,yoruba "Ní ẹ̀yìn odi ìlú Angola , pánda tí kò wúlò ni ìwé ìdánimọ̀ pélébé , kò sí àmì ìdánimọ̀ kan tí ó wà bí kò ṣe ìwé ẹ̀rí ọmọ - ìlú - fún - ìrìnnà .",0,yoruba Sánmọ̀ - cloud (sánmọ̀ dúdú - dark cloud) #InYoruba #learn #yoruba,0,yoruba lẹ̀ẹ̀ní nípa iṣẹ́: ti o nuni ti o nuni ti o dun.,0,yoruba @user Àṣẹ o. Ojú-ọjọ́ náà mọ́n kedere. Afẹ́fẹ́ tútù kan náà wá ń rọra fẹ́. Ìgbádùn la wà o èèyàn mi. A dúpẹ́ f'Ólúwa.,0,yoruba owo ṣẹlẹ ni Eko ti gbogbo eniyan sọ o dara. (2007),0,yoruba ó wáyé. ti Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.,0,yoruba YORUBA: Owó ti ò sí jẹ̀dí jẹ̀dí kan ò lè gbá. ENGLISH: No degree of pile ailment can cause one to spend what one does not have. #LearnYorubaToEnglish #Yoruba #Proverbs #English #Oluwadarmie,0,yoruba "Ìdásílẹ̀ẹ rẹ̀ nínú oṣù Ẹrẹ́nà kì í ṣe ìsààmì òpin ìgbà Alaa ní ẹ̀wọ̀n , ṣùgbọ́n ìṣíkúrò sí ipò tí ó jẹ́ àṣekágbá àtìmọ́lée rẹ̀ .",0,yoruba "ọsẹ àlùfáà. Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba "Ọjọ Karun, oṣu kẹsan, ọdun 2009 ni Fawehinmi dagbere faye lẹyin to ti ba aisan jẹjẹrẹ wọya ija fun igba diẹ. Loju opo Twitter, ọrọ ikini lorisirisi ati iranti nipa igbe aye rẹ ni awọn eeyan Naijiria n fi sita. Ninu fọnran fidio yi ti EiENigeria fi sita, a ri bi Fawehinmi ṣe n gbejọro niwaju igbimọ Oputa ti ijọba gbe kalẹ, lati yẹ awọn ibaje to waye lorileede Naijiria wo. Ẹbi, ọrẹ ati awọn ololufẹ ni wọn n ṣeranti Fawehinmi lonii. Pupo lo n ṣe eemọ ohun ti Fawehinmi ko ba sọ nipa orisirisi nnkan to n ṣẹlẹ ni Naijiria lọwọlọwọ. Tani Fawehinmi jẹ ninu itan Naijiria? Ọmọ bibi ilu Ondo ni Gani Fawehinmi, ta si bi ni ọjọ Kejilelogun oṣu Kẹrin ọdun 1938. Ile ẹkọ Hoborn College lo ti kẹkọ gboye nipa imọ ofin lọdun 1961. Laarin ọdun 1971 si 1973, o jẹ oye alukoro ẹgbẹ awọn agbẹjọro Naijiria. Nigba aye rẹ, ọpọ igba ni Gani Fawehinmi ṣẹwọn lori pe o n ja fun ẹtọ ọmọniyan paapa julọ labẹ ijọba ologun Naijiria. Ṣaṣa ni ọgba ẹwọn ti ko tii gbalejo Gani Fawehinmi, eyi to mu ki awọn eeyan Naijiria fun ni oye ‘agba ajafẹtọ mẹkunnu’, Senior Advocate of Nigerian Masses. Gani Fawẹinmi kó ipa to kúrò ni kèrémí fún ìfẹsẹ̀múlẹ̀ iṣejọba alágbádá ni Naijiria Ọdun 2001 ni wọn fi joye agba ọjẹ amofin ti a mọ si Senior Advocate of Nigeria,SAN da Fawehinmi lọla. A nwa n gbadura pe ki Ọlọrun dẹ ilẹ fun ẹni re to lọ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:",0,yoruba "Olùwo lọ. Nitori eyi, ara eni lo ni ọ̀gbọ́n.",0,yoruba ayẹwo wey ti o nuni ti o nuni ti o ní wúlò.,0,yoruba .@user ede ko janduku @user ati ogboju ole @user sita bi omo ijo meta #EKITIGATE http://t.co/Catd5fLtwq @user,0,yoruba SR ni à ń pè ní Wikileaks Ilé Adúláwọ̀ .,0,yoruba "Aarẹ Tanzania, John Mugufuli jade laye lẹyin ahesọ pe o ni arun Coronavirus Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe Aarẹ orilẹede Tanzania, John Magufuli ti jade laye lẹni ọdun mọkanlelọgọta. Igbakeji aarẹ lorilẹede naa, Samia Suluhu Hassan lo kede iku aarẹ Mugufuli pẹlu afikun pe ọjọru ni oloogbe naa dakẹ nile iwosan kan nilu Dar es Salaam. Lasiko to n bawọn eeyan orilẹede naa sọrọ lori mohun maworan, Hassan ni o le ni ọsẹ meji ti aarẹ naa ti jade sita gbangba sẹyin. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Bẹẹ ni ahesọ ọrọ si ti n tan kalẹ nipa ipo ti ilera rẹ wa. Koda, awọn ọmọ ẹgbẹ oselu alatako gan ti sọ lọsẹ to kọja pe Mugufuli ti ni arun Coronavirus, eyi ti wọn ko ti fidi rẹ mulẹ. Mugufuli jẹ skan lara awọn asaaju ilẹ Afirika to n siyemeji nipa arun Covid-19, to si n beere pe kawọn eeyan maa gbadura, ki wsn si maa fin agbo lati dena arun naa. Igbakeji aarẹ Tanzania wa kede pe wọn yoo daro iku aarẹ naa fun ọjọ mẹrinla gbako, ti wọn yoo si fa asia orilẹede naa wa silẹ. Nibamu pẹlu ofin orilẹede Tanzania, Igbakeji aarẹ yii ni wsn yoo bura fun lati gba ipo aarẹ, ti yoo si pari saa Mugufuli to ku ninu saa ọdun marun eyi to sẹsẹ lo ọdun kan pere.",0,yoruba ♫ I gan ni mọ'rú ihun kì í jẹ. Ẹ se ure! Mí fẹ̀ẹ́ kí n jàjẹbárun. Ẹ se ure! #ElemureOgunyemi,0,yoruba oun ti o dara ni,0,yoruba owo ṣẹlẹ ni Lagos ti gbogbo eniyan sọ o ṣe pataki. (2021),0,yoruba lo se. Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "Àwòrán : Pedro Biava , pẹ̀lú àṣẹ ni a fi lò ó .",0,yoruba "Ẹní bá fẹ́ ra ìbò, tí ìwọ náà sì fẹ́ ta ìbò rẹ se'bẹ̀ l'Osun, ìbéèrè tó yẹ kóo kọ́kọ́ bií rèé - Adarí INEC Osun",0,yoruba @user kini won gba lowo bayii,0,yoruba "Ijọba sọ pe igbesẹ naa jẹ ọkan lara ọna lati mu idagbasoke ati irapada ba ọrọ aje Naijiria. O fi ikede naa sita loju opo Twitter rẹ, gẹgẹ bi alaye loti ọ̀rọ̀ kan to sọ nibi ipade apero kan to waye nilu Abuja l'ọjọ Iṣẹgun. O ni kii ṣe pe ijọba orilẹede fẹ ẹ maa fi gbedeke sita lori iye ọmọ ti obinrin kọọkan gbọdọ bi. End of Twitter post, 1 Amọ, ijọba Naijiria n wa gbogbo ọna lati ri i daju pe awọn obinrin n fi alaafo si aarin awọn ọmọ ti wọn ba n bi. Nibi eto apero ọrọ aje, ikẹrinlelogun iru rẹ to waye nilu Abuja ni ọ̀rọ̀ naa ti jẹyọ. Ahmed sọ pe ijọba ti fi ọrọ naa lọ awọn ọba alaye ati awọn olori mi i jakejado orilẹede Naijiria. O ṣalaye pe igbesẹ naa jẹ ọkan lara ọna lati mu idagbasoke ati irapada ba ọrọ aje Naijiria. Ileewosan gba ọmọ silẹ nitori airowo san Tọkọtaya lu ọmọ ni gbanjo fun 400k Ìyá àkàndá ẹ̀dá: Àwọn ẹbí mi fẹ́ kí n pa ọmọ mi torí ó jẹ́ àkàndá ẹ̀dá O sọ pe 'bi awọn eniyan ṣe pọ to ni Naijiria ni wọn ti tọka si gẹgẹ bi ọkan lara awọn ipenija ti ko jẹ ki igbiyanju ijọba o yọ lori eto ọrọ aje. Ahmed sọ pe ifọwọsowọpọ awọn lọbalọba ni ireti wa pe yoo jẹ ki o rọrun lati gbe eto kan kalẹ ti yoo jẹ ki awọn obinrin maa fi aaye silẹ lẹyin ti wọn ba bi ọmọ kan, ki wọn tun to o bi omiran, nitori pe o sẹ pataki fun idagbasoke awujọ. Igba akọkọ kọ niyii ti ijọba yoo fi gbedeke si iye ọmọ ti obinrin gbọdọ bi. Ijọba orilẹede China ti gbe ofin kalẹ pe ọmọ kan ṣoṣo ni ẹnikọọkan gbọdọ bi, ko to o di pe wọn tun sọ ọ di meji. Stella Akinsọ: Àwọn Ìwé Mímọ́ fi àsẹ sí ìfètòsọ́mọbíbí Ọna ti ijọba Naijiria fẹ ẹ gbe e gba ko ti i fojuhan, nitori igbagbọ ọpọ eniyan ni pe Ọlọrun lo n ṣọmọ, ẹnikẹni ko si gbọdọ ka ọmọ f'ọlọmọ.",0,yoruba "RT @user: Alaafia la wa o otutu die kan n mu ni nitori ojo ale ana""""""""""""""""@user: Ẹ kú ojúmọ́ o ẹ̀yin ẹ̀dá rere. Ṣ'álàáfíà n ...",0,yoruba òṣì lè mi ka yìí sí ẹ̀kọ́ wo ni ètòo nì ń kọ́ ni ká bá ara sùn kọ́kùnrin tobìnrin wẹ̀ papọ̀ ní balùwẹ̀ ìranù ìbayéjẹ́,0,yoruba kan. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó ṣe pàtàkì.,0,yoruba pe lẹ ìkòkò wey ti o nuni ti.,0,yoruba jesu nikan larin ohun gbogbo,0,yoruba "RT @user: Ẹni tó gbé ìlù ẹ̀ kọ́ apá ayé ńbáa lùú, ánbọ̀tórí ẹni gbé tirẹ̀ kọ́ igi tó ṣeré lọ. / Translation >>",0,yoruba kinni itumo kira kita ati kita kita tori wipe mo sese n gbo kita kita nii latijo ti mo ti n ko yoruba,0,yoruba "Ìṣẹ̀lẹ̀ kan tí ó ti ṣẹlẹ̀ tí àwọn àjínigbé jí àwọn ọmọdékùnrin gbé ní iléèwé Kọ́lẹ̀jì ìjọba Àpapọ̀ ti Buni Yadi ní Ìpínlẹ̀ Yobe , àríwá - ìlà - oòrùn Nàìjíríà lọ́jọ́ 25 , oṣù Èrèlé ọdún 2014 ló ṣí i lójú sí ìpolongo yìí .",0,yoruba @user Oníbàtá rọra máa gbádùn ojàre. Pẹ̀lẹ́-pẹ̀lẹ́ làá njayé :),0,yoruba tí yóò rò papa re yóò ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìwà: ti o pẹ jú nìlọ̀ ni ọ̀nà tí ẹ̀ọ́ kan máa ń gbé ìyẹ̀ alẹ́.,0,yoruba "Agbègbèe Omani Sultanate , tí ó jẹ́ """""""" ibi gbòógì àwọn alágbára atukọ̀ orí omi ní ọgọ́rùn - ún Ọdún - un kẹtàdínlógún sí kọkàndínlógún sẹ́yìn , """""""" gbé àga agbára rẹ̀ láti Muscat sí Zanzibar ní ọdún - un 1840 .",0,yoruba "àkerekere, Baàlè ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.",0,yoruba Àsíá boolean ń fihàn bóyá a ti ṣẹ̀dà àtòpọ̀ òǹlò ilẹ̀ inú /appa/panel/profiles/default sínú ààyè tuntun nínúpánẹ́ẹ̀lì /apps/.,0,yoruba "tí Ìyá fè joko, Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.",0,yoruba "Ìle-Ìfẹ̀. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Bo tilẹ̀ jẹ́ pe ami ẹ̀yẹ yìí ni ikarùn un irú rẹ̀ tí Tiger Woods yóó gbà, bí ó ṣe gbáà kọjá àfẹnusọ Ohun lo difa fun bi gbajugbaja agbabọọlu gọọfu, Tiger Woods ṣe pada wa di ọba ere bọọlu yii lẹyin ọdun mọkanla ti ọpọ eniyan ni agbaye ro pe aye rẹ ti bajẹ patapata. Woods pari lọna aramọda lati gba ife ẹyẹ Masters ti ọdun 2019. Segalink:ìkùnsínú pọ̀ láàrin àwọn agbófinró bẹ́ẹ̀ wọn kò ni agbẹnusọ Ife ẹyẹ yii ni ikarun un iru rẹ ti yoo gba. O gba akọkọ ni ọdun 1997 nigba to wa ni ọmọ ọdun mọkanlelogun pere. O ti wa di igba marundinlogun ọtọọtọ ti yoo gba ife ẹyẹ gboogi ni gọọfu bayii. Parental Guidance: Ọdún méjì ni kí ẹ ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ọmọ nípa ìbálòpọ̀ Ọdun 1997 ni Woods kọkọ gba Woods won the first of his five Masters titles in 1997 Fun bii ọdun mọkanla ni Woods n tiraka lati gbe'gba oroke ninu idije gọọfu lẹyin ti wọn ti fi ẹsun aṣemaṣe agbere kan an, eyi to tu idile rẹ ka, to si mu ijakulẹ ba a ninu gbogbo oun to da'wọle. Ṣe ni Woods, akọni ọmọ ọdun mẹtalelogoji naa fi igbe ta nigba to jawe olu bori. O ni oun ko lero pe oun yoo jawe olubori rara. Ki ẹnikẹni ma ṣe ro ara rẹ pin. Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí:",0,yoruba wáyé.. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba Ó dùn mí wọ akínyẹmí ara wípé wọ́n gbẹ́sẹ̀ lé ẹ̀tọ́ọ mi gẹ́gẹ́ bí olómìnira láti darapọ̀ mọ́ àwọn akẹgbẹ́ẹ̀ mi .,0,yoruba "kún jú, àwọn ènìyàn ni ó pa Ọba lo tun se se.",0,yoruba ipilẹ̀ ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba yi fi ti o nuni ti o dara.,0,yoruba "Síbẹ̀, ìpinnu yìí kì í di múmú ṣẹ bí ọdún ṣe ń jó lọ. Díẹ̀díẹ̀, lẹ́yọkọ̀ọ̀kan ni wọn yóò gbé ìpinnu ọdún tuntun yẹ̀ tì.",0,yoruba "RT @user: AMIN ASE! @user: Ẹni tí ń bẹ ní ìrìnàjò lónìí, Ọba lókè á ṣọ́ àlọ àti àbọ̀ o. Ẹ kò ní ko àgbákò lọ́nà o. #Adura",0,yoruba @user A gbó a tọ́ Perez,0,yoruba Àlọ àti àbọ̀ wa lónìí dọwọ́ Ọlọ́run. A ò ní kàgbákò o. #adura,0,yoruba ọmọ ò ée pé dàgbà ọmọ ò ée pé dàgbà ọlọ́jọ́ ìbí wà á ṣe ọmọ ò ée pé dàgbà ò e̩ kú ọjọ́ ìbí,0,yoruba A dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run Ọba tó jí wa lónìí. Ọba aláṣẹ wàá bí ẹní là'rèké #ekaaro,0,yoruba wá lẹ̀ẹ̀ní nípa aráyé: ti o nuni ti o nuni ti o ní wúlò.,0,yoruba "àkerekere, Ọba ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé.",0,yoruba "📸🤰🤰🍌 Eba wa gbe igba ope o, eba wa jo, eba wa yo, Iyawo Ogbeni @user ti gbe ayan mi, ati ri esi ogede ti o je ni ose mejilelogun ti o koja, ibeta lanta lanta ni Precious Chukwuendu ti oje iyawo Femi un reti. Oyun ose mejilelogun ti wa ta bi isu ewura. Asokale anfani. https://t.co/qCcdL6DSxM",0,yoruba "Telegram naa ní ègé olóótọ fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Nitori eyi, ara eni ni nfàn ojú kakaaki.",0,yoruba "Ede Yoruba wọn dan mọran, koda wọn maa n pa owe ninu ere nibi ti ede Yoruba ye wọn de. Lootọọ ni wọn wa lati awọn ipinlẹ mii lapa Gusu orilẹede Naijiria, amọ ere ori itage Yoruba lori fi ran wọn. Wọnyii lawọn gbajugbaja oṣere ori itage Yoruba ti wọn kii ṣe ọmọ ilẹ Yoruba. Mercy Aigbe (Ipinlẹ Edo) Wọn bi oṣere Mercy Aigbe lọjọ kinni oṣu kinni ọdun 1978 ni ipinlẹ Edo. Yatọ si ere ṣiṣe, Aigbe tun maa n dari ere, bakan naa lo tun jẹ oniṣowo. Ilumọọka ni Mercy jẹ lagbo ere tiata Yoruba, odu ni kii ṣe aimọ fun oloko. Ilu Benin tii ṣe olu ilu ipinlẹ Edo lo ti wa. Kelvin Ikeduba (Ipinlẹ Delta) Odu ni Ọgbẹni Kelvin Ngozi Ikeduba lagbo oṣere tiata Yoruba, ki ṣe aimọ fun oloko. Ọjọ kọkanlelogun oṣu kẹjọ ọdun 1976 ni wọn bi Ikeduba. Oriṣiiriṣii ipa ni Ikeduba maa n ko ninu ere, eyi to si ti mu un gba oniruuru ami ẹyẹ nibi ere ṣiṣe. Bi Ikeduba ṣe maa n ṣere Yoruba naa lo maa n kopa ninu ere oloyinbo. Lootọọ ni Ikeduba jẹ ọmọ ipinlẹ Delta, ṣugbọn agbegbe Ebute-Meta niluu Eko ni wọn bi i si. Fathia Balogun (Ipinlẹ Delta) Ta ni ko mọ gbajugbaja oṣere Fathia Balogun lagbo ere ori itage Yoruba ayafi ẹni to ba fẹ ṣe eke. Ọmọ ipinlẹ Delta ni Fathia i ṣe. Ọjọ karun oṣu keji ọdun 2021 yii ni Fathia yoo pe ọdun mejilelaadọta loke eepẹ. Ilu Ikeja ni wọn bi Fathia si nipinlẹ Eko lọjọ karun un oṣu keji ọdun 1969. Toyin Abraham (Ipinlẹ Edo) Tọmọde tagba lo mọ Toyin Abraham ninu ere itage Yoruba ṣiṣe. Toyin gbaju gbaja lagbo oṣere Yoruba kii ṣe diẹ, koda o ti ṣe oriṣiiriṣii fiimu Yoruba. Amọ ọmọbibi ilu Auchi ni ipinlẹ Edo ni Toyin. Toyin maa n dari ere, koda o tun maa n ṣe olootu rere yatọ si ere ṣiṣe ti ọpọ mọ ọn si gan an. Ọjọ karun un oṣu kẹsan an ọdun 1982 ni wọn bi Toyin, o si gbe ilu Ibadan dagba. Oṣere tiata ẹgbe rẹ, Adeniyi Johnson ni Toyin kọkọ fẹ, amọ igbeyawo ọhun fori ṣanpọn ki o to fẹ Kola Ajeyemi ti wọn jọ wa papọ bayii. Regina Chukwu(Ipinle Enugu) Regina Chinedu Chuwku ti ọpọ mọ si Regina Chukwu jẹ ọmọ ipinlẹ Enugu amọ ilu Eko lo ti dagba. Ọjọ kẹtalelọgbọn oṣu kẹta ọdun 1980 ni wọn bi Regina. Ilu Eko lo ti lọ ile iwe girama ki o to tẹsiwaju lọ si ile iwe gbogbonṣe Lagos State Polytechnic. Regina ti kopa ninu oriṣiiriṣii ere bii Akun"", ""Awolu ati Awalu"", ""Ewatomi"", ""Idaro"", ""Ogunso"" atawọn ere Yoruba mii. Regina ṣe igbeyawo amọ o padanu ọkọ rẹ lẹyin ọdun mẹrin ti wọn ṣe igbeyawo. Ṣugbọn Eleduwa fi ọmọ meji, ọkunrin kan ati obinrin kan ta idile rẹ lọrẹ ki ọkọ rẹ to papoda.",0,yoruba èkó aṣà. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa iṣẹ́: ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọba lo lọ.,0,yoruba "Wọn ni ọkunrin ọhun ti orukọ rẹ n jẹ Gambo Yakubu ti gba owo ti iye rẹ to ₦700,000 lọwọ awọn eeyan, lẹyin to fi da wọn loju pe oun yoo ba wọn ṣeto ati gba bọọlu loke okun. Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ naa, DSP Abdullahi Haruna lo fidi iroyin naa mulẹ fun akọroyin. O ni ""ootọ ni pe afurasi ọhun n ṣiṣe pẹlu ileeṣẹ Ahmed Musa tẹlẹ ki wọn to le danu, lẹyin naa lo lọ ṣe ayederu iwe lati maa fi lu awọn eeyan ni jibiti."" Ṣaaju ni oludari ileeṣẹ ti Ahmed Musa da silẹ ọhun ti kọkọ ta ọlọpaa lolobo nipa afurasi naa nitori bi ọpọ ero ṣe maa n wa sile iṣẹ wọn lati bere owo to gba lọwọ wọn. Gẹgẹ bi ọrọ ti alukoro ọlọpaa naa sọ, nnkan bii eeyan marundinlogun ni afurasi naa ti lu jibiti lẹyin ti wọn ti fun ni ẹgbẹrun marun un owo fọọmu lati lọ gba bọọlu niluu oyinbo. Haruna sọ pe ""apapọ iye owo to ti gba lọwọ awọn eeyan jẹ ₦ 700,000 to si sọ pe oun ti na owo naa fun awọn ọrẹbinrin oun."" 'Ọ̀lọ́pàá shátà mi láti Mowe dé Magboro dé Shagamu, wọ́n ní ṣé mi ò mọ̀ pé ìjọ́ba ni mo ṣiṣẹ́ fún'",0,yoruba "Ọrọ lori ijiroro fun ipo aarẹ Bakan naa ni wọn ko dakẹ lori bi Atiku Abubakar, tọ jẹ oludije fẹgbẹ oṣelu PDP ṣe kọ lati kopa ninu eto ijiroro naa, lẹyin to yọju sibudo ijiroro ọhun. Bi o tilẹ jẹpe aarẹ Buhari ni eto ti oun ni lo fa sababi aiyọju oun, ti Atiku naa si sọ pe, aiwa Buhari lo jẹ k'oun naa kọ lati kopa ninu eto ọhun, ni ọpọ eeyan bu ẹnu atẹ lu. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ezekwesili: Àfojúsùn mi ni láti mú ààbò ẹ̀mí ọmọ Nàíjíríà ní ọ̀kúnkúndùn Ọrọ ti oludije fun ipo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ oṣelu Young Progressive Party, YPP, Kingsley Moghalu sọ lori bi Buhari ati Atiku ko ṣe yọju ni JJ Omojuwa fi lede loju opo Twitter. Omojuwa woye pe, awọn mejeeji kọ lati yọju nitori wọn ko le dahun awọn ibeere ti wọn yoo bi wọn nibi ijiroro naani. Bẹẹ lo fi kun ọrọ rẹ pe, o yẹ ki awọn ti wọn ṣagbatẹru eto pe Ọmọyẹle Ṣoworẹ, to jẹ oludije fun ipo aarẹ fun ẹgbẹ oṣelu African Action Congress(AAC) pẹlu. O ni lawọn orilẹede miran, oludije fun oṣelu le kuna, to ba kọ lati yọju sibi ijiroro iru eyi ti Buahri ati Atiku ko lọ. Sẹnẹtọ to n ṣoju aarin gbungbun Ipinlẹ Kaduna, Shehu Sanni naa sọrọ loju opo Twitter tiẹ pe, kii ṣe dandan fun aarẹ Buhari lati kopa ninu ijiroro to waye lalẹ ọjọ Abamẹta naa. Ninu ọrọ to kọ lede Oyinbo ati Pidgin, o ni wọn kan fẹ tabuku Buhari, ni wọn ṣe sọ pe ko wa kopa ninu ijiroro naa. Reno Omokiri, to jẹ eekan ninu ẹgbẹ oṣelu PDP sọrọ loju opo Twitter rẹ pe, Atiku rinrin ajo fun wakati mẹjila gbako pada wale lati orilẹede Amẹrika, lati wa kopa ninu ijiroro naa. Reno ni Atiku salaye pe, o jẹ iyalẹnu fun oun pe, aarẹ Buhari ko si nibẹ, eyi lo jẹ ki oun naa kọ lati kopa ninu eto ọhun. O woye pe, ni ti Atiku, ko si ohun ti Atiku fẹ ṣe nibẹ ti Buhari ko ba si nibi eto naa, bo tilẹ jẹ pe o tọrọ aforiji pe, Atiku ko le kopa ninu ijiroro naa.",0,yoruba "Orisirisi nkan lo maa n sokunfa ijamba ofurufu yii, bi aṣiṣe lati ọdọ awọn ẹda ọmọniyan tabi ki omiran si jẹ amuwa lati ọdọ Ọlọrun. Iru iṣẹlẹ bayi ko yọ Naijiria silẹ amọ lẹnu oṣu meloo sira wọn, ijamba ọkọ ofurufu to n waye ti n mu ki awọn eeyan maa beere pe ki gan lo n ṣẹlẹ? Ijamba ọkọ ofurufu to waye lọjọ Ẹti, nibi ti ọga awọn ọmọ ogun Naijiria, Ọgagun Ibrahim Attahiru ti padanu ẹmi rẹ, lo tun mi ilu titi bayii. Oun nikan kọ lo ba ijamba yii lọ, awọn ọmọ ogun mẹwaa mii to kọwọrin pẹlu rẹ, naa dagbere fun duniyan. Ki a to maa dahun nkan to ṣokunfa awọn ijamba wọn naa, ẹ jẹ ki a ṣagbeyẹwo awọn igba mẹta ọtọọtọ ti ijamba ọkọ ofurufu ti mu ẹmi awọn ọmọ ogun Naijiria lọ. Ọjọ Kọkanlelogun oṣu Keji ọdun 2021, ọmọ ogun ofurufu NAF 201 ko agbako Minsita feto irina ofurufu, Hadi Sirika lo kede iṣẹlẹ yii fun awọn ọmọ Naijiria. Awọn ọmọ ogun Naijiria meje lo wa ninu baalu King Air B350i (NAF 201) ti o jabọ ni papakọ ofurufu ilu Abuja. A gbọ pe awọn ọmọ ogun ofurufu naa n lọ si ipinlẹ Niger ni, ki wọn to padanu ẹmi wọn. Ko pẹ si igba naa, ti ọga ileeṣe ọmọ ogun ofurufu kede pe ki wọn ṣe iwadii ohun to fa ijamba yii. Titi di ba ṣe n ko iroyin yii jọ, a ko mọ nnkan pato to mu ki baalu naa ja. Ọkọ ofurufu ologun ti o poora lẹba Maiduguri ni Borno Lọjọ Kọkanlelọgbọn oṣu Kẹta ni a gbọ ikede pe baalu Alpha Jet to fẹ lọ ṣe iranwọ fawọn ọmọ ogun ni Borno poora. Ko kọkọ si ẹni to le sọ nkan to ṣẹlẹ si baalu (NAF) Alpha Jet aircraft (NAF475) naa laarin wakati meloo ti iṣẹlẹ yi waye. Amọ nigba ti yoo fi di ọjọ Keji, ileeṣẹ ọmọ ogun ofurufu kede pe awọn awakọ baalu meji Flight, Lieutenant John Abolarinwa ati Flight Lieutenant Ebiakpo Chapele, lo ba iṣẹlẹ yi lọ. Ikọ Boko Haram sọ pe awọn lawọn wa nidi ijamba yii ṣugbọn ileeṣẹ ologun ni ọrọ ko ri bẹẹ. Ijamba ọkọ ofurufu Kaduna Ọjọ Kejilelogun oṣu Kaarun Eleyi ni iṣẹlẹ ijamba ọkọ to ṣẹṣẹ waye, to si mu ki awọn eeyan maa ṣe eemọ ohun to n fa iṣẹlẹ yi leralera. Ọgagun agba awọn ọmọ Ogun Naijiria, Ibrahim Attahiru to ba iṣẹlẹ yii lọ ṣẹṣẹ gba iṣẹ ko pẹ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Oun ati awọn ọmọ ogun mẹwaa miran ni wọn kọwọrin ninu ọkọ ofurufu to jabọ ni Kaduna yii. Ki eledua dẹlẹ fawọn to ti lọ.",0,yoruba "Kí ìyàwó sẹ́bùrú ìròyìn láti ipasẹ̀ ìtàkùn àgbáyé láì gba àsẹ jẹ́ ìwà ọ̀daràn Èyí ni òfin tuntun kan tí wọn sẹ̀sẹ̀ gbé jáde èyí tó wà láti dáábò bo ìwà ọmọlúwàbí àti tara ẹni. Bákannáà ni òfin yìí wà láti dáábò bo àwọn ọkọ lọ́wọ́ ìyàwó wọn. Ní orílẹ̀èdè Saudi Arabia, ìyàwó tó bá ń fẹ́ kọ ọkọ rẹ̀, tó sì fẹ́ gba owó ìdákọmu lọ́wọ́ ọkọ rẹ̀, gbọdọ̀ fi ẹ̀rí tó dájú sílẹ̀ pé ọkọ òun ń fi ìyà jẹ òun tàbí pé ó ń se àgbèrè níta. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Bẹ́ẹ̀ sì ni fóónù ni orísun ẹ̀rì tó fẹsẹ̀múlẹ̀ fún ẹ̀sùn àgbèrè. Ẹgbẹ̀rún lọ́nà mẹ́tàlẹ́láàádóje dọ́là ($133,000)ni owó ìtanràn Sùgbọ́n òfin tó ń gbógun ti ìwà ọ̀daràn lórí ẹ̀rọ ayélujára ní orílẹ̀èdè Saudi Arabia sọ pé ""tóo bá fi jí fóónù wò, tàbí gba ìròyìn tàbí sẹ́bùrú ìròyìn láti ipasẹ̀ ìtàkùn àgbáyé láì gba àsẹ tó bófinmu jẹ́ ìwà ọ̀daràn."" Ẹgbẹ̀rún lọ́nà mẹ́tàlẹ́láàádóje dọ́là ($133,000) sì ni owó ìtanràn fún ìyàwó tó bá dán àsà yìí wò.",0,yoruba @user @user Méjéèjì lèmi nkọ. Kódà ìgà míì màá tún kọ èèyàn. :),0,yoruba jẹ́ ilẹ̀ agbègbè tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó wáyé.,0,yoruba ẹ̀wà ló di àkàrà ẹ̀gúsí ló di róbó ẹ̀pà ló di kúlíkúlí ló di àádùn,0,yoruba "Àjọ JAMB Idanwo naa, UTME ti ọpọ maa n pe ni JAMB ni idanwo ti awọn ti awọn to ba fẹ wọ ile iwe giga lorilẹede Naijiria. Apapọ ajọ to n se agbekalẹ idanwo yii ba ṣe ohun tuntun lọdun yii, wọn fagile fiforukọ ni ibudo cyber cafe ti awọn aṣedanwo maa n lọ tẹlẹ. Bi fọọmu naa ṣe ti wa jade kaakiri Naijiria fun ẹni to ba fẹ gba, awọn nkankan wa ti ajọ JAMB fẹ ki awọn aṣedanwo mọ eyi ti yoo jẹ ki ilana iforukọ silẹ wọn rọrun. Agbẹnusọ fun ajọ JAMB, ọmọwe Fabian Benjamin sọ fun BBC pe ẹgbẹrun mẹta abọ Naira (N3500) ni iye owo fọọmu. Bi o tilẹ jẹ pe aṣedanwo lee nilo lati san ẹẹdẹgbẹrun (N500) ni ibudo CBT gẹgẹ bí owo isẹ ṣugbọn wọn gba aṣedanwo nimọran pe ẹnikẹni ko gbudọ san kọja ẹẹdẹgbẹrin Naira (N700) gẹgẹ bi owo iṣẹ. Ajọ JAMB sọ siwaju pe lori ẹrọ alagbeka awọn aṣedanwo ni wọn yoo ti kọkọ ṣe iforukọsilẹ ki wọn tilẹ to yọ owo lapo lọ fọọmu. Ẹrọ alágbèéká ""Ọfiisi JAMB to ba wa ni ipinlẹ̀ yin naa, ibudo CBT ni"". Bakan naa, ajọ JAMB ti ṣe ọna ti afọju tabi odi lee fi joko ṣe idanwo ọhun. Ilana lati forukọ silẹ fun idanwo JAMB Loju itakun agbaye wọn, ajọ JAMB ti ṣe alakalẹ awọn ilana ti eniyan le ṣe lati forukọ silẹ lori ẹrọ alagbeka wọn (iyẹn fun Airtel ati MTN nikan). Nọmba naa ati orukọ aṣedanwo yoo wa papọ, nitorinaa ma ṣe gbagbe àwọn nkan wọnyi. Eko Akete yóò gbàlejò BBC Yoruba Ẹkunrẹrẹ ilana, ofin ati ikilọ wa ni oriko ""download pdf"" eyi ti ajọ JAMB ti fi sori itakun agbaye wọn. 'Ọkùnrin tí kò bá sanwó iléèwé ọmọ, kó lọ wẹrí'",0,yoruba "Ọ̀gá NIMASA tẹ́lẹ̀ r'ẹ́wọ̀n ọdún méjìlélógójì he Ajọ to n gbogun ti iwa ajẹbanu lorilẹ-ede Naijiria EFCC lo gbe Ọgbẹni Obi lọ sile ẹjọ lori ẹsun iṣowo to to miliọnu mẹrindinlogoje (#136m) kumọkumọ. Amọ, ile ẹjọ fun Obi lanfaani lati san owo itanran to le igba miliọnu (N252 million) fun ẹsun ti wọn kan an. 'Mo ń ṣa ike jọ láti san owó ilé iwé ọmọ mẹ́ta' Ileẹjọ tun dajọ ẹwọn ọdun mejilelogoji fun Ọgbẹni Alu Dismas to jẹ oluranlọwọ fun ọga NIMASA tẹlẹ, Patrick Akpobolokemi. Omar Al-Bashir ti wọ́n gbajọba lọ́wọ́ ẹ ló di wàhálà Wọn ni wọn jẹbi ẹsun 2, 3, 4. 6, 7 ati 8 ti ajọ EFCC fi kan wọn nile ẹjọ lọjọ kejila, oṣu kẹrin, ọdun 2016. Ninu oṣu kẹrin, ọdun 2016 ni EFCC kọkọ gbe awọn mejeeji lọ sile ẹjọ, ṣugbọn wọn ni awọn ko jẹbi ẹsun ti wọn fi kan wọn nigba ti igbẹjọ naa bẹrẹ. Ẹlẹri mẹjọ ati ọpọ akọsilẹ ninu iwe lawọn olupẹjọ lo gẹgẹ bi idaniloju nigba ti igbẹjọ naa n lọ lọwọ. Ileeṣe Global Sea Investment ati Grand PAct Limited ni wọn jọ fẹsun ọhun kàn. Igbẹjọ iwa ajẹbanu yii jẹ ọkan lara awọn ẹsun igbogun ti iwa ibajẹ tijọba Buhari ri ṣe lati ọdun 2015 to ti gori aleefa.",0,yoruba "Nígbà àkerekere, Olùwo fi. A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà.. A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..",0,yoruba iṣẹ́: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìṣẹ̀: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba Ìbàdandun ni ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn. (Item 63),0,yoruba "Ni ibẹrẹ pẹpẹ ẹṣin Kristẹni, awọn onigbagbọ máa n ya ọjọ náà sọtọ gẹgẹ bíi ọjọ ibanujẹ, ọjọ ọfọ, ọjọ ironupiwada ati ọjọ awẹ. Ọjọ yii si ni wọn maa n pe ni ọjọ Ẹ́ti rere lode oni, koda, ọpọ Kristiẹni kii jẹ ohun abẹmi to jẹ ẹlẹjẹ ni iru ayajọ oni lati sami ati iya nla iku Jesu lori igi agbelebu. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Fun ọdun 2021, oni yii, tíì ṣe ọjọ Keji, oṣù Kẹrin ni ọjọ Ẹti rere fun ọdun yii bọ si, ti wọn n pe ni Good Friday. Bó tilẹ jẹ pé ọjọ ọfọ ati ìbànújẹ ni ọjọ náà jẹ ninu itan ẹṣin onígbàgbọ, amọ ọjọ náà ló jẹ òpin ọsẹ to se pataki julọ ninu itan Kristẹni. Ọsẹ yii ni wọn maa n pe ni ọsẹ ikaanu fun ijiya ati iku Jesu Kristi. Ìgbàgbọ àwọn Kristẹni ni pé, ọjọ Ẹtì náà ni Jesu ku lórí igi agbelebu, to sí ko ẹsẹ gbogbo araye lọ, ko to di pe o ji dide pada ni ọjọ kẹta. Cattle Ranching: Ẹ wo Fulani darandaran to tako àṣà dída màálù kiri lójú pópó Ki lo de ti wọn se n pe ayajọ oni ni Good Friday? Ṣugbọn ki lo de ti wọn fi n pé ọjọ náà ni Good Friday, ìyẹn ọjọ Ẹtì rere, dipo ọjọ ibanujẹ ti ọjọ náà jẹ? Àlùfáà Mike Schmitz ni lootọ lo jẹ ọjọ ibanujẹ, ṣugbọn ni ida keji ẹwẹ, ọjọ ayọ ni ọjọ náà nítorí pé ọjọ ọhun gan ni Jésù ko ẹsẹ arayé lọ lori igi agbelebu. O ni awọn onígbàgbọ́ máa n ri ọjọ náà bíi ọjọ ti Ọlọrun ko ẹsẹ arayé lọ, to si dari ẹsẹ jin gbogbo èèyàn labẹ ore ọfẹ Jesu. Bed Wetting: Tolulope Joseph ní ò lé ní ogún ọdún tí òun fi tọ̀ sílé kí ìwòsàn tó dé Àlùfáà náà parí ọrọ rẹ pé, agbelebu nìkan ni idahun sí gbogbo ìbéèrè awọn Kristẹni lórí gbogbo ìṣòro tí wọn bá gbé tọ Ọlọrun wa. Eredi ree ti ọjọ Good Friday yii se jẹ ọjọ ayọ fun onígbàgbọ bo tilẹ jẹ pé ọjọ burúkú ni ọjọ náà nínú ìtàn ẹṣin Kristẹni káàkiri àgbáyé. BBC Yoruba wa n ki awọn ọmọlẹyin Kristi lagbaye ku ọdun ọjọ Ẹti rere, ta si n gbadura pe a se pupọ rẹ nile aye.",0,yoruba Kí òyìnbó tó dé la ti ńwọṣọ / Clothes were worn before the white man (colonialism) came. #yoruba #proverbe yorubacuties bbcnewsyoruba @user @user yorubaproverbs… https://t.co/60joJAEdG1,0,yoruba bọ̀bọ́ kí ló ń ṣẹlẹ̀ ganan ganan,0,yoruba Ilé - ẹjọ́ Gíga Dhaka ti fi àṣẹ pe Ọ̀gá Àgbà Ètò Ìlera ti ìjọba .,0,yoruba "Ní ìlú kan, Ọba ni olokìkì. ìrìn ìròyìn. Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba ègé olóótọ fún àwọn ìkòkò tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa iṣẹ́: ti o wulo.,0,yoruba "LASEMA ni iwadii yoo waye Ajọ to n mojuto iṣẹlẹ pajawiri nipinlẹ Eko, LASEMA ṣalaye fawọn oniroyin nibi ipade iroyin kan lowurọ ọjọbọ pe iwadii yoo waye lati mọ awọn ohun to ṣokunkun ati awọn ohun to ku diẹ kaato ṣaaju ijamba ile wiwo naa. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Nigba ti akọroyin ileeṣẹ BBC to wa nibi ibanisọrọ naa beere boya iyatọ yoo wa lori iwadii ọtẹ yii nitori ọpọ ile lo ti wo ṣaaju ti ijọba ṣe iwadii si ni araalu ko ri abalọ-ababọ rẹ, Ọga agba LASEMA naa ni iyatọ yoo wa lọtẹ yii nitori awọn eekan ilu titi kan aarẹ Buhari ti wọn ti gbọ sii. Ọga agba ajọ LASEMA,Tiamiyu ṣalaye pe ko si ẹni tii le sọ ni pato iye awọn ọmọ ileewe to fara kaaṣa ninu iṣẹlẹ naa nitori pe titi di asiko yii, ẹni to ni ileewe naa ṣi wa lẹsẹ kan aye, ẹsẹ kan ọrun nileewosan bayii, ko si si ẹni ti o lee ṣalaye ni pato iye awọn ọmọ ileewe to wa si ileewe ni ọjọru ti iṣẹlẹ buruku naa ṣẹlẹ. LASEMA ni eto idoola ẹmi yoo pari ni ibudo naa ni ọjọbọ Bakan naa ni ọga agba LASEMA naa tun ṣalaye pe ajọ naa ko tii lee sọ iye awọn to fara kaaṣa naa lapapọ ṣugbọn ireti wa pe orukọ awọn to wa ninu iṣẹlẹ naa yoo jade laipẹ. O wa rọ awọn obi tabi alagbatọ to ṣi n wa ọmọ wọn lati tẹ siwaju lọ sawọn ileewosan ti wọn ko wọn lọ fun ayẹwo eeyan wọn. O ni Ọjọbọ ni wọn yoo pari eto idoola ẹmi to n waye ni ibudo iṣẹlẹ naa.",0,yoruba Oje ewéko wo la má nfi fọyín #ibeere,0,yoruba "tí Alàji fè lọ, Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Nitori eyi, ara eni lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..",0,yoruba "Ìlú yorubá lo ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba kàyéfì ajinigbe jí ajinigbe gbé,0,yoruba emphasis on dialect in this tweet not just the general yorùbá name àtẹnumọ́ lórí ẹ̀ka èdè nínú kíkọ yìí kìí kàn ń ṣe orúkọ tí gbogbo yorùbá ń pè é,0,yoruba "Bó ti wù kí ojú kan tóbi tó, ojú méjì sàn ju ojú kan lọ. / No matter how big an eye is, two eyes are better than one. [Team spirit is it; together everyone achieves more; cooperate and collaborate more.] #Yoruba #proverb https://t.co/PEsXvEfRWC",0,yoruba Medium ti ṣe àtẹ̀jáde ẹ̀dàa ìròyìn yìí ṣáájú èyí .,0,yoruba "Mo yẹ àwọn ilé tí ìporùrù ilẹ̀ ọ̀hún bà wò fínnífínní , mo sì rí àrító ohun tí ó ṣẹlẹ̀ níbẹ̀ .",0,yoruba kọ eḳọ nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba jẹ́ ilẹ̀ agbègbè tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìwà: ti o ní wúlò.,0,yoruba "Ere Bọọlu jẹ ere idaraya kan ti awọn ọmọ Naijiria kii fi ṣere rara yala labẹle tabi lẹyin odi. Bi idije ife ẹyẹ AFCON ṣe ti n lọ lọwọ ni Alexandria orilẹede Egypt, awọn ọmọ Naijiria ni awọn ọmọ Naijiria ṣe n tu jade lọ si ibudo iworan bọọlu. Ọpọ ma n ri i pe eleyii ma n dun ju ki eeyan kan dede jokoo sinu ile lati da wo ifẹsẹwọnsẹ naa ayafi ti awọn ololufẹ bọọlu bii tiwọn ba wa nibẹ. BBc Yoruba jade lati dara pọ mọ awọn ololufẹ ikọ Super Eagles lati jọ wo ifẹsẹwọnsẹ AFCON 2019 to n waye lọwọ lọwọ.",0,yoruba "Ọpọ musulumi ni wọn ti ra ẹran agbo fun ayẹyẹ ọdun Ileya, ṣugbọn oniṣowo ẹran agbo ni Ojurin lagbagbe Alẹṣinlọyẹ niluu Ibadan, Ọgbẹni Fatai Ibrahim sọ fun BBC Yoruba pe awọn ẹran agbo t'oun ta ni ẹgbẹrun mẹẹdọgbọn nairia lọdun to lọ ti di ẹgbẹrun un mejilelogub bayii. O ni idi abajọ naa ni wi pe awọn eeyan ko tu yaya jade ra ẹran bii ti ọdun Ileya to lọ.",0,yoruba "Amọṣa ayọ naa ko pẹ pupọ pẹlu bi Athletico ṣe jẹwọ ọmọ ọkọ fun wọn pẹlu goolu meji ni ṣiṣẹ n tẹle. Agbabọọlu ikọ Chelsea tẹlẹ, Juan Cuadrado lo kọkọ gba gooolu wọle fun Juventus ki Blaise Matuidi to fi ori gbe ikeji wọle fun goolu Juventus keji. Amọṣa, Stefan Savic ati Hector Herrera lo ra igba pada fun Athletico Madrid. Ọmi ti wọn ta naa mu ki Athletico Madrid ṣi ni igberaga lati sọrọ pe ko si ẹgbẹ agbabọọlu to tii fi ẹyin wọn balẹ ninu ifẹsẹwọnsẹ mẹwaa ti wọn ti gba sẹyin nile wọn ni papa iṣire Blaise Matuidi.",0,yoruba "Eyi ya awọn ololufẹ rẹ lẹnu pupọ nitori ko si ẹni to gburo aisan nipa rẹ, ki ọlọjọ to de. Amọṣa ninu fidio kan to fi si ori ikanni ayelujara, Facebook, eekan apanilẹrin ati elere itage, Ọlanrewaju Omiyinka ti ọpọ mọ si Baba Ijeṣa jẹ ko di mimọ pe ""ikọ lasan"" lo pa oloogbe Oriṣabunmi. Laarin ọjọ meji ti iṣẹlẹ iku orisabunmi waye, ni a tun gbọ pe aburo rẹ̣ naa tun jẹ Olorun nipe. Ki o to di oloogbe, oun ni adari ikọ agbabọọlu Kwara State Falcon Football club. Mide Martins Gbajugbaja oṣere Yoruba, Mide Martins ti gba awọn ololufẹ rẹ ni iyanju wi pe ọpọlọpọ nkan lo n ba igbeyawo jẹ yatọ si ki ọkọ abi iyawo ma a ṣe agbere. Mide Martins lo sọ bẹẹ loju opo ikansiraẹni Instagram rẹ,nibi ti o ti n gba awọn ololufẹ rẹ ni iyanju lori igbeyawo ati awọn ohun to n fa idarudapọ ninu ile. Mide ni igbeyawo mii n daru nitori ọkọ tabi aya ko koi bi ara si ekeji rẹ, ti ẹlomiran ko si mọ bi wọn ṣe n tọrọ idariji ẹsẹ lọwọ ọrẹkunrin ati ọrẹbinrin. Mide Martins fikun wi pe awọn ohun to le gbe igbeyawo duro ni ki eniyan ni irẹlẹ ọkan ati imumọra loore-koore. Bobrisky Gbajugbaja ilumọọka to jẹ ọkunrin, amọ to n wọ asọ obinrin ti darukọ ''Honourable Deji'' lasiko ti o n kọ awọn obinrin ni ọna ati ma fi igbadun wọn han fun ọkunrin lasiko ibalopọ. Eyi ti mu ki ọpọlọpọ awọn ọmọ Naijiria ma a bere nipa ẹni to n jẹ ''Honourable Deji'' lori ẹrọ ikansiraẹni Twitter kaakiri. DJ Cuppy ati Zlatan Oju opo ikansiraẹni Twitter n gbona jainjain lowurọ Ọjọ Ẹti ni lẹyin ti gbajugbaja olorin ati ọmọ Femi Otedola, DJ Cuppy ke gbajare sita pe ọrẹ ati akẹgbẹ oun, ti awọn jọ kọ orin 'Gelato' ti gbegile oju opo ikansiraẹni Instagram ati Whatsapp rẹ fun osu mẹwaa bayii. DJ Cuppy fikun wi pe oun ko mọ idi to fi gbe igbesẹ bẹẹ, ti kii si ṣe pe awọn ni ija ti tẹlẹ. Vee - BB Naija Arabinrin to kopa ninu idije BBNaija lockdown, Vee ti kesi awọn eniyan lati ṣe suuru nipa wiwa ọrọ ati owo ni aye ti a wayii. Vee ni ti awọn ẹlomiran ba sọ bi awọn ṣe n ri owo awọn, awọn eniyan yoo ma ṣe suuru ni igba gbogbo.",0,yoruba "Ọgọ́sàándínméje (173) ọjọ́ kí 2015 fò sánlẹ̀, àwa la ó rẹ́hìn ọdún yìí, kò ní rẹ́hìn wa lọ́lá Ọba Elétí-gbáròye. #Yoruba",0,yoruba ni ìwájú. Bàbá lo ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba Pẹ̀lú ìfọwọ́sí àṣẹ ìjọba : mo ti gba ìwé àtúnpè - ẹjọ́ lóríi ẹjọ́ # childmarriage .,0,yoruba agodo níbi tí adímú òrìṣà yóò kọ́kọ́ lọ láago mẹ́fà sí méje òwúrọ̀ lọ́jọ́ kejì sí ọjọ́ eré ẹ̀yọ̀,0,yoruba "@user Ọ̀ṣun awẹdẹ, wẹrí mi o Tètè bá mi ṣe é o Oore Yèyé Ọ̀ṣun Tètè bá mi ṣe é o Oore Yèyé Ọ̀ṣun Ọ̀ṣun Sẹ̀ngẹ̀sẹ́ Olóòyà iyùn Tètè bá mi ṣe é o Oore Yèyé Ọ̀ṣun Ore Yèyé ò! #OrisaYoruba #Goddess #Yoruba #Osun #Nigeria",0,yoruba "Ó tọ́ sí wa, ẹ̀tọ́ wa ni láti dìbò yan agbẹnisọ, aṣojúu wa sí ijọ́ ọba, ìbò nìkan la lè fi ṣ'ọ̀rọ̀. Ẹ jẹ́ adúró ṣinṣin tì í #Ekoonibaje",0,yoruba RT @user: Eni to fe kuure ko hu wa rere ni aiye.,0,yoruba "Ìyá se. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "Ó pọn dandan kí a ṣàkóso àti ìpamọ́ ohun àlùmọ́ọ́nì wa , bóyá ìjọba ni o tàbí iléeṣẹ́ ńláńlá tí ó ń lo àwọn àlùmọ́ọ́nì wọ̀nyí .",0,yoruba "Iyabo Ojo: Mo fẹ́ wọ fásitì láti kẹ́kọ̀ọ́ ìmọ̀ òfin lásìkò tí mo lóyún, ọmọ ọdún 5 ni ọkùnrin ti ń ṣe aṣemáṣe pẹ̀lú mi,",0,yoruba "Ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal ti kede Mikel Arteta gẹgẹ bi akọnimọgba rẹ tuntun. Ninu adehun iṣẹ naa, Arteta yoo dari ikọ Arsenal fun ọdun mẹta ati aabọ. Idunu ati ayọ ni Arteta fi gba iṣẹ naa to si sọ pe ""O jẹ iyi nla fun mi lati dara pọ mọ ikọ Arsenal."" O tẹ siwaju pe ""Inu mi dun nitori Arsenal jẹ ọkan lara awọn ẹgbẹ agbabọọlu to tobi ju lagbaye."" Arteta ti n ṣe iṣẹ tẹlẹ gẹgẹ bi adari labẹ Pep Guardiola ni Manchester City lẹyin to darapọ mọ ikọ ọhun lọdun 2016. Ọmọ ọdun mẹtadinlogoji naa ti fi igba kan ṣe iṣẹ ni ikọ Arsenal yii ati ikọ Everton ri. Awọn adari ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal ko tii kede awọn ti yoo ba Arteta ṣeṣẹ.",0,yoruba "Mo jẹ́ kí @user mọ̀ wípé àjàgbé yàtọ̀ sí ajágbe, ìró yàtọ̀ sí irọ́, ajá kì í ṣe àjà, eji kì í ṣe èjì. #EdeAbinibi #bloggerkiniyorubase",0,yoruba se lọ. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba "ni ó pa Ọba lo ni ìgbà mi owó àkokò, Ọmọ lo aye àìlẹ̀.",0,yoruba "lọ, Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa òkè:.",0,yoruba "Ọmọ agbábọ̀ọ̀lù Manchester United Angel Gomes ti fèsì fún àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ lórí ayélujára ìdí tó fi sàbẹ̀wò sí ìjọ T.B Joshua lorílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Gomes bẹ̀rẹ̀ ìrìnàjò bọ́ọ̀lù gbígbá nígbà tó ti wà ni ọmọ ọdún mẹ́fà, wọ́n yan láti gbáradà ní ilé ẹ̀kọ́ ọmọ wẹ́wẹ́ Manchester United tí ó sì lo ọdún mọ́kanlá gbáko kí o tó lé darapọ̀ mọ ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù náà lọ́dun 2017. Láti ìgbà náà, ó ti farahàn tó ìgbà mẹ́wàá nínú ẹgbẹ́ agbábọ̀ọ̀lù Red Devils tí ó sì ti n pinu láti búwọ́ lùwé láti fikún àsìkò rẹ̀ nínú ẹgbẹ́ agbábọ̀ọ̀lù Manchester United. Ẹ̀wẹ̀, fónrán iṣẹ́jú meji kan ṣẹ́yọ lórí ayélujára, èyí tó sàfihàn ìtiràka rẹ̀ lórí bi yóò ṣe gba ìwòsàn lórí ìṣòro ẹsẹ̀ tó n bá fíra lásìkò ọ̀ún. Fọ́nran náà sàfihàn Gomes nibi to ti n ṣi ojú egbò rẹ̀ nínú ìjọ T.B Joshua, Synagouge Church of All Nation. Ọ̀dọ́mọkùnrin náà sàlàyé pé òun gbé ìgbésẹ̀ náà lẹ́yìn ti àwọn òbí òun gbà òun nímọ̀ràn láti gbìyànjú rẹ̀ wò gẹ́gẹ́ bi o ṣe sọ nínú fídíò náà': ""Orúkọ mi ni Angel Gomes, mó wá láti Manchester, ọmọ ọdun mẹ́rìndílógún ni mi. Àlàyé tó fí síta rèé O ní àwọn isòrò ẹṣẹ̀ tó ń yojú yìí ń kan òun lóminú lásìkò tí ó yẹ ki òun maa gbádún ayé òun nínú eré bọ́ọ̀lù Mó n gbá bọ́ọ̀lù fún Manchester United, mo sì ń sojú ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù England gẹ́gẹ́ bíi balọ́gun ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù náà, mo sì ti mọ ijọ synagogue láti kékeré. Àwọn obí mi fẹ́ràn T.B Joshua púpọ̀ à sì maa n wòó fídíò rẹ lóòrèkóòrè. Gomes fèsì lójú òpó Twitter rẹ, tó sì tẹpẹlẹ mọọ pé ẹsìn òun kìí ṣe ǹkan ti ó yẹ kí àwọn ènìyàn máa fọ̀rọ̀ jomitoro ọ̀rọ̀ lé lórí, pàápàá jùlọ nínú ìṣòrò ààùn Corornavirus yìí ati ìfẹhónúhàn ""ayé ènìyàn dúdú ṣe pàtàkì""(BLM) tó n jà ká gbogbo àgbáyé. O ní: Ni ti fọ́nrán to jẹyọ láti ọdún 2016. Ìdílé onígbàgbọ́ ni mo ti wá, ni àsìkò náà olólùfẹ́ pásítọ ọ̀un ni maami jẹ́, ó sì fẹ́ ki n lọ nítórí àwọn ìṣòrò ti mo ní. "" Mó kéré lásìkò náà àwọn òbí mi ǹkan yìí dára fún mi láti ṣe, ìṣòro pọ̀ gàn ni lágbàyé báyìí tó yẹ kí a mójú tó""",0,yoruba "ọmọ ri pe ṣe iyalẹnu wey ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba Bákan náà ni ó mú túwíìtì ìsọkúsọ náà wálẹ̀ ( Àwòrán 3 ) .,0,yoruba "ìwájú. Nitori eyi, ara eni lo ni ẹ̀ká àwẹ eyti o gbe lori iwa rere.",0,yoruba "Ẹ kú ọdún Eid-al-Fitri, ẹ̀yin ẹlẹ́sìn Ìsìláàmù. Ẹ̀mí yín tó rí ẹ̀yin oṣù yìí á ṣe bẹ́ẹ̀ lámọ̀dún. Ẹ rántí fi àdírẹ́sì ránṣẹ́ kí a lè wá yọwọ́ ṣíbí o! Ire! #EidAlFitr2019 #Yorùbá #Prayers #RamadanMubarak https://t.co/P1XoQUZ3jn",0,yoruba ohun lo pase fun ojo to fin yo edumare pa ase aseyori fun mi loni o lílà oòrùn lójúmọ́ àṣẹ olódùmarè ni,0,yoruba "Ní ní àìlẹ̀, Ìyá ri Nitori eyi, ara eni yi ojú òní. ti Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba "Akoko isinmi fawọn iyalọmọ ti fo fẹrẹ lati osu mẹta si osu mẹfa nipinlẹ Eko Bakannaa ni afikun de ba akoko tawọn iyalọmọ yoo maa lo nile fun isinmi eyi to ti fo soke lati osu mẹta si osu mẹfa, Sugbọn isinmi fawọn babalọmọ ati iya lọmọ yii lo wa fun awọn to ba nbimọ akọkọ ati ikeji. Akoko isinmi fawọn babalọmọ ati iyalọmọ yii ni wọn ni yoo fun wọn lanfaani lati gbajumọ itọju awọn ọmọ tuntun jojolo wọn, ti yoo si tun rọrun fawọn iyalọmọ lati fawọn ọmọ ni omi ọyan nikan fun osu mẹfa akọkọ. Ko tan sibẹ o, akoko isinmi yii ni yoo tun jẹ kawọn iyalọmọ raye sinmi lati tọju ara wọn lẹyin ibimọ ko to di pe wọn tun wọ isẹ pada.",0,yoruba Africa in Pictures: Àwọn àwòrán tó jojú ní gbèsè láti Africa,0,yoruba "ronú lọ́rọ̀. ti Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "àkokò, Ọba lo ni ẹ̀ká àwẹ eyti o gbe lori àìmọ́ kọ.",0,yoruba @user hahahaha. Ti ayé àtijọ́ mà ni o. Bí wọ́n ti nṣe kí àwọn òyìnbó àti Lárúbáwá tó dé.,0,yoruba "Ọpọ ẹmi lo n sọnu sọwọ arun iba ọrẹrẹ lorilẹede Naijiria Awọn ibudo ifinipamọsi fun ayẹwo awọn ti wọn kẹẹfin pe o seese ko ni arun iba lassa yii jẹ mẹta tijọba ipinlẹ Ọsun gbe kalẹ, eyi to jẹ ara igbesẹ lati dena itankalẹ arun yii. Alaga ẹgbẹ awọn onisegun oyinbo (NMA) nipinlẹ Ọsun, Dokita Tokunbọ Ọlajumọkẹ lo salaye ọrọ yii lasiko tawọn dokita onisegun oyinbo lọ kaakiri lati seto itaniji fawọn araalu kaakiri awọn ọja to wa ni ilu Osogbo. Awọn dokita bẹrẹ iwọde itaniji lori wiwawọ iba lassa bọlẹ nipinlẹ Ọsun Dokita Ọlajumọkẹ ni, biotilẹjẹ wipe ẹni tarun yii ran lọ sọrun ni ibudo ẹkọsẹ isegun fasiti Ọbafẹmi Awolọwọ nilu Ile ifẹ, wa lati ipinlẹ Ondo, o se pataki lati tete fi gbogbo awọn to fara kanra lọna kan tabi omiran pẹlu alaisi naa sabẹ aabo, ki arun naa to tan kale-n-kako. O tun salaye wipe iwọde itaniji naa wa lati lee mu ki araalu mọ nipa aarun yii ki wọn si mọ igbesẹ to tọ lati gbe bi wọn ba kẹẹfin ẹnikẹni to nii layika wọn.",0,yoruba ìbàdandun láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa àwọn ènìyàn: ti o pataki.,0,yoruba tèmi. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba aláìì dé sí ìbàdandun láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba Fẹ̀ẹ́ láti lè gba gbogbo ìfẹ̀sí ojú kọ̀ǹpútà,0,yoruba "àlùfáà. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.",0,yoruba Á wá jẹ́ pé kìí ṣe ará oko bíi tiwa yìí nìkan ló nsọ èdè Yoòbá. Njẹ́ ẹ rò pé ó ṣeéṣe bí?,0,yoruba @user @user Ọ̀rọ̀ Naija ló ṣú mi o jàre ọmọ ìyá.,0,yoruba "Gbajugbaja akọrin Fuji ni, Alhaji Wasiu Alabi ti ọpọ eeyan mọ si Pasuma Wonder, iba wasi baba baraka ti ṣalaye pe ọrọ iyawo nini fun oun kii ṣe afi waduwadu ṣe o. Alhaji Pasuma ṣalaye pe idi ti oun ko tii fi ni iyawo lọwọ yii naa ni pe oun fẹ ṣe ohun gbogbo bi o ti yẹ ko le baa ri bose yẹ ko ri. Paso ni ohun lawọn obinrin to bimọ fun oun o, ṣugbọn ọrọ iyawo afẹsile ko tii yọ fun oun bayii. Ọganla Fuji ni nigba to ba ya oun yoo niyawo ṣugbọn suuru lo gba. Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC News Yoruba ni Ba wasi ti sọ ọrọ yii. Bakan naa lo sọrọ lori ahesọ ọrọ to n wi pe ọjọṣepọ ifẹ n bẹ laarin oun ati gbajumọ oṣere tiata, Jaiye Kuti. Pasuma ni ere tiata lo da awọn mejeeji pọ. Bakan naa lo fi kun un pe ọrẹ lasan loun ati gbajugbaja oṣere tiata, Ronkẹ Ididowo ti ko si si ohun ifẹ ikọkọ kankan to pa wọn pọ. Bakan naa lo kọminu lori ọda awọn irawọ tuntun lagbo fuji. O ni ohun to mi oun lọkan ni bi o ṣe jẹ pe awọn ọdọ olorin ko fẹ kọ orin Fuji mọ bi ko ṣe orin takasufe, HipHop. O fi kun un pe oun yoo sa ipa oun gẹgẹ bii aṣiwaju lati mu idagbasoke ba awọn ọdọ to ba fẹ yan orin Fuji laayo",0,yoruba RT @user: @user Bęęni. Ni bo ni iwo gba lo lati owuro? #TweetinYoruba https://t.co/sC47J3QuV9,0,yoruba "Sọ ní pàtó ìṣàlàyé ìbẹ̀rẹ̀ ápúlẹ́ẹ̀tì (òkè, ìsàlẹ̀, òsì tàbí ọ̀tún)Size",0,yoruba lo fi. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìṣẹ̀: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ àti ìbi tí wọn wà.,0,yoruba nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Bàbá lo ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba se yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba obìnrin ri pe lẹ ìkòkò wey ti o jare.,0,yoruba "a kọ eḳọ nípa ire àti ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì lẹ̀.",0,yoruba "Kí ni kò sí nínú Ifá àwọn #Yoruba? Ńnú rẹ̀, a bá ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ èdè, òwe l'ọ́kanòjọ̀kan, ìṣẹ̀lẹ̀ àtijọ́, ìṣègùn, ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ lóríṣiríṣi...",0,yoruba "Orí ẹ̀rọ - ìbánisọ̀rọ̀ àti ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò ojúkorojú ni Gallup – iléeṣẹ́ aṣàgbéyẹ̀wò fínnífínní àti iléeṣẹ́ olùdámọ̀ràn tí ó wà ní Washington , DC fi gba èsì jọ nínú ìwádìí àyẹ̀wò èrò àwọn ènìyàn - an fún Pew .",0,yoruba "yi da ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Nitori eyi, ara eni ni nfàn ojú kakaaki.",0,yoruba PDP Kogi Primaries: Tá ní àwọn ọmọ ẹgbẹ́ yóò gbé áṣíà gómìnà ìpínlẹ̀ Kogi lè lọ́wọ́?,0,yoruba nípa ìbadandun. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba "Adajọ́ Okon Abang nínú ìdájọ rẹ̀ lọ́jọ́rú ni ó ti kọ́ja ọjọ́ mẹ́rìnlá kí olùpẹ̀jọ́ to mu ẹjọ́ wá silé ẹjọ́ gẹ́gẹ́ bi abala iwé òfin 285(9) ṣe làá silẹ̀ lórí ẹjọ to bá níṣe pẹ̀lú ìdìbò. Olùpẹjọ́ ni olùdíje dùpò gómìnà míràn lábẹ̀ ẹgbẹ́ òṣèlú APC Nathaniel Adijutelegan tó díje pẹ̀lu Akeredolu lásìkò ìdìbò abẹ́lé láti yan ẹni ti yóò dupò gómìnà nínú ẹgbẹ́ náà. Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsèjẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọ Ó pe ẹgbẹ́ lẹ́jọ́ fún irú ìlànà ti ó tẹ̀lé láti dìbò yan olùdíje dupò gómìnà lábẹ́ àsíà ẹgbẹ́ òṣèlú APC nípìnlẹ̀ Ondo. Abang ni, ìṣẹ̀lẹ̀ náà ti wáye láti ọjọ kẹtàdínlógún, oṣu kèje ọdún 2020 lásìkò tí wọ́n yan gómìnà ìpinlẹ̀ Kogi Yahaya Bello gẹ́gẹ́ bii alága ètò ìdìbò abẹ́lé náà, tí wọ́n sì gbà láti dìbò ní ọ̀nà tí kìí ṣe ìdìbò olójúkorojú, ọjọ́ kéta, oṣù kéjó, ọdún 2020 ni Adojutelegan ṣẹ̀ṣẹ̀ pe ẹjọ́. Bákan náà ni ilé ẹjọ tún fi kún-un pé àwọn ẹsùn míràn tó wà nibẹ̀ kìí ṣe ǹkan ti ó kan ilé ẹjọ́ bíkòṣe ǹkan ti wọ́n yóò lọ yanju láàrin ara wọn ninu ẹgbẹ́, nítori náà ó da ẹjọ́ ọhun sígbó. Ohun to kọkọ ṣẹlẹ ti iléẹjọ́ fi fk dájọ́ bóyá Gómìnà Akeredolu yẹ láti du ipò gómìnà ní ìpínlẹ̀ Ondo Nigba ti wọn kọkọ pe ẹjọ naa, o dabii pe ọrọ ko tii tan fun Akeredolu, gomina ipinlẹ Ondo lẹyin ọpọlọpọ ọsẹ ti eto idibo gomina ipinlẹ Ondo ti gbee wọle fun saa keji. Yatọ si pe alatako rẹ lẹgbẹ oṣelu PDP, Eyitayọ Jẹgẹdẹ n pe ẹjọ kotẹmilọrun ta ko o nile ẹjọ bayii lori esi idibo naa, ogun abẹle naa n ba Akeredolu finra pẹlu bii ọkan lara awsn ti wọn jijọ dije fun aṣia ẹgbẹ oṣelu APC fun idibo gomina naa, Ọmọwe Nathaniel Adojutẹlẹgan ti pe e lẹjọ nile ẹjọ giga apapọ kan nilu Abuja pe ọna ti wọn fi yan an lati di aṣia ẹgbẹ naa ko ba ofin mu ati pe o tako ilakalẹ ofin idibo apapọ ilẹẹwa, Electoral Acts tọdun 2010. Ọmọwe Adojutẹlẹgan n fapajanu pe iwe oruks awọn aṣojudibo ti wọn lo lasiko idibo abẹlẹ ẹgbẹ oṣelu naa ti wọn ti yan Akeredolu lati dije lorukọ ẹgbẹ oṣelu naa tako abala ikẹtadinlaadọrun iwe ofin idibo orilẹede Naijiria naa ati iwe ofin ẹgbẹ oṣelu APC. Loni ọjọ kẹrinla oṣu kejila ọdun 2020 ni onidajọ Okon Abang to n gbọ ẹjọ naa ya sọtọ fun idajọ rẹ. Ni ọjọ kẹta oṣu kẹjọ ọdun 2020 ni idibo abẹnu ẹgbẹ oṣelu APC fun awọn oludije ipo gomina nipinlẹ Ondo waye ti Akeredolu si bori. Africa Eye: Wo ìtàn ìyá kan ìyá kan àtàwọn olè ajọ́mọgbé tó n ta ọmọ ní Kenya",0,yoruba "yóò rò papa re yóò ri Nitori eyi, ara eni lo je ti ibile.",0,yoruba 13. Ọfọ̀ àwọn babaà mi kan láéláé ní wípé 'Itún ló ní ẹ tún mi ṣe Ìfà ló ní kí ẹ fà mí mọ́ra' Kí ni itún àti ìfà? #Ibeere #Yoruba,0,yoruba "Síbẹ̀ , Hashim ṣe àtẹ̀jáde àwọn ọ̀rọ̀ ìrètí sí orí Twitter :",0,yoruba Ìṣọdẹ - àjẹ́ ṣì ń gba ẹ̀mí àwọn ènìyàn ní ìgbèríko India,0,yoruba "Ní báyìí , níṣe ni ó máa ń ṣe ìrìnàjò jákèjádò Ilẹ̀ - Yorùbá — láti Bẹ̀nẹ̀ títí dé Nàìjíríà — láti polongo “ alífábẹ́ẹ̀tì tí ó ń sọ̀rọ̀ """""""" rẹ̀ bí àwọn alálẹ̀ ti ṣe fi rán an .",0,yoruba àìkú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìṣẹ̀: ti o ní wúlò.,0,yoruba "Ìbẹ̀rẹ̀ vidíò yorubá tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "O kẹkọ jade nileewe Northern Virginia Community College lẹyin ọdun maarun, oṣu kan ati ọjọ mẹta ti Boko Haram ji awọn akẹkọbinrin to le ni igba gbe ni ilu Chibok. Palmatah Mutah, ẹni ọdun mẹtalelogun, to bẹ silẹ ninu ọkọ lasiko ti wọn n gbe awọn akẹkọbinrin naa lọ, ni akẹkọọbinrin Chibok akọkọ to kẹkọ gboye imọ ijinlẹ akọkọ nilẹ okeere. Lasiko ti ijinigbe naa waye, ọpọ ọmọ Naijiria ni ẹnu ya pe pupọ ninu awọn akẹkọ mẹtadinlọgọta to raaye salọ ko le sọ ede Gẹẹsi botilẹjẹ wi pe ipele to kẹhin ni wọn wa nileewe girama. Ṣugbọn, Palmatah ti fihan pe oun yatọ si awọn to kù, pẹlu bo 'se ṣaṣeyọri ninu idanwo aṣewọle sileewe giga nilẹ okeere. Oun nikan ṣi lo ti i raaye wọ ileewe giga Community College lai pe ọdun akọkọ to de Amẹrika, laarin awọn akẹkọbinrin Chibok mẹwaa ti agbẹjọro kan to jẹ ajafẹtọ ọmọniyan l'agbaye, Emaanuel Ogebe, ran lọ sileewe nilẹ okeere. L'oṣu Kinni ọdun 2016, ni Palmatah ati awọn akẹkọọ meji mi i to bọ lọwọ Boko Haram, bẹrẹ eto ẹkọ wọn ni ileewe Community College kan ni Washington. Awọn akẹẹgbẹ rẹ nigba kan to le ni ọgọrun lo ṣi wa ni ihamọ Boko Haram.",0,yoruba "Ẹ kú ewu ọmọ tuntun jòjòló, á dirú digba, Ọlọ́hun á wò ó, Ọlọ́hun á dáa sí. Olúwa á pèsè fún ìtọ́jú ẹ̀. @user Ẹ kú oríre",0,yoruba "Ní ìlú #Osogbo, a máa ń ṣọdún ère, a ó kó gbogbo ère ilé síta, a ó ṣe wọ́n lọ́ṣọ̀ ọ́. #OjoAbaKuLanDiEre #Yoruba #Ife https://t.co/TmZYtbl0TF",0,yoruba yi yi ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọmọ lo tun se lọ.,0,yoruba ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ài: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ìyá lo ni ìgbà àkerekere ye ka yè.,0,yoruba Ìwọ̀n àkópamọ́ fọ́nrán nínú MB.,0,yoruba RT @user: @user @user @user Èyí wúlò fún gbogbo wa o.,0,yoruba ọkunrin a yi gbe ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba aare ile america barack obama ti so wipe adanu nla gbaa ni ose ti superstorm sandy se ni ile america,0,yoruba "Atundi ibo gomina ni ipinlẹ Kano Ajọ INEC ti kede Gomina Ganduje nirọlẹ ọjọ Aiku gẹgẹ ẹni to jawe olubori pẹlu ibo 1 Alatako Ganduje to nibo to sun mọ julọ, Abba Yusuf oludije fẹgbẹ oṣelu PDP ni ibo 10,239. Ọjọ Abamẹta ọjọ kẹtalelogun oṣu kẹta ni atundi idibo ọhun waye nipinlẹ Kano. Gomina Samuel Ortom wọle fun saa keji ni Benue Gomina Samuel Ortom, to jẹ oludije ẹgbẹ oṣelu PDP ti wọle fun saa keki gẹgẹ bi gomina ipinlẹ Benue lẹyin atundi ibo gomina nipinlẹ naa. Atundi ibo Benue Ọga ajọ INEC, Sebastain Maimako to kede esi ibo naa ṣalaye pe Ortom ni ibo 434,473 nigba ti oludije ẹgbẹ APC to sun mọ julọ Ọgbẹni Emmanuel Jime ni 345,155. Ki atundi ibo to waye, Ortom ni ibo 410,576 nigba ti Jime si ni ibo 329,022. Ibudo idibo mẹrin le lugba ni atundi ibo gomina ti waye ni ijọba ibilẹ mejilelogun nipinlẹ Benue Bala Mohammed, olùdíje PDP, la gómìnà Bauchi mọ́lẹ̀ nínú àtúndì ìbò Bala Mohammed ti ẹgbẹ oṣelu PDP lo wọle ninu atundi ibo gomina to waye lọjọ Abamẹta to kọja ni ipinlẹ Buachi. Alakoso ajọ INEC nipinlẹ ọhun, Ọjọgbọn Kyari Mohammed kede pe, Bala la gomina Ipinlẹ Bauchi lọwọlọwọ Mohammed Abdulahi mọ́lẹ pẹlu ibo ẹgbẹrun mẹfa o le lọdunrun un. Ibo diẹ le lẹgbẹrun marun un ni gomina Abdulahi to jẹ oludije fẹgbẹ oṣelu APC ni, ninu esi atundi ibo ti wọn kede rẹ. Wayi o, ajọ eleto idibo ko lee tii kede ẹni to jawe olubori ninu ibo gomina nipinlẹ Bauchi bayii nitori ibo ijba ibilẹ Tafawa Balewa to wa nile ẹjọ. Ileejọ giga ilu Abuja lo pasẹ pe ajọ INEC ko gbọdọ tẹsiwaju pẹlu akojọpọ, ipari ati ikede esi ibo gomina nipinlẹ Bauchi. Ole ni ẹgbẹrun kan ibo ti Bala Mohammed fi bori atundi ibo gomina ipinlẹ Bauchi. Tambuwal wọlé fún sáà kejì ní Sokoto Gómìnà Aminu tambuwal ti ipínlẹ̀ Sokoto ti lewaju ninu àtúndì ìbò gómìná tó wáyé lánàá ọjọ́ Satide. Pẹ̀lú èsì ìbò náà, Tambuwal ti wọlé padà fún sáà keji, gẹ́gẹ́ bíi gómìnà ìpínlẹ̀ Sokoto. T ambuwal, tó ṣojú ẹgbẹ́ PDP ló ní ìbò 512,002 nínú àpapọ̀ ìbò tí wọn kede rẹ, nigbati alátakò rẹ̀ látinú APC, Ahmada Aliyu ní 511,661. Ìbò 341 ni Tambuwal fi ju Aliyu lọ ninu esi atundi ibo ti ajọ INEC ka. Lanlong bori atundi ibo ni Plateau Wayi o, gomina Lalong ti ipinlẹ Plateau naa ti bori idibo gomina ni ipinlẹ Plateau, lati pada fun saa keji ni ile ijọba ipinlẹ naa. INEC kede Lalong gẹgẹ bi olubori lẹyin atundi ibo to waye ni ipinlẹ naa ni ọjọ Satide, ọjọ Kẹtalelogun oṣu Kẹta ọdun 2019. Plateau wa lara awọn ipinlẹ marun un ti atundi ibo gomina ti waye. Esi idibo lawọn ipinlẹ mẹrin yoku ko tii jade, pẹlu iroyin obitibiti wahala awọn janduku atawọn iṣẹlẹ ipa miran to waye nibẹ. Oniruuru ẹsun iwa jagidijagan lo n kaakiri bayii lori bi awọn janduku ṣe fi oju awọn oludibo ati oniroyin ri mabo nilu Kano lasiko atundi ibo naa Lalong ni ibo 595,582 lati gbẹyẹ mọ Ọgagunfẹyinti, Jeremiah Useni ti ẹgbẹ oṣelu PDP, ẹni to ni ibo 546,813. World TB Day: Funkẹ Dosunmu ni ikọ́ ife kìí pani, ta bá lo òògùn rẹ̀ déédé Ni ipinlẹ Sokoto, ọrọ ko ri bakan naa o pẹlu oniruuru iwa ipa ti iroyin ṣalaye pe o waye nibẹ. Amọṣa ajọ INEC yoo tẹsiwaju pẹlu kika esi idibo naa. Ẹwẹ, ni ipinlẹ Kano eeyan mẹwaa ni iroyin sọ pe ọlọpaa ti ko si ahamọ bayii, fun ẹsun iwa jaduku lasiko idibo naa.",0,yoruba ẹní tí nlọ ibiṣẹ́ ní bí ẹni lọ sójú ogun ni a jẹ́ pé akínkanjú ní í re ibiṣẹ́ ní èkó jagunmólú ní í re ibiṣẹ́ ní ìbàdàn,0,yoruba "igba mi owó àkokò, Alàji lo ìgbà ọkọ.",0,yoruba "Ìbẹ̀rẹ̀ vidíò yorubá tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "àkokò, Ọba ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..",0,yoruba iyalẹnu wey ti o nuni ti o lẹ.,0,yoruba "O fi kun pe idi ti oun ko fi yọju sibi ipade naa ni pe, wọn ko tete fi iwe pe oun, yatọ si awọn nnkan miran to yọju. Gomina Akeredolu fi ọrọ naa lede ninu atẹjade kan to fi soju opo Facebook rẹ, eyi ti akọwe iroyin rẹ, Richard Olatunde buwọ lu. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: O ni ""O wu Akeredolu lati wa nibi ipade naa nitori o da lori abọ ipade ti awọn gomina iha Guusu Naijiria ṣe niluu Asaba. Idi ti gomina naa ko ṣe yọju sibi ipade naa ni pe, ko tete ri iwe ipe ati pe o ni ipade miran to ni lati yọju si niluu Ibadan, ṣaaju ki iwe ipe ọhun to de."" Down Syndrome Skill centre: Wo bí ọmọ tí ọpọlọ wọn kù díẹ̀ ṣe ń kọ́ iṣẹ́ agẹrun Sugbọn gbogbo awọn ohun ti awọn ti adari ẹgbẹ APC fẹnuko le lori niluu Eko ni Akeredolu fọwọ si nitori awọn ọrọ naa ṣe pataki fun ilọsiwaju ati iṣọkan orilẹ-ede Naijiria. ""Ẹwẹ, gomina ipinle Ekiti, Kayode Fayemi naa ti fi ọrọ lede lori idi ti ko ṣe yọju sibi ipade apero ọhun. Ninu atẹjade kan to fi soju opo Twitter rẹ, Fayemi ni kii ṣe pe oun mọọmọ pinnu lati mase yọju sibi ipade ọhun, ṣugbọn iwe ti wọn fi ranṣẹ ko tete tẹ oun lọwọ. Gẹgẹ bo ṣe sọ, ""Iwe ipe fun ipade naa ti wọn ni amugbalẹgbẹ Tinubu fi ranṣẹ lori ẹrọ atẹjiṣẹ WhatsApp ko tẹ Gomina Fayemi lọwọ. Epe Fish Market: Wá wo oríṣi ẹja tí o rírí lọ́jà ẹja tó tóbi jùlọ ní Nàíjíríà ""Gomina Fayemi ko ri iwe ipe ipade, lo fa ṣababi idi ti ko fi si nibẹ. Fayemi ni oun ti tọrọ aforiji lọwọ awọn adari ẹgbẹ naa lori bi oun ko ṣe yọju sibi ipade ọhun, oun ko mọọmọ. O pari ọrọ rẹ pe, digbi ni oun wa lẹyin awọn adari ẹgbẹ naa lori gbogbo oun ti wọn fẹnu ko le lori nibi ipade ọhun. Ile ijọba ipinlẹ Eko ni ipade awọn adari ẹgbẹ oselu APC naa ti waye, nibi ti wọn ti bu ẹnu atẹ lu awọn to n pe fun ipinya Naijiria. Wọn tun fẹnuko pe Naijiria dara ni oṣuṣu ọwọ ju ki o pin lọ. Akungba Suicide: Ẹbí, ọ̀rẹ́ àti ọ̀gá iléẹ̀kọ́ sọ̀rọ̀ lórí irú èèyàn tí Feranmi Fasunle jẹ́ Lara awọn to wa nibi ipade naa ni aṣaaju ẹgbẹ APC ni Naijiria, Bola Hamed Tinubu, gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu, atawọn eekan mii ninu ẹgbẹ oṣelu APC. Tinubu, Gbajabiamila, Sanwo-Olu gbárùkù tí fífòfin de dída ẹran káàkiri ìgboro Awọn adari ni ẹgbẹ oṣelu APC ni Iwọ oorun Naijiria ti fi ọwọ sowọpọ pẹlu awọn gomina ni iha Guusu Naijiria lati fofin de awọn Fulani darandaran lati maṣe da ẹran kaakiri igboro mọ. Awọn adari ẹgbẹ oṣelu APC naa gbe igbesẹ ọhun lasiko ipade to waye ni bonkẹlẹ ni ilu Eko ni Ọjọ Kẹtalelogun, Oṣu Karun, ọdun 2021. Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu to pe ipade naa ninu atẹjade to fi lede ni awọn fi gbogbo ara wa lẹyin abajade ipade awọn gomina Iwọ Guusu Naijiria. Àfinra! Amotekun lé àwọn Fulani 137 tó gba inú igbó ìjọba lọ́nà àìtọ́ kúrò l'Ondo 'Ọkọ̀ ńlá méjì ló kó àwọn Fulani wọ Ajowa Akoko ní Ondo, àmọ́ a ti jọ ń sọ̀rọ̀ pé ...' Àwọn ọmọ Naijiria n sọ òkò ọ̀rọ̀ sí Buhari àti Osinbajo pé wọn kò lọ sí ìsìnkú Ibrahim Attahiru TAMPAN pàṣẹ pé 'director' kankan kò gbọdọ̀ pe Nkechi Blessing àti Adams Kehinde sí iṣẹ́ mọ́ Mo dúpẹ́ pé ìgbà tí mo wà nínú Jesu ni mo lọ sẹ́wọ̀n, tó bá jẹ́ pé mo wà nínú áyé ni ... - Wòlìí Genesis Wo àwọn orílẹ̀èdè tí ìbálòpọ̀ akọsákọ ti lòdì sí òfin Bakan naa ni wọn parapọ sọ wi pe eto oṣelu to fi aye gba ki ipinlẹ kọọkan ni agbara lati le da nkan ṣe fun ara wọn, iyẹn ''True Fedralism'' yoo jẹ ki eto oṣelu tiwantiwa gbooro si. Bakan naa ni wọn fikun pe ijọba apapọ gbọdọ fun ijọba ipinlẹ ni anfaani lati gbe igbesẹ lori eto aabo wọn ni abẹle, ki o to doju ru, ti yoo si fa rogbodiyan kaakiri Naijiria. Awọn adari ni ẹgbẹ oṣelu APC ni Iwọ Oorun Naijiria naa fikun pe eto aabo ti ko munadoko ni Naijiria, ti mu ki igbeaye niran fun awọn araalu, ti iya ati iṣẹ si gbode kan. Pé mo gba ìwọ́de lááyè kò túmọ̀ sí pé mo faramọ́ Oduduwa Nation - Akeredolu Wọn ò bí Baba Ijesha dáa kó sọ pé kò mọ mí rí - Agbẹjọ́rò Adesina Ogunlana Àìsàn jẹ́ kí àwọ̀ ara Amida dàbí ara ẹja",0,yoruba RT @user: @user oye ko gbo abo.,0,yoruba name it segment abala sọọ́ lórúkọ we go into mathematics today what yorùbá word coined or derived can we use in place of formula a wọ inú ìṣirò ní òní orúkọ yorùbá ìṣẹ̀dá tàbí ìlò wo ni a lè lò dípò formula,0,yoruba "Ààrẹ Muhammadu mú àdínku ba owó ìdánwo fún ìr'srún òbí-JAMB Eyi di mimọ nibi ìpade igbimọ alaṣe to waye lána, nílé ìjọba nílù Abuja Lásìkò tí BBC bá àwọn tọ́rọ̀kàn lórí ọ̀rọ́ náà láti fi ìdí abájọ múlẹ lórí ìdí ti ìgbésẹ̀ yìí fi wáyé nírú àsìkò yìí. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ àgbénusọ fún àjọ Jamb Ọmọ̀wé Fabian Benjamin tó bá BBC sọ̀rọ̀ sàlaàyé pé àfojúsún tí ìjọbá fún àwọn láti siṣẹ́ ló ń tukọ̀ ìṣesí àjọ JAMB pàápàá jùlọ láti ìgbà ti ọjọ̀gbọn Isa'aq Oloyede ti dí adarí àjọ náà. O ní ìdí ti èyí kò fi wáye ní ọdún tó kọja ní pé ìjọba kò ti rí àrídájú bóyá àjọ náà yóò le ṣe ojúṣe wọn ti ìgbéṣẹ̀ náà bá wáyé. Sùgbọn èyí ṣẹlẹ̀ lọ́dùn yìí nítori pé kò sí kọnu-kọhọ nínú ètó àjọ náà àti pé owó tó ń wole sápò ìjọba kò dínkù, ó fi kún-un pé ààrẹ Muhammadu Buhari tí ń wà gbogbo ọ̀nà láti mú àdínkú ìṣẹ́ tó wà láwùjọ. Ààrẹ Muhammadu mú àdínku ba owó ìdánwo fún ìr'srún òbí-JAMB Nínú ọ̀rọ̀ tirẹ ọgbẹni Mubaraq Akintola tó jẹ onímọ nípa ètò ẹkọ nínú ọ̀rọ̀ tirẹ̀ sàlàyé pé ìgbésẹ̀ ààrẹ yìí jẹ ohun ìwúri sùgbọn kìí ṣe èyí níkan ní ǹkan tí ètò ẹkọ́ orílẹ̀-èdè yiìí nílo rèé lásìkò yìí. Kíní àwọn ohun tí ètò ẹkọ Nàìjíríà nílò Gẹ́gẹ́ bí ọgbẹ́ni Akintola ṣe sọ, ó rọ ààrẹ Muhammadu Buhari láti wá ojútu sí ìyanṣẹ́lódi ti ASUU gùnlé lọ́wọ́lọ́wọ́ báyìí nítori pé tí àwọn ọmọ náà bá parí ilé ẹkọ́ gíga náà ní wọn yóò wọ. Ó rọ ìjọba láti jókó pọ pẹ̀lú àwọn adarí àwọn ASUU láti tọwọ́bọ̀wé lórí àdéhùn tí wọn pinu láti muṣẹ Lórí ibi ti ètEkó dé lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Akintola nní àwọn olùkọ náà nílò ìwúrí to tọ, o fíkun pé ààyè ti ìjọba fí àwọn olùkọ síí kò mú ìwúri dáǹí láti ori owo osù òṣìṣẹ́ títí tó fi mọ ọ̀nà ti wọn ń gbà láti ṣiṣẹ́. Akintola ni kò sí ìwúri kankan fáwọn olùkọ tí ó le mú kí wọn ṣe iṣẹ́ wọn dáradára. Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ Akintola tún parọwa sí ìjọba láti rii dáju pé ìjọba àti gbogbo àwọn eléto ìjọba gbọdọ máà rán àwọn ọmọ wọn náà lọ si ilé ẹkọ ti ìjọba dá sílẹ̀ nítori ọnà yìí níkàn ní ọnà àbáyọ ti tolórí tẹ́lẹmù yòó fi gbárùkù ti ètò ẹkọ lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà 2018 Jamb: Awọn akẹkọ fọnmu lori iforukọsilẹ Ajọ JAMB sun ọjọ iforukosilẹ idanwo UTME siwaju lati ọsẹ meji sẹhin Ọgọọrọ awọn akẹkọ to n gbaradi fun idanwo asewọle sile ẹkọ giga, UTME tọdun yii ti fẹhọnu han lori bii ajọ Jamb se ti oju opo ti wọn ti n forukọ silẹ fun idanwo UTME tọdun yii. Awọn akẹkọ naa ni wọn yabo agbegbe Bariga nilu Eko, pẹlu paali ti wọn kọ ẹhọnu wọn si lọwọ wọn, ti wọn si n sọ wipe ọpọlọpọ awọn ni ko tii forukọ silẹ fun idanwo naa. Idanwo tọdun yii naa ni yoo waye lọjọ kẹsan si ọjọ kẹtadinlogun osu kẹta, ọdun yii. Sugbọn tawọn to n fẹhọnu han naa sọ wipe, awọn fẹ ki wọn sun siwaju di osu Karun. Gẹgẹbi ọrọ awọn akẹkọ naa, awọn to kọ idanwo tọdun to kọja, ko tii wọ ile-iwe nitori sunkẹrẹ fakẹrẹ eto ẹkọ lorilẹede Naijiria. Lara ohun ti paali ti wọn gbe lọwọ yi ""ọọdunrun akẹkọ ni ko tii forukọ silẹ fun idanwo UTME"", ""Awa ko tii setan fun idanwo"" ati wipe ""Idanwo tọdun yii yoo jasi pabo"". Awọn akẹkọ to bawọn akọroyin sọrọ ni awọn ko tilẹ tii se '""silabọọsi"" ti saa yii tan, ati wipe ajọ Jamb n jẹ kawọn san owo toto ẹgbẹrun meji aabọ naira, tawọn ba se asemase kankan lasiko iforukọ silẹ fun idanwo UTME tọdun yii.",0,yoruba ẹ̀kọ́ dídì yìí ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "Gomina Rotimi Akeredolu ti ipinlẹ Ondo ti sọ pe awọn gomina 'yahoo-yahoo' laarin awọn gomina to wa lẹgbẹ oṣelu APC ni wọn n gbiyanju lati da omi ẹgbẹ oṣelu naa ru. Gomina Rotimi Akeredolu ninu ọrọ to sọ nipa bi nnkan ṣe n ri lagbo ẹgbẹ oṣelu naa lọwọlọwọ yii ṣalaye pe gbogbo ilakaka awọn to da ẹgbẹ oṣelu naa silẹ lawọn eeyan kan to pe ni arijẹnidimadaru ti wọn wa nipo ijọba n gbiyanju bayii lati doju rẹ bolẹ. Gomina Akeredolu ṣalaye peifẹsẹmulẹ awọn gomina kan lẹgbẹ oselu APC pe ko bajẹ laye olugbọn ko yẹ ko bajẹ laye awọn lo mu ki ẹgbẹ naa tete ṣẹri pada si ọna iṣejọba tiwantiwa nipa titẹle ilana ti Aarẹ Muhammadu Buhari la kalẹ fun ẹgbẹ naa fun ilana iṣejọba tiwantiwa laarin ẹgbẹ oṣelu naa lee tubọ fidimulẹ sii. Nigba ti wahala igbimọ adari ṣuyọ ni ẹgbẹ oṣelu APC lẹyin ti wọn yọ alaga apapọ ẹgbẹ oṣelu naa tẹlẹ, Adams Oshiomhole lawọn agbaagba ẹgbẹ oṣelu naa pe jọ lati gbe igbimọ fidihẹ kalẹ lati ṣe akoso ẹgbẹ oṣelu naa titi di igba ti wọn yoo fi ṣe akanṣe ipade idibo yan awọn aṣoju ati adari ẹgbẹ oṣelu naa. Wọn yan Gomina Buni lati jẹ alaga igbimọ naa, amọṣa gomina Akeredolu ni igbesẹ 'iditẹgbajọba alagbada' ti gomina Buni atawọn kan ninu igbimọ naa bẹrẹ si nii gbe lẹnu ọjọ mẹta yii tako ọna ti ẹgbẹ oṣelu naa la kalẹ lati rin ti ko si dun mọ ọpọ ninu rara. Rotimi Akeredolu ni awọn gomina kan, ninu eyi ti oun wa ni wọn yẹ aga mọ Buni atawọn to ko sodi nidi nibi ti wọn ti n gbimọran ki ipade idi apapọ ẹgbẹ oṣelu naa o maa waye.",0,yoruba Bákan náà ni ó jẹ́ òǹdíje sí ipò ààrẹ ní abẹ́ ẹgbẹ́ olóṣèlú Allied Congress Party ti Nàìjíríà .,0,yoruba ri pe nilo ayẹwo wey ti o jare.,0,yoruba "Àwọn ọmọ Èkó pàdánù ẹ̀mí, ọba Kòsọ́kọ́ sá lọ Àpápá. #Apapa ni Kòsọ́kọ́ bá wọ Ẹ̀pẹ́. #Lagos #OgunAhoyaya #Yoruba https://t.co/Z633qDrLGF",0,yoruba "nípa àìmọ́. Nitori eyi, ara eni lo ni àṣà yorubá eyti o gbe lori ọ̀run dídì.",0,yoruba owó la fí ń wáwó ọjà tá a fowó rà owó la ó fi pa ẹ máa yáṣẹ́ o,0,yoruba "èwe. Nitori eyi, ara eni lo ni ìwájú.",0,yoruba ni òun tí a ní láti ṣe aṣọ̀.,0,yoruba "Boya eyi lo mu ki igbakeji aarẹ nilẹ wa, Yemi Osinbajo fi n lọgun nipa isẹ ati osi to n bawọn ọmọ Naijiria mulẹ, bii ẹgbẹ isu. Osinbajo ni ipa nla ti arun Coronavirus nni lori ọrọ aje ati igbayegbadun wa ni Naijiria lojoojumọ lagbara pupọ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ninu atẹjade kan ti akọwe eto iroyin rẹ, Laolu Akande fisiti lo ti jẹyọ pe Osinbajo ke gbajare yii nibi agbeyẹwo isẹ iriju ọdun kinni awọn to dipo ilu mu. Mayowa Omoniyi: Kò sí orin Obey, Sunny Ade abí tàkasúfèé tí ń kò le ta gìtá sí Osinbajo wa kesi awọn minisita lati gbe igbesẹ ni kanmọ n kia lori owo triliọnu meji o le diẹ naira tijọba gbe kalẹ lati mu adinku ba ipa arun naa lori ọrọ aje Naijiria. Osinbajo ni ""ọjọ kẹtadinladọrin ree ta ti se ifilọlẹ eto naa, idi si ree ta fi gbọdọ se amusẹ rẹ ni kiakia, ki ori to ta araalu jinna. Bakan naa si la gbọdọ ri daju pe a n se odiwọn awọn aseyọri wa lojoojumọ, ta si n se gbogbo ohun to yẹ ni sise. Akoko kii se ọrẹ wa mọ, isẹ ati osi si n jinlẹ laarin ilu si lojoojumọ ni."" Nigba to n sọrọ lori eto ọgbin ọlọpọ eniyan, Osinbajo ni ijọba ti se akọsilẹ miliọnu mẹrin agbẹ lati kopa ninu rẹ. Lori eto ilegbe, o ni ijọba yoo kọ ilegbe ẹgbẹrun lọna ọọdunrun jake jado Naijiria eyi towo rẹ ko ni ju miliọnu meji naira lọ. O fikun pe, gbogbo awọn igbesẹ naa lo wa lati pese isẹ oojọ fun araalu. Mi ò kọ̀wé fipò sílẹ́ - Osinbajo Igbakeji Ààrẹ Yemi Osinbajo ti fesi si ahesọ ọrọ kan n to tan kalẹ lori ayelujara wipe, o ti binu kọwe fipo sile. Ọsinbajo sọ lori itakun Twitter rẹ wipe, iroyin ofege ti wọpọ ni orilẹede Nigeria nitori oṣelu. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: O ni ""Mi o ti i kọwe fipo silẹ o. Mo duro digbi lati siṣẹ sin awọn ọmọ Naijiria labẹ iṣakoso Aarẹ Muhammadu Buhari. A gbọ wipe awọn iroyin ofege naa sọ wipe, Osinbajo ti fi ibinu kọwe fipo silẹ nitori wipe wọn ko pe e si ibi ipade kan ni ile ijọba.",0,yoruba "Ọdun Ileya Buhari ni alaafia ni ki wọn maa lepa nitori ẹsin alaafia lẹsin musulumi bo tilẹ jẹ pe awọn alajagbinla kan ti fun ẹsin naa lorukọ buruku pẹlu iwa ipa wọn. Aarẹ Buhari to sọrọ ninu atẹjade kan to fi ki awọn musulumi ki ọdun Ileya, sọ pe ifaraẹnijin to ṣe pataki julọ fawọn musulumi ododo ni pe ki wọn fi idajọ otitọ ati ododo ṣe atọna wọn lọjoojumọ. ''Ọjà ẹran àgbò kò yá bí ti ọdún tó lọ'' Oro Festival: Àwọn olórò ní ọdún Màgbó ló ń gba ibi lọ, kó ire wọlé ní Ikorodu Buhari iwa apanle ni ipenija to tobi julọ to n koju ẹsin musulumi lagbaaye bayii, aarẹ ni ọna kan gbogi lati din ipa buruku iwa yii ku ni pe koni kaluku yago fawọn waja awọn ti ko mọ wọ ti mẹ sẹ. Bakan naa ni aarẹ Buhari rọ awọn obi lati mojuto awọn ọmọ wọn kawọn maa ba ya wọn lo lati fi wọn wuwa ipa lorukọ ẹsin. Aarẹ Buhari dẹbi ru awọn musulumi lori ọrọ agbesunmọmi Boko Haram nitori wọn o tete dẹkun iwaasu odi tawọn Boko haram n gbe kiri ki wọn to di nla. Buhari ko sai fi dawọn ọmọ Naijiria loju pe ijọba oun n ṣiṣẹ takuntakun lati fopin si Boko Haram, iṣẹlẹ ijinigbe ati awọn iwa ọdaran mii to gbode kan ni Naijiria. Niluu rẹ, Daura nipinlẹ Katsina ni Aarẹ Buhari ti sọdun Ileya.",0,yoruba Àrá sán pa ọ̀dọ́kùnrin mẹ́rin tó ń gbá bọ́ọ̀lù nínú òjò l'Ondo,0,yoruba ni ìrìn ìròyìn kan mòní nípa àkóbì asin.,0,yoruba "RT @user: Ẹdan kì í kú, kì í rùn. Ojú Ẹdan kì í fọ́ nílédì. #Yoruba #Ogboni #Ogboran https://t.co/66pPsXkMrG",0,yoruba irúfẹ́ èso wo ni àgbagbà,0,yoruba Kò yá mi lára láti kọ lọ́sẹ̀ọ̀sẹ̀ mọ́ sórí http://t.co/cYVinSLF6c @user #bloggerkiniyorubase #EdeAbinibi #Yoruba,0,yoruba "RT @user: Àwọn ẹ̀dá ẹranko àti ewéko ń dínkù lórí ilẹ̀ ayé, bẹ́ẹ̀ náà ni ti ẹyẹ yìí tí kò sí ní ibòmíràn lórí ilẹ̀ ayé àyàfi ní Nepal..…",0,yoruba ìṣẹ́ tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Bàbá lo aye àìlẹ̀.,0,yoruba ise ni ogun ise tepa mo ise oore mi ekaaro gbogbo omo yoruba ni tile toko,0,yoruba "Ní òwúrọ̀ ọjọ́run ni ọkunrin awa kùsà kan kú ní Goma níbi ti ènìyàn tó le ni miliọnù meji. Ní bayìí ibẹru bojo ní àwọn ènìyàn Rwanda wá nítori ìlú Goma pààlà pẹlú Rwanda ti àwọn ènìyàn sì tí ń rò ó pé àisàn náà le tan ju bó ṣe yẹ lọ. Ní òwúrọ̀ ọjọ́run ni ọkunrin awakùsà kan kú ní Goma níbi ti ènìyàn tó le ni miliọnù meji ń gbé. O lé ni ènìyàn ẹgbẹ̀jọ ènìyàn tó ti kú nítori àìsàn Ebola láti ìgbà to ti bẹ́ sílẹ̀ ní nínú oṣù kẹrin ọdún 2018 ní àwọn abúle DRC. Àjọ WHO tí kéde pé ìṣẹ̀lẹ̀ pàjáwìrì ni ọ̀rọ̀ Ebola yìí lọ́sẹ̀ tó kọja. Ìgbà mẹ́rin ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ní àjọ WHO tí ló ìrú ìkéde yìí tó fi mọ àsìkò ti Ebola gba gbogbo ìhà Ìwọ̀-òòrun Afirika láàrin 2014 -2016 tó pa ènìyàn tó lé ni ẹgbẹ̀rún mọkànlá. Ènìyàn méji ló ti kú lórí àìsàn Ebola ni DRC Ẹni tí ìṣẹ̀lẹ̀ ọhun tún bẹ̀rẹ̀ lóri rẹ̀ báyìí wá láti ìhà ìlà-òòrun arewa Ituri ti wọ́n si gbe e lọ si ilé ìwòsàn Kizba ní àgbègbè Goma lójọ kẹtàlá osù keje. Lẹ́yìn èyí ni wọn ri àwọn àmì Ebola bii ki ẹ̀jẹ̀ máa ya, wọ́n ṣe àyẹwò àbájade àyẹwo yii ló fìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé Ebola ni . O gbẹmi mi ni ọjọ́rú. Ní báyìí, àgbègbè méji ni Ebola n dà láàmú ni DR Congo, North Kiv àti Ituri, Goma ni olúlùú Kivu tó sì pààlà pẹ̀lú ìlú Gisenyi tó wà ni Rwanda.",0,yoruba "Bí - ó - ti - lẹ - jẹ́ - pé ẹ̀yà ẹyẹ orílẹ̀ èdè Nepal ju 800 lọ , ẹyẹ Spiny Babbler ( Turdoides nipalensis ) jẹ́ ẹ̀dá tí kò sí ní ibòmíràn àyàfi orílẹ̀ èdè náà .",0,yoruba "lọ. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Àìmọ́ ni ó pa Ọmọ lo ìgbà ọkọ. ìgbà àkerekere. Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Aarẹ Ọna Kakanfo ilẹ Yoruba Gani Adams ti kesi aarẹ Muhammadu Buari lati ri pe o fi iwe ofin miran parọ ti 1999 to wa nilẹ saaju ki idibo ọdun 2023 to waye. Adari ati agbaọjẹ ilẹ Yoruba yi ni ki aarẹ Buhari mu atunto ba orileede Naijiria ati pe nkan to seese ni ti aarẹ ba fi ọkan si. Lasiko to n ba awọn akọroyin sọrọ ni Ile Ife nibi asekagba ajọdun Oduduwa lọjọ Aje ni o ti fi ọrọ yi lede. Kini Iba Gani Adams tun so nibẹ? Iba Gani Adams sọ pe ẹnikẹni to ba n pe fun idio labẹ eto ijọba yi,ọdaran lo yẹ ki wọn pe onitọhun. O sọ pe ''atunse iwe ofin Naijria gbọdọ waye saaju idibo ọdun 2023.Mi o ni sọ pe ki idibo ma waye ni 2023 sugbọn o se pataki ti a ba fẹ tẹsiwaju gẹgẹ bi orileede, ki a se atunto si agbegbe'' ''Bi a ko ba se eleyi, mo nigbagbọ pe ẹnikẹni ti a ba yan sipo, ko ni ri nkankan se labẹ eto taa n tẹle yi.Bi a ba dibo wọle fun , yoo maa sojo lati fọwọ kan iwe ofin.Buhari n palẹmọ bayii, asiko diẹ lo wa fun lati tun eto yi se kuro nibi to wa bayii.'' Gani Adams wa kesi awọn ile asofin ati alẹnulọrọ lati mu iyipada ba iwe ofin si ti ẹda ọdun 1960 ati 1963 ki Naijiria baa le ni ilọsiwaju. Lakotan, Gani Adams kesi Ooni Ile Ife Oba Adeyeye Ogunwusi pe ki o ba awọn Gomina ipinlẹ kaarọ o jiire lati ya ọjọ sọtọ fayajọ ayẹyẹ Oduduwa to jẹ babanla awọn Yoruba.",0,yoruba "fè joko, Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìṣẹ̀: ti o ní wúlò fún gbogbo.",0,yoruba Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìwà: ti o dara.,0,yoruba ni ọ̀gbọ́n. Alàji lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "RT @user: @user beeni bibeli gan fi idi e mule, awa gan",0,yoruba "Ǹjẹ́ o máa ń s'oúnjẹ nílé bí? Ǹjẹ́ o ti gbìdánwò rẹ láti s'oúnjẹ? Ìwádìí fi hàn pé ìgbà díẹ̀ ni àwọn èèyàn ń lò nílé ìdáná bóyá nítorí oúnjẹ-àsèsílẹ̀ nílé ìtajà-ìgbàlódé, àbí nítorí àsìkò tí ò sí àbí látorí ìdínkù ìmọ̀ ẹ̀kọ́ oúnjẹ ṣíṣe láti ọwọ́ òbí sí ọmọ.",0,yoruba "fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Nitori eyi, ara eni ni nfàn ojú kakaaki.",0,yoruba Orúko mi ni Olájídé Omolayó láti ìpínlè Èkìtí. Omo Yorùbá rere ni mi. #TweetInYoruba,0,yoruba "Nigba to n sọrọ nibi apero kan to da lori ọna lati ṣeto aabo to mọyan lori, Monguno ṣalaye pe lai fopin si Almajiri bayii, yoo pada wa ṣakoba fun orilẹede Naijiria lọjọ iwaju. Loṣu kẹfa to kọja ni Monguno sọ pe ijọba apapọ n gbero lati fi opin si Almajiri ki iru awọn ọmọ le lanfaani lati lọ si ile iwe. Ọgbẹni Monguno fifi opin si Almajiri kan gbogbo eeyan kii ṣe ijọba nikan lọrọ naa kan. Bakan naa lo sọ nibi apero ọhun pe ọrọ eto aabo to mẹhẹ ni Naijiria nii ṣe pẹlu awọn ọta ile ti wọn ṣi ilẹkun fun ti ita. O ṣalaye siwaju si pe awọn kọlọnbiti ẹda kan ni wọn lẹdi apo pọ pẹlu awọn kan nilẹ okere lati maa da eto alaafia ru ni Naijiria. Monguno ni ijọba fẹ lo apero lori eto aabo lati wa ojutuu si iṣoro eto aabo to mẹhẹ, eto ẹkọ ti ko munadoko ati awọn idojukọ pẹlu eto ilera ni Naijiria.",0,yoruba díẹ̀ lára àwọn gbajúgbajà olórin ìbílẹ̀ ni sàká láíwọlá popular jingo lefty sàlámì haruna ìṣọ̀lá yusuf ọlátúnjí àyìnlá ọmọwúrà àyìndé barrister kwam adéwálé àyúbà sàlàwà àbẹ̀ní àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ,0,yoruba "Eto naa yoo ṣe awọn akanda ẹda lanfani Eto naa to pe akọle rẹ ni ""Aim High"" lo fi lọlẹ lẹyin awọn idanilẹkọọ to waye nigba to ṣabẹwo si ẹka ileeṣẹ naa to wa lorilẹ-ede Kenya. Hall sọ pe, eto naa yoo fi aye silẹ fun awọn akoroyin mẹta to jẹ akanda lati ṣiṣẹ fun oṣu mẹta, bẹrẹ lati ọsun kẹrin ọdun 2020. Awọn akọroyin naa yoo siṣẹ lori ẹrọ asọrọmagbesi ati ẹrọ ayelujara ni ẹka ileesẹ BBC to wa ni Nairobi, pẹlu awọn akẹgbẹ wọn miran lati orilẹ-ede Afirika. Eto naa yoo ṣe awọn akanda ẹda lanfani Hall ni ""Iroyin BBC to n wa lati ilẹ Afirika n de ọdọ awọn eeyan ti ko din ni ọgọrun un miliọnu kan."" O tẹsiwaju pe ""A fẹ ki awọn akọroyin ṣe iṣẹ wọn lai si ibẹru, a si fẹ ran awọn alaabọ ara lọwọ."" Hall ni oun mọ pe o ṣoro fun awọn akanda ẹda lati gbori soke ninu isẹ akọroyin. O sọ siwaju sii pe ""Afojusun wa ni lati pese idanilẹkọ to peye fun wọn, mo si rọ awọn ti ọrọ naa kan lati mu anfani yii ni ọkunkundun."" Alaye ni kikun nipa eto naa ni ileeṣẹ BBC yoo fi lede ti asiko ba to. Nigeria Independence Day: Wo ìlérí tí àwọn ènìyàn ṣe",0,yoruba "Ní nígbà àkerekere, Baàlè ri Nitori eyi, ara eni yi ojú òní. ti Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba nínú ọ̀rọ̀ọ rẹ̀ pẹ̀lú bbc joenia sọ pé ohun tí ó ṣe pàtàkì sí òun jùlọ nínú ìgbìmọ̀ náà ni ìyàsọ́tọ̀ àwọn ilẹ̀ abínibí htt,0,yoruba Ṣẹ̀dà àdírẹ̀sì lẹ́tà kọ̀ǹpútà “%s”,0,yoruba "Awọn oniṣowo oogun oloro naa ti kọ ẹyẹ ọhun lati pariwo ''mama, ọlọpaa'' ni ede Pọtugi lati jẹ ki awọn ọdaran naa mọ pe awọn ọlọpaa n bọ. Ileeṣẹ ọlọpaa gbagbọ pe awọn oniṣowo naa ''mọọmọ kọ ẹyẹ ayekootọ naa ni ofofo ṣiṣe ni,'' nitori lọgan ti awọn ọlọpaa ba ti sun mọ ile ti awọn oloogun oloro naa wa, ni yoo bẹrẹ si ni i pariwo.'' Lẹyin ti ọwọ ọlọpaa tẹ ẹyẹ naa, wọn fi pamọ si ahamọ wọn lati fi ọrọ wa a l'ẹnu wo lori ohun to mọ nipa awọn oniṣowo oogun oloro ọhun. Dokita ẹranko kan, Alexander Clark, ti awọn ọlọpaa gba lati fi ọrọ wa ẹyẹ naa lẹnuwo sọ pe ''niṣe ni ayekootọ kọ̀ lati sọ ohunkohun.'' Ileeṣẹ ọlọpaa ti sọ pe awọn yoo fa ẹyẹ naa le awọn alaṣẹ ibugbe ẹranko to wa ni agbegbe naa lọwọ nibi ti yoo wa fun oṣu mẹta lati kọ́ bi yoo ṣe maa fo, ko to o di pe wọn yọnda rẹ.",0,yoruba "Ọ̀rọ̀ ìperí ní èdèe Swahili àkàwé oògùn náà ni “ amùjẹ̀ """""""" tàbí “ agbẹ̀jẹ̀ - fún - ìwòsàn """""""" — tí ó ti di “ ìmórí - ẹni - sábẹ̀ """""""" báyìí .",0,yoruba "lẹ. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Bàbá lo ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba Ìlú yorubá lo ni àṣà yorubá eyti o gbe lori iwa rere. A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba "igba mi owó àkokò, Ìyá lo tun se lọ.",0,yoruba "Alao Akala: Àwa àti ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo la jọ ń ṣèpàdé, ohun tí mọ̀lẹ́bí sọ gangan rè",0,yoruba "Harry Kane ló ń ṣíwáájú nínú àwọn tó ti gbá bọ́ọ̀lù sáwọ̀n jù ní Russia pẹ̀lú àmì ayò márùn ún Ayo mẹta ọtọtọ ni ẹlẹsẹ ayo Harry Kane gba sawọn bi ikọ England ti pegede bayi lati kopa ninu ipelekeji idije ife ẹyẹ agbaye t'ọdun yii. Adiẹyinmu fun ẹgbẹ agbabọọlu Manchester City John Stones naa fakọyọ ninu ifẹsẹwọnsẹ ọ'un lẹyin igbati o gbayo meji sawọn. Ìyìn, ati ìmọ̀ràn fún Super Eagles World Cup 2018: Àwọn ọmọ Nàíjíríà kún fáyọ̀ lóri Super Eagles 'Ìjọba APC ní láti tún wọlé lẹ́ẹ̀kan síi' Jesse Lingard to n gba bọọlu fun Manchester United naa ko gbẹyin bi o ti gba ami ayo kan sawọn. Felipe Baloy dayo kan pada ninu mẹfa fun ikọ Panama, ṣugbọn ẹpa ko boro mọ. Eyi ni igba akọkọ ti ikọ England yoo gbayo mẹrin okere tan wọle ninu ifẹsẹwọnsẹ kan ninu idije ife ẹyẹ agbaye lati ọdun 1966.",0,yoruba @user @user @user @user @user @user @user @user @user @user emi no fe gbiyanju: aje ku iya ni'oje 🎶 aje ku iya ni'oje 🎶 eni ti o t'eni no 🎶 t'on de na de ni 🎶 aje ku iya ni'oje 🎶 😂😁😂 #TweetInYoruba,0,yoruba Àpẹẹrẹ wo ni ti òwìwí nínú ilé ìgbìmọ̀ ?,0,yoruba Richard Akínjídé dágbéré fáyé ní ìkan bíi agogo kan òru ọjọ́ Ìṣẹ́gun .,0,yoruba "Ọpọlọpọ miliọnu eniyan, papa awọn obinrin ni Asia ati Africa lo n gba oriṣiriṣi ọna lati di eniyan pupa. Ọmọbinrin yii, Shiroma Pereira (ti a fi orukọ bo ni aṣiri), n mura fun ayẹyẹ igbeyawo rẹ. Lara imurasilẹ rẹ gẹgẹ bi ọpọ ṣe maa n ṣe ni South Asia, ni pe o pinnu lati bo ara rẹ ṣaaju ọjọ igbeyawo. O ni ireti aàwọ ara to n dan, to si rẹwa. Cerebral Palsy: àrùn tó n gba omijé lójú ẹni láìnídìí Oṣu meji ṣaaju ọjọ igbeyawo, o lọ si ṣọọbu aṣaraloge kan, wọn si fun un ni ipara kan lati mu ki ara rẹ o pupa. Lẹyin to lo ipara naa fun ọsẹ kan, oju rẹ pupa. O sọ fun BBC Sinhala pe, ''mo fẹ ki ara mi o pupa, ṣugbọn ṣe ni gbogbo aàwọ mi jona."" Niṣe lo fi gbogbo asiko to yẹ ko fi maa gbaradi fun igbeyawo, ṣe itọju ara rẹ eyi to n gba asiko rẹ ati owo rẹ. 'Àjẹ́, eégún, kí ni wọn ò pè mí tán tórí Vitiligo lára mi' Ipara ti wọn fun un ko si lara awọn eroja iṣaraloge ti wọn fi ọwọ si ni Sri Lanka. Awọn kan lo n ko wọn wọle lọna ti ko ba ofin mu, ti wọn si n ta a ni ọja pade mi ni kọọrọ. Titi di asiko yii lati bi ọdun kan o le, àwọ ara Pereira ko ti i bọ sipo. Iṣoro ara bibo kii ṣe iṣoro to n koju Sri Lanka nikan. Ọpọlọpọ miliọnu eniyan, paapa awọn obinrin ni Asia ati Afrika lo n gba oriṣiriṣi ọna lati di eniyan pupa. Odiwọn ọja eroja ibora l'agbaye to biliọnu marun un Dọla ($4.8bn) lọdun 2017, igbagbọ si wa pe yoo di ilọpo meji nigba ti yoo ba fi di ọdun 2027. Awọn eroja yii pe oriṣiriṣi; ọṣẹ, ipara, ororo, tabilẹti oogun ati abẹrẹ. Awọn eroja yii pe oriṣiriṣi; ọṣẹ, ipara, ororo, tabilẹti oogun ati abẹrẹ, ti wọn ṣe lati le da iṣẹ eroja melanin, to n sọ iru awọ ti eniyan yoo ni, duro. Osun Supreme: Àwọn èèyàn Ọṣun rọ Oyetọla láti jẹ́ kí àsìkò rẹ̀ tú aráàlú lára Gẹgẹ bi ajọ eto ilera l'agbaye, WHO, ṣe sọ, obinrin mẹrin ninu mẹwaa nilẹ Afrika lo n lo awọn eroja ibora. Nilẹ Afrika, orilẹ-ede Naijiria ni wọn ti n lo eroja ibora julọ. Awọn obinrin to n bora jẹ ìdá mẹtadinlọgọrin. Orilẹ-ede Togo lo tẹle e, pẹlu ìdá mọkandinlọgọta, ati South Africa pẹlu ìdá mẹtadinlogoji. A nilo agọ ọlọpa ni Orin Ekiti fún aabo wa -Falua Ni Asia, awọn obinrin ìdá mọkanlelọgọta lo n bora ni India, ti ìdá ogoji si n lo wọn ni China. Lọdun to kọja, awọn alaṣẹ l'orilẹ-ede Ghana kilọ fun awọn alaboyun lati dẹkun lilo oogun ibora to ni eroja antioxidant glutathione. Awọn obinrin l'orilẹ-ede naa n lo oogun naa pẹlu ireti pe yoo mu ki ara ọmọ inu wọn o pupa. Àwọn ọ̀dọ̀ ti ń gbógun ti ara bíbó, ṣùgbọ́n ó ṣì wọ́pọ̀ Orilẹ-ede South Africa ní awọn ofin alagbara to gbogun ti ara bibo. Gambia, Ivory Coast, ati Rwanda ti fi ofin de awọn eroja ibora to ni hydroquinone ninu. Bi o ṣe maa nipese eroja melanin ku ninu ara, naa lo le ba àwọ ara jẹ. Ajọ to n risi ọrọ aàwọ ara ni orilẹ-ede Britain sọ pe, ''awọn ohun to ba ni hydroquinone ninu ṣe e lo lati ṣe iwosan awọn aarun aawọ ara kan, labẹ amojuto onimọ nipa àwọ ara, ti yoo si so eso rere. Ajọ naa sọ pe ''ko si ọna 'otitọ' kankan lo le mu ki gbogbo ara pupa.'' Ṣugbọn, ọpọlọpọ awọn obinrin lo maa n ra awọn eroja ibora lai gba itọni tabi ilana lọwọ onimọ nipa eto ilera. Oriṣiriṣi akoba ni kẹmika ibora maa n ṣe fun ara. Wọn le ni ipa bi i : Ara yiyun ati wiwu Ara tita tabi jijajẹ Ati ki àwọ ara o maa bo (Orisun -NHS UK)",0,yoruba Mo kí dede ọmọ Ẹ̀gbá mọlíṣàbí #Abeokuta #Ogun,0,yoruba "Orisisrisi aisan lawọn eeyan ma n ko latara yiyagbe sita Yala ni awọn ilu kekeeke tabi lawọn ilu nla bi Abuja, Eko tabi Port-Harcourt, ipenija yii jẹ ohun to n kọ awọn eeyan lominu. Ninu iwadi kan ti Ajọ to n risi idagbasoke ọmọ wẹwẹ lagbaye, UNICEF gbe jade lọdun 2017, Naijiria wa ni ipo kẹji ninu awọn orileede ti ṣisẹ igbọnsẹ ni ita gbangba ti peleke. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Orileede India naa n ba ipenija igbẹ yiya ni ita gbangba finra Pẹlu bi iṣesi yii ti ṣe gbale, ki ni awọn aburu to wa ninu ki eeyan ma yagbẹ si ita gbangba lalai bikita. Ewu to wa ninu igbẹ yiya nita gbangba A na ọwọ ibeere yi si onimo isegun ilera ayika ẹni, Dokita Olajire Olanrewaju, to si salaye fun ileese BBC Yoruba wi pe, ewu nla lo wa ninu ki awọn ara ilu ma yagbẹ sita gbangba. 'Yato si wi pe o fun Naijiria lorukọ buruku laarin awọn orileede to ku,iwa yi a ma ṣe ipalara fun ilera ati alafia ara ilu.' Èwo ló pàtàkì jùlọ nínú ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ àti ilé ìgbọ̀nsẹ̀? Iwa ṣiṣe gaa yi ko yọ agba naa silẹ O salaye pe, pupo ninu awọn aisan ti o ma n ba ẹdọ inu ara jẹ, bii Hepatitis A ati Typhoid, maa n wọwa latara bi igbọnse ṣe ma n dapọ mọ omi mumu. Dokita Olanrewaju ni, lawọn ipinlẹ bii Kebbi, Sokoto ati Zamfara nibi ti awọn ijọba wọn ko ti kọ ibi ara si kikọ ile igbọnse, orisirisi aisan a ma ba awọn ara ilu finra. Ki lawọn wole wole n ṣe? Dokita Olanrewaju ni, pelu bi nnkan ti ṣe ri lawujọ loni, o di dandan ki ijọba ṣe agbedide awọn oṣiṣe ilera ti yoo maa tọpinpin ibi ti awọn eeyan n ṣe ibẹrẹ si. 'Bi eeyan ba tapa si ofin, ọlọpa yoo mu iru ẹni bẹẹ, bi ara ilu ba wuwa aitọ nipa ayika, nibo lawọn wolewole wa ti yoo mu iru ẹni bẹẹ?' Awọn wole wole kii mojuto ibi ti awọn eeyan ti n se ounjẹ lopọ awọn agegbe ni Naijiria Dokita Olanrewaju ni, o di dandan ki ijọba pese ohun eelo to yẹ fun awọn oṣise ilera yii lati ṣe iṣẹ wọn. ""Ẹyin e woo nnkan ti ijọba Eko ṣe pẹlu ile ise to n ṣe ọṣẹ kan nipa bi wọn ti ṣe kọ ile iyagbe si awọn arin ọja kaakiri. Iru igbese yi daa pupọ ti a ba fẹ dẹkun iwa ibaje ka ma yagbẹ sita gbangba."" O rọ awọn ara ilu naa ki wọn ri wi pe wọn mu imọtoto wọn lokunkundun.",0,yoruba eba wa se itoju molebi yin kamal kashamu ejo e ba wa parowa fun senator ki won da si oro kamal eledumare a fun yin se,0,yoruba "12. Ẹ̀gẹ́ náà ni pákí, tàbí __. Ọ̀dùnkún náà ni ànàmọ́ tàbí __ #ibeere #Yoruba",0,yoruba "Iyè òṣìṣẹ́ ẹrú dín kù, wọ́n gbọ̀n wọ́n ń gbẹ̀ẹ́, ayé #IndustrialRevolution dé, ẹ̀rọ rọ́pò èèyàn. #BHM",0,yoruba "kọ eḳọ nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìṣẹ́ ọ̀pọ́lọ̀.",0,yoruba A kìí gbà'kàkà lọ́wọ́ akítì. Kò ṣ'ẹni tó lè gba ire mi. Ọlọ́run ló fi fún mi o jàre.,0,yoruba Ṣùgbọ́n ìrírí mi bí wọ́n ṣe ń rí mi bíi atọ̀húnrìnwá ti jẹ́ kí n ní ìmọ̀ nípa àṣà àwọn èèyàn mi : àṣà Tibet .,0,yoruba ohun eri ewi ohun eri ero seun ape kose moshood kashimawo olawale abiola sun re o mko o digbose o o darinako o doju ala o doko alawo ma jokun ma jekolo ohun won ba nje lajule orun ni koo maa bawon je o ile oodua oni parun ile nigeria oni parun a o ni rogun abele mo,0,yoruba o ye ki gbogbo ile iwe bere si lo ayarabiasa fun eko nitori ibi ti aye fi si bayi niyen,0,yoruba "Aisan ọkan ni wọn sọ pe, o pa Ọ̀gágun àgbà Sani Abacha Laifọtape, eniyan ko fẹrẹ jayopa lati sọ pe Ọgagun agba Sani Abacha fẹrẹ jẹ olori ijọba Naijiria ti agbaye sọrọ rẹ julọ. Lẹyin wahala ibo ọjọ kejila, oṣu kẹfa, ọdun 1993 ni Ọgagun agba Sani Abacha, wọle nigba to yẹ aga mọ ijọba fidihẹ Oloye Earnest Ṣonẹkan nidi ni ọjọ kẹtadinlogun, oṣu kọkanla, ọdun 1993. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Laarin ọdun 1993 si ọdun 1998 ti Ọgagun agba Sani Abacha fi wa lori aga iṣejọba orilẹ-ede Naijiria, ọpọlọpọ nnkan lo ṣẹlẹ to jẹ ki awọn onwoye sọ pe o ni ipa lara eto iṣelu orilẹ-ede Naijiria. Atupalẹ diẹ lara awọn igbesẹ Ọgagun agba Sani Abacha ati ipa wọn lori eto iṣelu orilẹ-ede Naijiria. Ipade apero lori iwe ilana ofin (Sovereign Constitutional Conference) Laarin asiko ti Sani Abacha fi wa lori oye, ọpọlọpọ nnkan lo ṣẹlẹ eleyii ti awọn onwoye sọ pe o ni ipa lara eto iṣelu orilẹ-ede Naijiria. Irinwo awọn aṣoju ti wọn yan kaakiri ibu ati oro orilẹ-ede Naijiria ni wọn kopa ninu ipade apero yii laarin ọjọ kẹtadinlọgbọn, oṣu kẹjọ, ọdun 1994 si ọdun 1995 eyi to wa fun agbekalẹ iwe ofin tuntun fun orilẹ-ede Naijiria nigba naa. Ọpọ awọn onwoye ọrọ oṣelu ni wọn foju wo ipade apero yii gẹgẹ bii eyi to dara pupọ kani wọn ṣe amulo awọn abajade rẹ kan ni. Fifi MKO Abiọla si ahamọ Ahamọ Abacha ni MKO Abiọla wa titi to fi jade laye ni ọdun 1998 Ijọba ologun, labẹ Ọgagun agba Sani Abacha lo fi MKO Abiọla si atimọle ni ọjọ kẹtalelogun, oṣu kẹfa, ọdun 1994 nigba ti Abiọla kede ara rẹ gẹgẹ bii aarẹ orilẹ-ede Naijiria ni ọjọ kọkanla, oṣu kejila, ọdun 1994. Ìjọba ologun labe Ibrahim Babangida wọgile esi idibo oṣu kẹfa ọdun 1993 ninu eyi ti MKO Abiọla ti ko pa gẹgẹ bii oludije ipo aarẹ fun ẹgbẹ oṣelu SDP. Ahamọ yii ni MKO Abiọla wa titi to fi jade laye ni ọjọ keje, koṣu keje, ọdun 1998. Yiyẹgi fun Ken Saro Wiwa atawọn ajafẹtọ agbegbe ogoni mẹjọ Oloogbe Bọla Ige ṣe akawe awọn ẹgbẹ oṣelu ti Abacha da silẹ gẹgẹ bii, 'ọmọ ika marun ọwọ adẹtẹ.' Ni ọjọ kẹwa, oṣu kọkanla, ọdun 1995 ni wọn yẹgi fun gbajugbaja onkọwe ati ajafẹtọ ọrọ ayika lẹkun Niger-Delta, Ken Saro Wiwa, atawọn akẹgbẹ rẹ mẹjọ ti wọn ja fun atunṣe agbegbe ogoni nibi ti iṣẹ epo rọbi wiwa ti da wahala alailẹgbẹ si igbaye-gbadun awọn olugbe ibẹ. Eleyi fa ọpọlọpọ ariwo kaakiri agbaye, eyi to fa oniruuru igbesẹ inira lati awujọ agbaye gbogbo. Idasilẹ ẹgbẹ oṣelu marun ati ipinnu lati di oludije kan ṣoṣo fun wọn Awọn ipinlẹ Ebonyi, Ekiti, Bayelsa, Nasarawa, Zamfara ati Gombe ni Sani Abacha da silẹ Ni ọgbọn ọjọ, oṣu kẹsan, ọdun 1996 ni ajọ eleto idibo igba naa NECON fi orukọ ẹgbẹ oṣelu marun silẹ. Awọn ẹgbẹ oṣelu marun yii gba lati yan Ọgagun agba Sani Abacha gẹgẹ bii oludije fun ipo aarẹ labẹ aṣia wọn. Igba yii gan an ni oloogbe Bọla Ige ṣe akawe wọn gẹgẹ bii, 'ọmọ ika marun ọwọ adẹtẹ.' Ṣiṣigun le awọn ẹgbẹ alatako Ni ọgbọn ọjọ, oṣu kẹsan, ọdun 1996 ni ajọ eleto idibo igba naa, NECON, fi orukọ ẹgbẹ oṣelu marun silẹ Lasiko iṣejọba Ọgagun agba Sani Abacha, ọpọ awọn ẹgbẹ alatako lo fara kaaṣa ibinu ati ikọlu rẹ. Awọn ẹgbẹ bii NADECO ati ẹgbẹ oṣiṣẹ ni ijọba ologun ṣigun lu bẹẹni ọta ibọn ati ado oloro awọn agbenipa ṣọṣẹ lara Abraham Adesanya, Kudirat Abiọla, Alex Ibru, Shọla Omatṣọla ati bẹẹbẹẹ lọ. Abraham Adesanya ati Alex Ibru ye ikọlu ti wọn ṣugbọn Kudirat Abiọla ati Ọmatsọla ko yee. Idasilẹ ipinlẹ mẹfa Lasiko ọdun bii marun to lo lori aga aarẹ lorilẹ-ede Naijiria, Ọgagun agba Sani Abacha ṣe idasilẹ awọn ipinlẹ mẹfa tuntun kan ojọ kinni, oṣu kẹwaa, ọdun 1996. Awọn ipinlẹ naa ni Ebonyi, Ekiti, Bayelsa, Nasarawa, Zamfara ati Gombe.",0,yoruba "Àwòrán láti ọwọ́ọ Ọmọ Yoòbá , a gba àṣẹ láti lò ó .",0,yoruba "Àwòrán láti ọwọ́ọ Georgia Popplewell , a lò ó pẹ̀lú àṣẹ .",0,yoruba wúlò. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Alàji lo ni.,0,yoruba "Nígbà àkerekere, Baàlè fi. A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà.. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..",0,yoruba se yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba "ọ̀rọ̀ yi kún fún àwọn ìkòkò tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba "Ona meji ni Saraki ti n gbowo osu gẹgẹ bi SERAP ti sọ Awọn minista ati asofin wonyi jẹ awọn ti wọn ti figba kan ri jẹ gomina tẹ̀lẹ́ri ni ìpinlẹ̀ wọn, ti wọn si n gba owo ifeyinti pelu owo asofin lọ̀wọ̀lọ̀wọ̀. Adajọ Olurẹmi Oguntoyinbo ti ile ẹjọ giga ti ilu Eko lo se idajọ naa Siwaju si, SERAP n sọwipe ki wọn da owo to to aadota biliọnu pada si apo ijọba. Akpabio je okan lara awọn gomina tẹlẹri to n gbowo lọna meji Nigba to n gbe idajọ rẹ kalẹ, Adajọ Oguntoyinbo ni ""a ko lee ri ajọ SERAP bii alatojubọ ninu ọrọ yi, bẹẹ si lo lẹtọ lati pe ẹjọ, fi dawọ irufẹ igbese naa duro.",0,yoruba "fè lọ, A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..",0,yoruba "Ọdún - un 2018 ni ìfilọ́lẹ̀ CAX wáyé ní ibi Ìpàtẹ Ọjà Inú Ilẹ̀ - Adúláwọ̀ ní ìlúu Cairo , orílẹ̀ - èdèe Egypt , nínú oṣù Ọ̀pẹ̀ ọdún - un 2018 .",0,yoruba the english call it parrot yorùbá á ma pè é ní odídẹrẹ́ tàbí aiyé kòótọ́,0,yoruba oluwabukayo omo won ni iperu akesan baale oja omo felewa ogobiro te bafe wami wale ewa si agbo ile erugu #TweetinYoruba #TweetInYorubaDay,0,yoruba Lọ sí ojú-ìwé ilé,0,yoruba "Ó ní ìgbéyàwó láàárín akọ àti akọ tàbí abo àti abo si lòdì sí òfin lórílẹ̀-èdè Ghana. Ààrẹ Akufo-Addo sọ pé Òun kò ní sati lẹ́yìn òfin fún ìbálòpọ̀ láàárín akọ ṣákọ tàbí abo sábo lásìkò ìṣèjọba òun.Ààrẹ Akufo-Addo sọ̀rọ̀ yìí nínú àtejáde kan, Ó ní ìjọba òun ń kojú ìfúngunmọ́ láti sọ ìhà tí òun fì sí láti ìgbà tí Theresa May, olórí ilẹ̀ gẹ̀ẹ́sì tí gorí alefa.Ó ṣàlàyé pé May sọ pé àwọn yóò rán orile-ede lábẹ́ Commonwealth lọwọ láti fi ààyè gba ètò ìgbéyàwó ọkùnrin ṣókùnkùn àti obìnrin sobinrin nínú ìwé òfin orile-ede kòwá wọn tó setan láti fàyè gbà á. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àtẹ̀jáde ọ̀hún wáyé látàrí awuyewuye kan láti ọ̀dọ̀ àwọn alátakò pé ààrẹ Akufo tí fọwọ́ sì òfin náà lórílẹ̀èdè Ghana.Gẹ́gẹ́ bí ààrẹ ṣe sọ, mímú idagbasoke ba awon ara ìlú ni ó jé ìjọba lógún lásìkò yìí.Ó ní ìgbéyàwó láàárín akọ àti akọ tàbí abo àti abo si lòdì sí òfin lórílẹ̀-èdè Ghana.Akufo-Addo ni Ààrẹ ẹlẹ́keeta tí to sọ ní gbangba pé òun kò fọwọ́sí ibalopo ọkùnrin sí ọkùnrin tàbí obìnrin sí obìnrin.",0,yoruba Àwọn ènìyàn láti agbègbè náà máa ń pè é ní ‘tigress’ .,0,yoruba kí a ṣọ́ oúnjẹ tí à ńjẹ ní ìwọ̀ntúnìwòsì nǹkan dídùn dídùn ò yẹ adùn èso àti ọ̀gbìn ló dára,0,yoruba "Igbesẹ yii ko ṣẹyin abajade igbimọ iwaadi ti ile ẹkọ naa gbe kalẹ, lati ṣe iwaadi bi awọn akẹkọọ naa ṣe lu akẹgbẹ wọn kan nilegbe awọn akẹkọọ. Iṣẹlẹ naa waye lọjọ kẹrindinlogun oṣu Kọkanla ọdun 2019. Igbakeji oludari eto ibanisọrọ fasiti Futa, Adegbenro Adebanjo lo fi ikede yii sita ninu atẹjade kan ti ile ẹkọ naa fi sita. Gẹgẹ bi o ti ṣe sọ, wọn ni orukọ awọn akẹkọọ naa ni: Bakanna ni wọn ni lile tawọn le awọn akẹkọọ naa wa ni ibamu pẹlu ofin ileewe to la ijiya ''lile akẹkọọ kuro ti o ba lu akẹkọọ akẹgbẹ rẹ nibikibi ti kii ṣe ọgba ile ẹkọ'' Wọn ni lnitori eleyi, awọn akẹkọ to huwa aidaa naa ko le e jẹ anfaani kankan to tọ si awọn akẹkọọ fasiti naa mọ bayi. Ẹwẹ, fasiti FUTA tun sọ pe kii ṣe nitori pe awọn eeyan ke gbajare lori iwa awọn akẹkọọ to lu akẹgbẹ wọn naa, bi kii ṣe pe awọn tẹle ofin ti ile ẹkọ la kalẹ lori fifi iya jẹ ẹni ba tasẹ agẹrẹ sofin wọn.",0,yoruba Àkójú ọ̀rọ̀ yi kún fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde sí ara ilẹ̀. (Item 31),0,yoruba "Fére ~► asthma. Fèrè ~► flute, whistle. Fère ~► to sip. Fẹ̀rẹ̀ ~► early morning. #InYoruba",0,yoruba "Kọ́mú ni ilée ìkówópamọ́sí, àti owó t'ẹ́lẹ́ran ti fẹ jẹ̀ yí #Naira",0,yoruba sorosoro nimidakun ma je ki n fenu koto ri enu orofo lo n porofokenu temi ma se pami,0,yoruba "yorubá tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.",0,yoruba "Tani tabi Kini oke nla ti o do ju ko o bi iṣoro/idaamu/Apata ninu aye ati ẹbi rẹ, Olodumare yoo fi gbogbo wọn le ọ lọ wọ ni osù yii ni Orukọ Jesu. Iwọ yoo jẹ #StrongerThanYourEnemies3 nitõtọ. A ku Ayo Osu Titun. Happy New Month 💐 #GiveMeThisMountain #Yoruba https://t.co/YV98B0pjrv",0,yoruba "@user alayé mi Gbèngúlòó, ó tó'jọ́ mẹ́ta. A kú ìsinmi o!",0,yoruba RT @user: Bàtà orí àkìtàn náà re òde ìyàwó rí. / Those pair of shoes on the refuse dump was once worn to a wedding. [Change is i…,0,yoruba "A ti pa diẹ lara awọn imọran ti ẹyin naa fi sọwọ pẹlu ti wọn. Awọn imọran to le mu ki ẹ gbadun sise isẹ lati ile lasiko idejumọle to n lọ lọwọ lasiko konile-o-gbele yii Wo diẹ lara awọn aba ati ọna ti yoo jẹ ki ṣiṣe isẹ lati ile rọrun sii lasiko konile-o-gbele coronavirus yii: Sarah M, to n sisẹ nilu London ni oun ti wa ri wi pe didanikanwa jẹ nkan to maa n mu irẹwẹsi ba ọkan. O rọ awọn eeyan lati ma se fojudi anfani ibaraẹni sọrọ to ti wa tẹlẹ saaju ajakalẹ yi. Haralds Gabrans, a to wa lati orile-ede Latvia ni o nira fun oun lati gba pe bi nkan yoo ti se maa ri ree ati pe yoo to ọsẹ meloo kan ti o to dopin. Yatọ si gbogbo ipenija wọn yi, awọn kan ti sawari pe sise isẹ lati ile lasiko ajakalẹ yi si le jẹ ọna isẹ to sanfaani pupọ paapaa ti eeyan ba ni awọn isesi to daa ati ibalẹ ọkan ti yoo mu ki isẹ lọ deede. Fifi eto si iṣẹ ati ifaayesilẹ ṣe pataki: Ọpọ lo ti sọ fun wa pe awọn n sisẹ fun wakati to pọ tawọn ba wa nile ju ki awọn wa ni ibi isẹ lọ. Lalai si awọn alabasisẹ ti yoo tawọn lolobo pe asiko ti to lati lọ jẹun tabi ki wọn nasẹ diẹ, eeyan o kan maa sisẹ lọ bi aago ni. Aba tawọn eeyan muwa ni pe ki a fi eto si isẹ wa ki a si faaye kalẹ fun isinmi loore-koore. Angeliki (Pavlou) Heinz, da ọrọ to wa nilẹ yi bi ọgbọn. Ohun ati ọkọ rẹ a ma saaba pade ni ile idana wọn lasiko isinmi bi igba pe ibi isẹ ni wọn wa. Diana Wilson to jẹ ọga agba nile isẹ Tracemyfile ni ilẹ Gẹẹsi ni tiẹ sọ pe awọn ki fi asiko ounjẹ aarọ, ọsan tabi talẹ sẹre, koda bi isẹ ba pari tabi ti ko pari nile. Kí ni Yorùbá ń pe ọmọ tí wọ́n bí lẹ́yìn Àlàbá? Christina Brazzale, ni sise isẹ lati ile ko ni awọn nkan ti yoo ma dari ọkan kaakiri pupọ bi ki eeyan wa ni ibisẹ. O ni ''bayi ti mo wa nile, mi o ki n fi asiko ti maa rin jade lati gba oorun tabi atẹgun sara ṣere. O tẹsiwaju pe ""Bi mo ti se wa nile yi, o fun mi laanfaani lati mu asiko isinmi mi ni koko yatọ si ti mo ba wa ni ibisẹ'' Bakan naa wiwa nile a maa mu ki awọn eeyan mi maa sare lati pari isẹ ti wọn n se, awọn eleyi ti wọn yan fun ara wọn ati isẹ ile lẹẹkan naa. Child Labour: Fífi ọmọ ṣòwò wọ́pọ̀ ní Naijiria Imọran ti Hannah Allyse Kim ati awọn mi mu wa ni pe ,ma se ju ara rẹ lọ. Sebi-o-timọ bi ẹlẹwa sapọn. Asaretete ko ni kọja ile bẹẹ ni aringbere ko ni sun sọna ni imọran pe ki onikaluku ṣe iṣẹ niwọnb ko si maa dide. Wọn kadi imọran yi pe ki a ri pe a ni eto ati ilana ta fẹ fi se isẹ wa lojojumọ. Eleyi ko ni mu ki a kan maa daamu ara wa lasan. Wa ọna orisi lati fi ṣe iṣẹ rẹ: Fun ọpọ eeyan nise ni ọjọ yoo dabi ẹni pe ko fẹ tan. Irẹwẹsi ọkan ti n mu ki gbogbo ọjọ ri bakan naa loju wọn. Imọran ti wọn le fi koju eleyi tawọn eeyan mu wa ni pe ''ẹ sisẹ nibi ti atẹgun yoo ti maa fẹ si yin daadaa. Bi o ba ṣe pe ki ẹ tẹni si abẹ igi ni tabi ki ẹ duro ni faranda yin, eyi ko ni mu ki isẹ tete su u yin. Anastasia Balandina lati London ni balikoni oun loun ti maa n sisẹ ti oorun ba ti jade. O ni o maa n tu oun lara gan an ni Huda Shaarawi: Kò dára kí obìnrin sè’yàwó lọ́mọ ọdún mẹ́tàlá Yatọ si eleyi, ọna miran ti a le fi gbadun sise isẹ wa lati ile ni pe ki a wa awọn ere ti awa ati awọn mọlẹbi wa yoo jijọ maa se. Bi o ba se wi pe ki ẹ jijọ maa se bojuboju tabi sise ipade ranpẹ lori oun tẹ ẹ fẹ se ni ojumọ kọọkan lẹ ba yan laayo, ko si ọna ti ẹ yan ti ko ni jẹ ki ẹ gbadun isẹ yin lati ile. E ma jẹ ki o yọ awọn ọmọ yin silẹ: Awọn to ba n sisẹ lati ile ti awọn ọmọ wọn wa lọdọ wọn a maa ronu bi awọn yoo ti se sisẹ pẹlu wahala itọju ile. Imọran ti ọpọ fi sọwọ ni pe ki eeyan wa nkan ti awọn ọmọ yoo ma se lasiko ti eeyan ba n se isẹ rẹ bi ki wọn ma tun ile se,sise ere idaraya tabi ki lọkọlaya ma bawọn sere laarin ara wọn. Emma Cantril, to jẹ oludasilẹ ileesẹ Intelligent Profile ni ilẹ Gẹẹsi ni oun ti ni isẹ toun ya sọtọ fawọn ọmọ oun lojojumọ. Lati igba ti mo ti n sisẹ lati ile bi nkan bi ogun ọdun sẹyin ipenija ti o lagbara ti mo le tọka si ni pe bi maa ti se yanju asọ fifọ, ina dida, ile titunsẹ ki n si tun lee se isẹ mi pẹlu ifọkanbalẹ. O ni ki wahala naa ma baa le fẹ se oun lese, oun a maa ri pe onikaluku lo ni isẹ tiẹ ti yoo ṣe lojumọ. O ni bi bẹẹ kọ, eeyan ko ni le se gbogbo rẹ pọ pẹlu asiko perete to wa nilẹ. Bẹẹ lọrọ ri lọdọ ọgbẹni Jonathan Wareham lati Italy ti isede ka oun, iyawo rẹ ati awọn ọmọ mẹta mọle. O ni yiyan isẹ fun onikaluku se pataki bẹẹ si ni o yẹ ki eeyan maa nasẹ sita lẹẹkọọkan naa se pataki. ''Sisọ otitọ fun ara rẹ ati awọn ọmọ rẹ nipa oun to n sẹlẹ se pataki'' Sport Betting: Idí rèé tí àwọn ọ̀dọ́ kan fi n ta tẹ́tẹ́... Ma se bọkan jẹ ninu gbogbo wahala idejumọle to wa nita yi, awọn to fi imọran sọwọ siwa ni ki a gba kamu ka si ma se ba ara wa lọkan jẹ. Wareham ni lati ilẹ lo ti yẹ ki ọkan eeyan gba kamu ohun to delẹ ki o si ri i gẹgẹ bii ''asiko ti eeyan yoo mu idagbasoke ba ara rẹ ati mọlẹbi rẹ.'' O ni bi oun ati mọlẹbi oun ti se bẹrẹ si ni gbe igbe aye wiwapọ pẹlu ara wọn yi, oun ti se awari awọn kudiẹ-kudiẹ to wa ninu iwa oun ti oun si ti n se atunse. O ni ki awọn eeyan gbiyanju lati gbadun aise nkankan yi ki wọn si gba pe gbogbo nkan ni yoo yi pada bọ sipo to ba ya. Ni pataki, o ni ki a ma gbagbe pe mọlẹbi wa se pataki pupọ. O ni ki a ri asiko idejumọle yi bi eleyi ti a o fi jẹ ki irẹpọ tubọ rinlẹ ninu mọlẹbi wa. O sọ pe ki a ma gbagbe pe itan manigbagbe ni a n fi lelẹ lasiko yi eleyi ti ko ni si ẹni ti yoo gbagbe rẹ ninu mọlẹbi wa.",0,yoruba "tí Ọba fè joko, Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.",0,yoruba "ÀSÌKÒ ÒWE Ẹnú dùn r'òfọ́, agada ọwọ́ ṣe é bẹ́ gẹdú. TRANSLATION: It is easy to cook a vegetable soup with with the mere words of mouth, the bare hand can cut down a timber. BREAKDOWN: It is easy to exaggerate. ÌTÚPALẸ̀: Àsọdùn rọrùn",0,yoruba RT @user: #Ibeere: Daruko ''OKE'' (Mountain) mesan ti o wa ni ilu Ibadan ti e mo. Cc @user @user @user @user omoi…,0,yoruba "Ìbàdàn. Nitori eyi, ara eni lo ni ìgbà mi owó àkokò, Ọmọ lo tun se lọ.",0,yoruba "Oludije lẹgbẹ oṣelu APC fun ipo aarẹ, Asiwaju Bola Ahmed Tinubu ti sọ pe oun ni ibọwọ to peye fun ẹsin mejeeji to tobi julọ ti wọn n ṣe lorilẹede Naijiria. Ahmed Tinubu sọ eyi lẹyin to yan gomina ipinlẹ Borno tẹlẹ, Kashim Shettima gẹgẹ bi igbakeji oludije lẹgbẹ oṣelu APC. O ni yiyan ti oun yan an ko nii ṣe pẹlu pe oun ko bọwọ fun ẹsin Kristẹni, nitori oun bọwọ fun ẹsin naa ti oun ko si fi ọwọ rọọ si ẹyin. Bakan naa lo ni oun gbọ gbogbo ẹdun ọkan awọn ti ko lọwọ si yiyan ẹlẹsin musulumi gẹgẹ bi igbakeji amọ o ni ilọsiwaju orilẹede Niajiria lo pọn dandan. ‘’Gbogbo ẹyin ti inu yin ko dun si ẹni ti mo yan nitori ẹsin, ẹma binu amọ kii ṣe pe mi o kọ ibi ara si ẹsin Kristẹni.’’ ‘’Mi o ni lailai tabuku ẹsin kankan ni Naijiria nitori mọ mọ bi o ṣe ri lara awọn ọmọ Naijiria’’ ‘’Mo si fi iye si gbogbo ẹdun ọkan awọn ẹniyan lori yiyan ti mo yan igbakeji.’’ Amọ Tinubu ni ko gbọdọ maa lọ lailai ki oun gbogbo ti ijọba ba fẹ ṣe gbọdọ jẹ nipa ẹsin tabi ẹya. O ni ipenija orilẹede Niajiria lọwọlọwọ n beere fun ki awọn eniyan fi ọkan si ẹni to ba pegede ju ọrọ ẹsin lọ. Tinubu ni awọn ọmọ Naijiria gbọdọ bẹrẹ si ni fi oju si ẹni ti yoo mu idagbasoke ati aṣeyọri ba orilẹede Naijiria, kii ṣe ọrọ ẹsin. Oludije sipo Aarẹ ninu ẹgbẹ oṣelu APC, Bola Ahmed Tinubu, ti kede sẹnetọ Kashim Shetima, gẹgẹ bii igbakeji rẹ ti wọn yo jọ dije. Tinubu lo fi ikede yii sita lasiko to n ba awọn akọroyin sọrọ niluu Daura, tii ṣe ilu Aarẹ Muhammadu Buhari. Shetima ni gomina ipinlẹ Borno laarin ọdun 2011 si 2019. Ṣaaju ni Tinubu ti kọkọ ṣe ipade pẹlu Aarẹ Muhammadu Buhari ninu ile rẹ naa ni Daura fun nnkan bii wakati kan ko to jade lati fi ikede ọhun sita. Gẹgẹ bii ohun ti Tinubu sọ, o yan Shettima  nitori o jẹ ẹnikan to jafafa, to ṣe fọkan tan, ati ẹni to mọ ohun to n ṣe. Lara awọn to ba Tinubu lọ si Daura ni Gomina Aminu Masari lẹyin ti ọkọ ofurufu to gbe Tinubu balẹ si papakọ ofurufu ti Umaru Musa Yar’Adua ni Katsina. Nigba ti so n sọrọ lori ikede naa, minisita eto igbanisiṣẹ, Festus Keyamo, juwe Kashim Shettima gẹgẹ bii ẹni to tọ fun Tinubu lati yan gẹgẹ bii igbakeji rẹ. Ninu atẹjade kan to fi soju opo Twitter rẹ, Keyamo sọ pe Tinubu ko ṣe aṣiṣẹ nipa yiyan Shettima. O ni “Oṣiṣẹ ile ifowopamọsi to dantọ ati onimọ nipa eto ọrọ aje to ṣe mu yangan” ni Shettima. “Shettima gan ni ẹni to tọ fun Tinubu lati yan gẹgẹ bii igbakeji rẹ.” Ẹwẹ, ẹni ti wọn kọkọ yan lati ṣe igbakeji Tinubu, Ibrahim Masari ti ni oun ko ṣe mọ. Ninu atẹjade kan to fi ṣọwọ si awọn akọroyin lọjọ Aiku, o ni lẹyin ijiroro pẹlu awọn ti ọrọ kan, oun ti jawọ ipo igbakeji naa. Lẹyin naa lo gbadura ki Ọlọrun jẹ ki ipo Aarẹ ti Tinubu n du bọ si lọwọ gẹgẹ bii ero ọkan rẹ.",0,yoruba Cyrillic/Ukrainian (Mac_Ukrainian),0,yoruba ọ̀ràn ► matter trouble issue wúrà ló dá ọ̀ràn sílẹ̀ = wúrà is the cause of the matter is gold,0,yoruba Ìyá joko. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "Lasiko ijoko ile to waye lọjọru ni Lawan kede igbesẹ yii. Aarẹ ile asofin agba salaye pe, ijọba apapọ n sisẹ kara lori akọsilẹ orukọ awọn eeyan to fẹ gba ipo minisita naa lọna ati ri daju pe awọn eeyan ti musemuse wọn da musemuse ni wọn yan lati sisẹ sin orilẹede yii. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: O ti le ni osu kan bayii ti aarẹ Buhari ti sebura fun saa keji sugbọn ti ko ti kede awọn minisita ti yoo wa ninu ijọba rẹ. Eyi si lo mu ki Senetọ Bassey Akpan fi pe akiyesi awọn akẹẹgbẹ rẹ lasiko ijoko ile naa pe, isẹlẹ ọhun se apakan jamọ, nitori pe awọn asofin naa yoo lọ fun isinmi olosu meji laipẹ. Akpan ni bi aarẹ se fi iyansipo awọn minisita naa falẹ yoo se akoba fun eto ayẹwo ati fifi ontẹ lu wọn, eyi ti ile asofin agba fẹ se fun wọn. Nigba to n fesi lori akiyesi yii, Lawan fọwọ sọya fawọn akẹẹgbẹ rẹ atawọn ọmọ Naijiria pe, aarẹ Buhari ko ni pẹ fi orukọ naa sọwọ, eyiun ki ọsẹ yii to pari. O ni ti awọn asofin agba naa yoo si se ayẹwo fun awọn to fẹ gba ipo minisita ọhun, ko to di pe wọn lọ fun isinmi olosu meji eyiti yoo bẹrẹ lọjọ Kẹrindinlọgbọn osu Keje taa wa yii.",0,yoruba "Nínú àkọsílẹ̀, Aláàfin Ọròmpọ̀tò ló ní ọmọ ogun julọ; jagunjagun orí ẹṣin ẹgbẹ̀rún (1000). #OgunIleYoruba #Oyo #Yoruba",0,yoruba "Àjọ kan tí kìí ṣe ti ìjọba, Oxfam International ti kéde pé, ó ṣee ṣe kí ikú tó jọ́ mọ́ ebi lú ènìyàn ẹgbẹ̀run méjìlá pa lọ́joojúmọ́ lẹ́yìn ti àrùn Colvid-19 bá kásẹ nílẹ̀. Wọn ni èyí yóò sì fẹ́ẹ̀ ju iye ènìyàn ti àrùn Covid-19 pa lójoojúmọ́ lọ. Lásìkò tí àjọ náà ń pe ìpàdé akọròyìn ló sàlàyé pé nígbà ti yóò fi di òpín ọdún yìí ènìyàn ẹgbẹ̀rún méjílà léé maa kú lóòjọ́, Eyí ju iye ènìyàn ti Coronavirus ń pa lójúmọ̀ lọ lati ìgbà ti ọ ti di rànto nínú oṣù kérin ọdún yìí. Àjọ náà sàlàyé pé ènìyàn mílíọnù mọ́kànlélọ́gọ́fà ní ó ṣeéṣe kí àrùn yìí tì sínú ìṣẹ́ àti òsì, àiníṣẹ́ àti àìsí ounjẹ, tó fi mọ́ aisi ìpèsè àwọn ǹkan tí ènìyàn fí ń gbé ìgbé ayé ojoojúmọ́. Adarí àgbà ilé iṣẹ́ náà, Chema Vera ní ""àrùn Covid-19 ni pabanbarì iṣẹ́ nitóri pé mílíọ́nù àwọn ènìyàn ti ń tiraka láti la àsìkò yìí já tẹ́lẹ̀"". O ni pe: oníruurú àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tó n bá àsìkò yìí rìn lo pọ. Ati pe ijà (ikọlu, ogun), àyípada ojú ọjọ́, àìdọ́gbà láwùjọ àti bí ètò òunjẹ ṣe dí èyí ti kò tóó pín naa fẹ apero. Eyi kò si ṣẹyin bi àwọn ilé iṣẹ́ tó n pèsè òunjẹ kò ṣe lágbára mọ. Alaye lori awọn to ri ṣe lasiko Covid 19: Ajo Oxfam ni: Síbẹ̀ àwọn tó wà nípò gíga àti ipò òṣèlú ṣì ń lówó sii. Ati pe àwọn ilé iṣẹ́ tó ń pèsè òunjé àti òhun mímu fún àwọn tó ní ipín ìdókòwò pẹ̀lú wọ́n ní bílíọ̀nù méjìdínlógun nínú oṣù kíní ọdún yìí, Ajọ yii ni pe èyí ju ìlópo mẹwàá iye ti àjọ ìsọ̀kan àgbáye sọ pé àwọn nílò láti kó ẹbi àti òsì kúrò lágbàyé"" Chema Vera ni: ""Kódà àwọn orílẹ̀-èdè ti wọ́n ti gbọ́njú dáadaa bi South Africa, India àti Brazil, ló ṣeẹṣe kí orílẹ̀-èdè wọ́n di olú ilú ebi. Ni ipari, ajọ OXFAM rọ àwọn ìjọba láti sa ipa wọ́n gidi kí wọ́n kásẹ̀ àrùn Covid-19 kúrò nilẹ̀, Bákan náà ni wọn ni pe ki ijọba tètè kó ọ̀rọ̀ ebi àti ìṣẹ́ kúrò nilẹ̀ kí ikú tó ní i ṣe pẹ̀lú ebi máa baa gbòde kan lẹ́yìn ti Covid-19 bá kásẹ̀ nílẹ̀.",0,yoruba "RT @user: """"""""""""""""@user: """"""""""""""""@user: Ojúmọ́ ire o. Ayọ̀ àti ìfọ̀kànbalẹ̀ ni fún gbogbo wa lọ́jọ́ òní.""""""""""""""""Ojúmọ́ 're ni o #ekaaaro"""""""""""""""" Amin. O…",0,yoruba "Lara awọn laasigbo naa la ti ri Black lives matter ati ENSARS amọ sibẹ sibẹ, ko ṣai si awọn asiko tabi idi diẹdiẹ fun idaraya ati idaraẹni ninu dun ninu ọdun yii. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Lara awọn idaraya to waye lọdun 2020 lawọn aṣayan aṣa to gbode laarin rẹ, eleyi to mu ẹrin ati ipenija dani, bẹẹ ni awọn miran mu ijigiri dani pẹlu. Ẹ jẹ ka mu diẹ lara awọn aṣa wọnyii ni ṣisẹ n tẹle: Mummy Calm down: Hmmm, bi eniyan ba wo bi aṣa yii ṣe bẹrẹ, bi ẹrin bi ere naa ni. Ọmọdekunrin kan Ooreoluwa, ni iya rẹ n ba wi fun aigbọran to hu, amọ ṣa nibi ti ọmọ naa ti n gbiyanju ati bẹẹ iya rẹ, lo ti n pariwo ""Mummy calm down"". Iya rẹ lo ya fidio ẹbẹ rẹ yii, to si fi ransẹ si ẹgbọn rẹ lati jẹ ko mọ iru alawada ti Ooreoluwa jẹ. Ẹgbọn iya rẹ naa si lo gbe fọnran aworan ọhun sori ayelujara eleyi to tan kaakiri agbaye, to fi sọ ọmọdekunrin naa di ilumọọka, koda, gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu gan kan si ọmọdekunrin naa. Lati igba naa ni ""Mummy calm down"" ti di aṣa to gbajugbaja. Koda awọn oloṣelu lo o fun ipolongo ibo, bẹẹ ni awọn ileeṣẹ kaakiri lo aṣa naa fun ipolowo ọja ati itaniji paapaa lasiko ti ajakalẹ arun COVID-19 gbalẹ kan. ""Sọrọ soke were, maa disguise"": Ara awọn aṣa to milẹ lasiko iwọde #EndSARS niyi. Koda, asa naa lo di ọrọ akọmọna fun awọn oluwọde to n pe fun iwọgile ikọ ọlpaa SARS naa kaakiri orilẹede Naijiria ati loke okun nigba naa. Gbogbo oluwọde, koda awọn ti ko gbọ ede Yoruba, gan pẹlu n pariwo sọrọ soke' nigba ti iwọde ọhun fọnna soju to bẹẹ gẹẹ, to si wa di ohun apejuwe fun iran ọdọ iwoyii. Ọrọ akọmọna naa, eyi to n se iwuri fun awọn ọdọ lati mase dakẹ tabi panumọ lori iwakiwa lo mu ki wọn maa pe iran iwoyi ni ""Sọrọsoke generation"" bayii. Kwarantain tabi Qurantine lede oyinbo: Aṣa yii jade lasiko ti ajakalẹ aarun COVID-19 wọ orilẹede Naijiria, ti ijọba si n ko awọn to ba ṣẹṣẹ ti ilẹ okeere de pamọ si igbele, eleyii ti wọn n pe ni Qurantine lede Gẹẹsi. Ẹ jẹri awọn ọmọ Naijiria, ko pẹ pupọ ti wọn fi gba eyi gẹgẹ bi aṣa lati maa lo fun ẹni ti wọn ba fẹ pa ti si ẹgbẹ kan. Fun apẹẹrẹ wọn lee ni, ""Mo ma ti Kwarantain (qurantine) ọrọ yẹn. Ma ko paliatifu (Palliative) mi: Lara awọn aṣa to gba ibi ajakalẹ arun COVID-19 lorilẹede Naijiria yọ naa leyii, bi o tilẹ jẹ wi pe lẹyin ti ọwọ kini ajakalẹ arun naa ti n rọlẹ lo waye. Bakan naa lo tun nii ṣe pẹlu iwọde #EndSARS to waye loṣu kẹwaa ọdun 2020. ""Palliative' lawọn ohun arẹmọlẹkun ti awọn ileeṣẹ aladani pa owo pọ ra fun mimu aye dẹrun diẹ fun araalu lasiko igbele COVID-19 nigba naa. Amọṣa, lasiko ti iwọde #EndSARS gba ibomiran yọ, tawọn janduku ja a gba mọ awọn to ṣeto rẹ lọwọ, lawọn eeyan fi bẹrẹ si ni ja awọn ile ikẹrusi kaakiri nigba naa. Eyi lo mu ki aṣa yii jẹyọ pe ""Ma ko Palliative mi"" O tumọ si ma ko mi ni nnkan lọ. Fun apẹrẹ, ""Alaye ko fi ọgbọn ko paliative mi jọọ."" We move: Lasiko iwọde #EndSARS ni eyi jẹyọ. Lasiko ti iwọde naa ṣi n lọ ni irọwọrọsẹ, ti awọn oluwọde n bẹ awọn ile ijọba wo lati fi ẹhonu wọn han si aye familete n tutọ awọn ọlọpaa kogberegbe SARS. Asiko naa si ni awọn ọdọ to n sewọde maa n pariwo ""We move"" ti wọn ba ti fẹ kuro ni ibudo kan si ikeji. Amọ ṣa, lẹyin iwọde yii lawọn eeyan kuku sọ ọ di aṣa, ti aṣa ""We move"" fi gberassọ titi de aarin awọn ọmọ Naijiria to wa loke okun pẹlu. Mad o: Eyi tun ni aṣa miran to gbaye kan lọdun 2020 yii, aṣa yii si jẹ ọrọ iyanu. Asiko ti wọn maa n lo aṣa yii ni igba ti nnkan iyanu ba ṣẹlẹ, ti awọn eeyan lee ṣe haa si. Dipo ki wọn pariwo haa, ni wọn a maa pariwo ""mad o"". Diẹ lara awọn aṣa to la'lẹ hu jade lọdun 2020 ree, ewo lẹyin mọ ti ẹ lee fi kun un?",0,yoruba """N kò le wo dígí torí bí àrùn ‘scleroderma’ tó ba ẹwà mi jẹ́""",0,yoruba èdùmàrè gbére ajé olókun kò mí lóòwúrọ̀ tòní owó tabua àbùbùtán owó tútù tí í dẹ́rù ba àgbàná ni kí o fi ṣe tèmi,0,yoruba "se se. Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba Anthony Joshua: AJ ní òun ṣetán láti bá Tyson Fury jà lẹ́yìn tí Usyk fìyà jẹ ẹ́,0,yoruba "Láìpẹ yìí ni ìròyìn tàn ká pé àwọn ọmọ ikọ Super Eagles n bínu pé afi dandan ki awọn aláṣẹ san owo ajẹmọnu awọn, ti wọ́n si dún koko pe ó ṣeeṣe ki awọn ma lọ si ibi ipade apero kan ti yoo sáju ifẹsẹwọnsẹ wọ́n pẹ̀lú Guinea láàná. Sùgbọ̀n ẹyìn-ò-rẹ́yìn ìfẹsẹwọ́nsẹ Super Eagles pẹ̀lú Guinea eyí ti wọ̀n gbá àmi ayò kan si odo lẹ́yìn ti wọ́n sọ ọ̀pọ́ ànfani nu lóri pápá. Nínú ìwádìí BBC láti mọ bóya àwọn ikọ̀ agbábọọlù Super Eagles ti gba owó ajẹmọnú wọ́n, BBC ò le fìdí ọ̀rọ̀ múlẹ̀ bóyá wọ́n ti rí àwọn ajẹmọnu náà gbà sùgbọ́n àwọn ayọlo ti wọ́n sọ ko jẹ ki a le sọ pato ibi ti ọ̀rọ̀ dé. Sùgbọ́n ó jọ bi ẹni pe wọ́n ti ṣe ileri fún wọ́n pé wọ́n o rówó gbà ni ọjọ ẹtì ọ̀la yìí. Ola Aina tó ń gbá fún ẹyìn apá òsì "" Asoju awa ikọ Super Eagles ati igbákeji rl pè wá jọ, wan si ni e wó ẹ tẹti, sááju oun gbogbo isẹ́ ni awá ṣe nibi, iṣk ki a gbá bọ́ọ̀lù si ni, ẹ jẹ́ ki a ṣe ǹkan to yẹ ki a ṣe láti sojú orílẹ̀-èdè wa, láti sóju ara wa àti awọn ẹbi wa, sááju ohun gbogbo a ni iṣẹ́ láti ṣe ǹkan to gbé wa wá sibi nìyìí, ẹ jẹ ki a gbá bọọ́lù ki a si mú èsì gidi jáde. Nínú ọ̀rọ̀ tirẹ̀ Akọnumọọgba wọ́n Gernot Rohr"" Ọ̀rọ̀ mí si àwọn olólùfẹ ikọ super Eagles ni pe ki jẹ ki awọn ọmọ agbábọọlu Nàìjíría ma wú wọ́n lóri, nítori wọ́n n sapa wọ̀n láti gbe ogo fún Nàìjíríà nínú ìdíje AFCON. wan fi ifẹ han nípa idije yìí ati àwọn ǹkan míran náà, eyi si jẹ iwúri fún gbogbo wa. John Mikel obi ní iṣẹ́ to pọ̀ láti ṣe nínú ìdíje tó lọ lọ́wọ́ yìí, ó ṣe wáhala púpọ̀ láàná nítori ó ba àwọn ìjọba sọ̀rọ̀ sùgbọ́n àwọn ọmọ ikọ rẹ̀ ló ṣe fún. Ní ti Alex Iwobi o ní "" ẹ jẹ́ ki a fí iyẹn sí ẹ̀gbẹ́ kan (ọ̀rọ̀ lóri owó ajẹmọnu tó n dá wàhálà sílẹ̀)láàrin ara wa, sùgban ǹkan to ṣẹlẹ̀ ni pe ǹkan ti a ba ṣe lóri pápá lo ṣe pàtàkì jù, kó si ǹkan ti yóò gbe oju wa kúro láti ṣe aṣe ọri, inú gbogbo wá lo dùn",0,yoruba "Obasanjọ ni ko jẹ ki Atiku wolé ààrẹ Lára ǹkan ti wọn ń mú gbọ́ náà ni kíní ìdi gan ti ó mú Atiku fìdírẹ̀mi? Ilé ìṣẹ́ BBC Yorùbá ṣe àkójọpọ̀ ǹkan Márun ti ó mú Atiku Abubakar fìdírẹmi nínú ìdìbò ọdún 2019 Àwọn abawọn òhun gẹ́gẹ́ bó ṣe sọ wá láti ẹnu Ààrẹ Olusegun Obasanjọ ti wọn ti jọ ṣe ìjọba fún ọdun mẹ́jọ, ó fi kún pé àwọn ǹkan tó sọ nípa Atiku ní àwọn ènìyàn gbàgba pé ó jẹ òtitọ nítori pe wọn gbàgba pé ó mọ̀ọ́ dárádára Obasanjo fi kún pé Atiku kò ṣe gbara lé àti pé ajinilẹ́sẹ̀ ni Atiku lásiko ti àwọn jọ ṣe ijoba. O fí kún pé Atiku ò fi ìgbà kankan janpata pé ìrọ ni obasanjo pa mọ oun àbi pé òun yóò gbe lọ sí ilé Ejọ Obasanjo fi kún pé Atiku kò ṣe gbara lé àti pé ajinilẹ́sẹ̀ ni Atiku lásiko ti àwọn jọ ṣe ijoba. Ọjọ̀gbọ̀n Dikirullai sàlàyé pé àwọn ètò ti ààrẹ Buhari ti ń gbé kalẹ tẹ́lẹ̀ wà fún àwọn tálákà tó ń dibò jùlọ lórilẹ̀-èdè yìí. O fíkun pé àṣẹ tí ààrẹ Muhammadu Buhari pa pé ki wọn pa ẹni ti ó ba ji apoti ìdìbo kún oun to jẹ ìbẹ̀ru fun àwọn ara ilú ti wọn o fi jáde lọ dibo. O ni ẹru wi pe wọn le yinbọn ti yoo si ba alaiṣeẹ kún ìdí ti wọn ko fi jáde",0,yoruba Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó ṣe pàtàkì. (Item 41),0,yoruba ẹ̀rínkẹ́rìnín ni asínwín ń rín ìdìkudì ni wèrè ń di ẹrùu tirẹ̀ ìwọ làkáṣègbé máa rẹ́rìnínkẹ́rìnín ìwọ tàmẹ̀dù máa dìdìkudì ẹrù kiri ewì òkè yìí jẹ́ àpẹẹrẹ irú ewì alohùn wo a oríkì b èṣù pípè d ọfọ̀,0,yoruba "Orisiirisi igbeyawo lo wa laye atijo ati laye ode oni. Awon igbesẹ kọọkan pa awọn mejeeji papọ ni eyi ti iran Yoruba fi nilo ọkunrin ati obinrin. Bẹẹ ọmọ ti aye bi ni aye n pọn. Ọpọ igbeyawo ni o ti lu ori ayelujara pa ti awọn eeyan si n sọrọ nipa wọn. Akojopọ marun un nibẹ ni BBC ṣa jọ ti o jẹ igbeyawo laarin awọn oju oge Yollywood. Wo àwọn ìgbéyàwó tí ayé pariwo wọ́n nigba ti wọn waye laipẹ: 1. Lateef Adedimeji & Mo'Bimpe Igbeyawo laarin oṣere Yoruba meji ti ololufẹ wọn si n pariwo kiri lori ayelujara pe eyi gọntiọ. Awọn naa ni Oladimeji Abdulateef ati Adebimpe Oyebade. Ojọ kejilelogun, oṣu kejila, iyẹn oṣu to kọja ni igbeyawo naa waye. Die lara awọn to peju pesẹ sibi igbeyawo Lateef ati Mo Bimpe naa ni awọn oṣere bii: Toyin Abraham, Kolawole Adeyemi, Nkechi Blessing Sunday, Mercy Aigbe, Adunni Ade, Wumi Toriola, Femi Adebayo, Yetunde Bakare, Odunlade Adekola ati awọn mii. Ọpọlọpọ eto nipa igbeyawo naa lo kun ori ayelujara. 2. Toyin Lawani & Segun Wealth: Lọjọ kejila, oṣu kẹfa ọdun to lọ ni ọjọ malegbagbe ninu aye akọṣẹmọṣẹ yeye oge arẹwa ni, Toyin Lawani ati ololufẹ rẹ Segun Wealth. Ipinlẹ Eko ni igbeyawo naa ti waye nibi ti awọn eekan ilu ti wa sibẹ. Ọ̀pọ̀ awọn ololufẹ rẹ to jẹ gbajumọ lawujo ti wọn fi iwe pe lo peju pese sibi ayẹyẹ naa. Oriṣiirisi aworan lo lu ayelujara pa lasiko igbeyawo Toyin Lawani ati Segun Wealth ti aye fi n pariwo. 3. Yetunde Barnabas & Peter Olayinka Oserebinrin ni Yetunde Barnabas lo gab oruka lọwọ ololufẹ nibi isopọ wọn loṣu kẹfa ọdun to lọ. Bayii won ti pe oṣe mẹfa ninu igbeyawo. Yetunde ati gbajugbaja agbabọọlu ikọ Super Eagles ni, Olayinka Peter ni won jọ di tọkọtaya. Ọpọ oju awọn elere idaraya paapaa awọn agbabọọlu lo kun inawo naa pẹlu awon osere lọkunrin ati lobinrin. Iroyin ni ọdun meji ni wọn fi kọkọ fẹ ara wọn sọna ṣaaju igbeyawo naa. 4. Wolii Arole ati Yemi: Igbeywao alarinrin waye larin gbajugbaja adẹrin poṣonu omọ Ogbomoso nii ti ọpọ n pe ni Wolii Arole. Toyin Balogun lo gbe ololufẹ rẹ Yemi ni iyawo lọjọ kẹwaa, oṣu kẹrin, lọdun to kọja. Ojọ naa jẹ ara ọtọ fun Wolii Arole ati Yemi to dun debi wi pe o gba ọkọ ayọkẹlẹ gẹgẹ bii ẹbun igbeyawo lọjọ naa. Won ṣe idana pẹlu igbeyawo alarede nile ijọsin ni. 5. Cute Abiola ati Oloufe re, Kudirat Mosunmola: Aderinpoṣonu ti o gbajumọ pupọ lori ayelujara Instagram ni, Cute Abiola naa ti ṣe igbeyawo. Cute Abiola to tun jẹ ọmọ ogun ori omi ni Naijiria naa fẹ ololufẹ rẹ ni ilu Ogbomoso ni ipinlẹ Oyo lọọ ẹti, ọjọ kejidinlọgbọn, oṣu karun un lọdun to kọja.",0,yoruba "Yoruba bọ, wọn ni alara nii gb'ara ga, bi adiẹ ba fẹ wọle, a bẹrẹ. Bi ayẹyẹ ọdun mọkanlelọgọta ti orilẹede Naijiria gba ominira ṣe ku ọjọ kan, Aarẹ Muhammadu Buhari yoo ṣe ifilọlẹ iwe kan to sọ nipa ẹwa, awọn ibi irinajo afẹ ati ohun manigbagbe ninu itan Naijiria. Oludamọran fun aarẹ lori ọrọ iroyin, Femi Adesina to fi ọrọ yii lede ṣalaye pe akọwe iwe naa ni ''DISCOVER NIGERIA'' eleyi to tumọ si ṣe awari Naijiria. Adesina ni ayafọto aarẹ Buhari, Bayo Omoboriowo, lo kọ iwe naa eyi to sọ nipa irinajo Naijiria lati igba ominira titi di akoko yii. Iwe naa to ni ewe to din mẹjọ ni irinwo(392) lawọn eeyan ti sọ pe yoo wa lara awọn to lamilaaka julọ ninu lagbaaye. Iwe yii sọ nipa awọn ọba alaye, oriṣiiriṣii ẹya, ilẹ oko Naijiria ati okun ti Eledua fi jinki Naijiria. Omoboriowo ṣalaye pe iwe naa wa lara awọn eto lati fi ṣe ayẹyẹ ọgọta ọdun ominira orilẹede Naijiria. Yàtọ̀ sí ọkọ Dora Akunyili, wo àwọn ibòmìí tí wọ́n tún ti pààyàn ní Anambra lọ́jọ́ kan nàá Kí ló mú kí agbẹjọ́rò àgbà yọ ọwọ́ nínú ìgbẹ́jọ́ Dibu Ojerinde ọgá JAMB tẹ́lẹ̀? Àwọn Oba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí Oba míràn jẹ lójú ayé wọn Awọn ọdọ to le lọgọta ni wọn ṣiṣẹ pọ pẹlu Omoboriowo lori ati kọ iwe naa. Ayẹyẹ ifilọlẹ iwe ọhun nile iṣẹ ijọba l'Abuja yoo tun ṣe afihan oriṣiiriṣii iṣẹ ọna lati ẹkun idibo mẹfa to wa ni Naijiria. Koda oriṣiiriṣii ounjẹ awọn ẹya to wa ni Naijiria naa ko ni gbẹyin nibi ayẹyẹ ọhun. Olori orilẹede Naijiria tẹlẹ. ajagun fẹhinti, Abdulsalami Abubakar, lo kọ ọrọ iṣaaju fun iwe naa. Minisita eto iroyin ati ọrọ aṣa, Lai Mohammed lo kọ ọrọ ifihan fun iwe ọhun. Koda, olori ologun Naijiria to tun jẹ aarẹ ologun orilẹede Naijiria tẹlẹ ri, Ibrahim Babangida naa ti ka iwe ọhun ti o si gboṣuba rabandẹ fawọn onkọwe Omoboriowo atawọn to ṣiṣẹ pọ pẹlu rẹ.",0,yoruba "Ninu atẹjade kan ni ijọba Kano ti fẹsun kan Sanusi pe, ko bọwọ fun ofin ati awọn ilana kan, lo jẹ ki wọn fi ọwọ osi juwe ile fun un. Eyii ni awọn ohun meje to yẹ ki ẹ mọ nipa Emir ana ọhun. 1. O man n sọ eroungba rẹ lai woju ẹnikẹni Muhammadu Sanusi jẹ ẹni kan ti kii bẹru ati sọ ohun to ba wa ninu ọkan rẹ fun ijọba lai bikita ohun to le tẹyin rẹ jade. Ko to gori oye Emir, Sanusi ma n sọrọ pẹlu igboya lori ọrọ iṣejọba ati ọrọ aje orilẹ-ede Naijiria. Sanusi ko gbe ọrọ oṣelu ti sẹgbẹ kan nitori ọpọ igba lo ti bu ẹnu atẹ lu awọn adari ni iha Ariwa Naijira fun aibikita wọn lori awọn eeyan ti wọn n ṣejọba le lori. Facebook love: Ọla àti Folashade ṣègbéyàwó lẹ́yìn ọjọ́ mọ́kànlá tí wọ́n ríra ni Facebook 2. Bo ṣe ṣẹlẹ si baba naa lo ṣelẹ si ọmọ Lamido Sanusi gori oye lọdun lọdun 2012 lẹyin ẹgbọn baba rẹ, Ado Bayero. Baba to bi baba rẹ, Muhammadu Sanusi kinni ni Emir kọkanla ilu Kano lati ọdun 1953 titi di ọdun 1963. Gẹgẹ bi wọn ṣe yọ Sanusi nipọ lọdun yii naa ni wọn yọ baba to bi baba Sanusi ọhun naa nipo, ẹsun ti wọn fi kan baba bab a rẹ naa ni pe, o n tẹ oju ofin mọlẹ. 3. Ọlọpọlọ pipe ni Sanusi Sanusi ṣeṣẹ lawọn ile ifowopamọ kaakiri ko ti de ipo ọga agba ile ifowpamọ apapọ ni Naijiria. Lẹyin to kawe jade ni ile iwe Kings college to wa ni ilu Eko, o tẹ siwaju ninu ẹkọ rẹ si fasiti Ahmadu Bello ni Zaria, nibi to ti kẹkọ gboye. Nitori ọpọlọ pipe to ni lo jẹ ki aarẹ Umaru Musa Yar'Adua faa kalẹ lọdun naa lọhun gẹgẹ bi ọga agbaile ifowopamọ apapọ Naijira. 4. Boṣe gori alefa Emir Awọn kan gbagbọ pe bi Sanusi ṣe gori alefa Emir lọwọ oṣelu ninu. Wọn ni bi Sanusi ṣe gba lati joye Emir jẹ ọna abayọ fun un ko ma baa jẹjọ lori ẹsun iṣowo baṣubaṣu ti wọn fi kan an gẹgẹ bi gomina banki apapọ Naijiria. Awọn miran tun n sọ pe ibatan rẹ ni oye naa tọ si lati joye Emir, wọn ibatan rẹ ọhun ni ni ojulowo ẹni to yẹ ko gori alefa Emir ọhun. International Womens day: Àwọn obìrintọ́kasí pàtàkì ìbáraẹnidọ́gba láárin ọmọnìyàn 5. Ẹni to tako ilana Nigba iṣejọba rẹ gẹgẹ bi Emir ilu Kano, ọpọ awọn awọn eeyan oke Ọya lo n wo Sanusi bi ẹni to n tako ilana aṣa awọn eeyan rẹ. Eyii ko ṣeyin bo ṣe ma n sọrọ tako awọn to n ṣẹlẹ lagbegbe ọhun bii; igbeyawo ọmọbinrin ti ko tii balaga, bo ṣe yẹ ki ijọba kọ awọn ile iwe dipo Mọsalaṣi, eti awọn nkan mii. Yatọ si eyi, Sanusi ma n sọrọ tako bi awọn eeyan Oke Ọya ṣe n bimọ bẹrẹ, leyi to ni o n fa iṣẹ ati iya lagbegbe ọhun, ti ko si dun mọ awọn eeyan naa ninu. Ọpọ igba ni Sanusi ma n sọrọ tako ijọba Kano pe o fi ẹtẹ silẹ lati mojuto lapalapa leyi to bi iwaadi iwa ibajẹ kan ninu ijọba naa. Lẹyin iwaaadi naa ni ijọba ipinlẹ Kano, labẹ iṣakoso Abdullahi Umar Ganduje yọ nipo gẹgẹ bi Emir lu ọhun. Fadeyi Oloro: Ọfọ̀, àyájọ́ kò ràn án lọ́jọ́ tí 'ṣó o láyà' bá a lálejò",0,yoruba "Tó bá jẹ́ òótọ́, a óò yí àwòrán ẹ̀yìn po tí pánẹ́ẹ̀lì náà bá jẹ́ olóòró.",0,yoruba Arsenal vs Burnley: Kí ló kàn fún Arsenal báyìí lẹ́yìn tí Burnley yẹ̀yẹ́ wọn mọ́lé ní Emirates?,0,yoruba bringing back the classics a mú àwọn orin ayébáyé padà wàá sikiru àyìndé barrister fuji garbage,0,yoruba "Ọgbẹni Akinọla Ọlaolu ni oun gba iwe ẹri gboye ọmọwe ni fasiti ilu Ibadan ki iwadi to sọ pe ko ri bẹẹ Igbakeji alaga igbimọ majẹobajẹ ileẹkọ naa, Oloye Inaọlaji Abọaba to ba awọn oniroyin sọrọ lọgba ileewe naa ni nigba ti iroyin naa lu sita pe ayederu ni iwe ẹri imọ ijinlẹ ọmọwe ti ọgbẹni Akinọla Olugbenga Ọlaolu n gbe kiri ni wọn ti yara kọwe si fasiti Ibadan nibi ti o ni oun ti gba iwe ẹri naa lati lee fidi otitọ ọrs mulẹ. "" Abajade ifidimulẹ lati ọdọ awọn alaṣẹ fasiti Ibadan ni pe, kii ṣe ileewe naa ni iwe ẹri ti o n lo ti jade. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Waris Kareem: Emmanuel Macron kan sáárá lórí àwòrán tó yà Igbimọ alakoso ileewe gbogboniṣe Igbajs ṣepade lori ọrọ naa nibẹ ni wọn si ti pinnu pe ki ọgbẹni Olugbenga Ọlaolu o fi ipo giwa ileewe naa silẹ."" Awo ọrọ nipa iwe ẹri Ọgbẹni Akinọla Olugbenga Ọlaolu lu sita ni ọsẹ diẹ sẹyin nigbati iroyin tan pe iwe ẹri ti o fi gba iṣẹ gẹgẹ bii giwa ileeks gbogbounṣe ilu Igbajọ kii ṣe otitọ ati pe arakunrin naa ko kẹkọ gboye ọmọwe, PhD ni fasiti ilu Ibadan",0,yoruba Ọ̀yọ́ jẹ́ ilẹ̀ agbègbè tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba joko. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó ga ju lọ nínú Nàìjíríà.,0,yoruba "Ní Nàìjíríà , àdó - olóró àgbẹ́sẹ̀léró ni gbàgede àgbàwí ọ̀rọ̀ òṣèlú .",0,yoruba Èkó yii nípa àlùfáà ni nfàn ojú kakaaki. Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba 14. Ìrà + ewé = ìràwé. Ìta + ilẹ̀ = ìtalẹ̀. Na + ìró = nàró ______ + egun = ojúgun #Ibeere #Yoruba,0,yoruba "Ojúu pópó olú ìlú náà , Conakry , àti àwọn ìlú tó kù ti di ojú ogun láàárín àjọ agbófinró àti àwọn ọmọ ìlú tó ń fi èhónú hàn .",0,yoruba "Akẹ́kọ̀ọ́ fásitì UNILAG ṣubúlulẹ̀ níbi tó ti ń gbá bọ́ọ̀lù, ó gba ibẹ̀ kú",0,yoruba "ìròyìn tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Ọkọ Adeola Egbebi ni ""mi o tilẹ mọ pe ara mi ni iso ti n run nigba ti mo sun mọ ibẹ afi ti wọn sọ fun mi mo si yari gidi gan"". Ọgbẹni Egbebi ni niwọn igba ti oun tun lọ bere lọwọ awọn ara inu ọja ti wọn ni bẹẹ lo ri koda ki ẹnikẹni to ba fẹ fọrọ wa awọn lẹnu wo ko maa bọ, o ka a lara gidi. Ìyàwó Adeboye gbàdúrà fún Nàìjíríà ní ìgbà akọkọ tó fara hàn lẹ́yìn ikú ọmọ wọn, Dare Akeredolu, jọ̀ọ́ gba iṣẹ́ lọ́wọ́ amúgbálẹ́gbẹ̀ẹ́ rẹ tó lu aláboyún - Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ yarí Obìnrin tó bá ṣí orí wọ Ààfin Deji Akure, Ọba á gbẹsẹ lé e, tóò bá wá lọ rẹwà ... Gba abẹ́rẹ́ Covid-19 kí o fi ọtí, ""Doughnut"", ẹ̀bùn owó ọ̀fẹ́ ṣararindin ""Bi mo ba nibi ti iṣẹlẹ igbati naa ti ṣẹlẹ ni, amugbalẹgbẹ ọhun ko ba ma fara ire lọ tori ohun to ṣe lo gbe iyawo mi de ile iwosan bayii"". O ni oun ti lọ fi ọrọ naa sun nile iṣẹ ijọba ipinlẹ Ondo to n ri si ọrọ awọn obinrin ati ileeṣẹ ọlọpaa lati da si ọrọ naa. Ẹwẹ, o sọ fun BBC pe inu oun bajẹ gidi nigba ti oun gbọ pe amugbalẹgbẹ gomina ipinlẹ Ondo gba iyawo oun leti to si ni oun ti lọ fi ọrọ naa sun nile iṣẹ ijọba ipinlẹ Ondo to n ri si ọrọ awọn obinrin ati ileeṣẹ ọlọpaa lati da si ọrọ naa. Gẹgẹ bo ṣe sọ, irẹjẹ naa kọja eyii ti oun ati idile oun le farada, oun si fẹ ki awọn ọmọ Naijiria da si ọrọ naa ki iyawo oun le ri idajọ ododo gba. Ẹgbẹ oṣiṣẹ ṣe iwọde lati ja fun ẹtọ arabinri oloyun. Ẹwẹ, ẹgbẹ awọn osisẹ nipinlẹ Ondo ti ke si gomina Rotimi Akeredolu lati gba isẹ lọwọ amugbalẹgbẹ rẹ fọrọ akanse isẹ ati aato, Ọmọwe Doyin Odebowale. Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe obinrin alaboyun kan to jẹ osisẹ nileesẹ kolẹ-kodọti lo daku nigba ti Odebowale gba leti lẹnu isẹ. Ẹgbẹ osisẹ naa ni iwa idojuti gbaa ni Odebowale hu si alaboyun naa, Adeola Egbebi lasiko ti obinrin naa wa lẹnu isẹ ladugbo Oja Oba nilu Akure l'Ọjọbọ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Atẹjade kan ti akọwe ẹgbẹ apapọ awọn osisẹ ọba (AUPCTRE) nipinlẹ naa, Comrade Moyin Banso fisita lọjọ Ẹti, lo sisọ loju ọrọ yii. 'Ẹ kálọ sí ìlú mi'... Ètò ńlá tó bẹ̀ sílẹ̀ kìjà lórí BBC Yorùbá ""A fi gbogbo ẹnu bẹnu atẹ lu iwa ti ọmọwe Odebowale hu si obinrin naa, idi si ree ta se n beere pe kijọba juwe ọna ile fun. Igbesẹ yii nikan si lo le jẹ ki alaafia jọba, ki wọn si maa tọpinpin ipo ti ilera obinrin naa wa."" Ki lo sẹlẹ saaju: Mo dákú rangbọndan lẹ̀yìn tí amúgbálẹ́gbẹ gómìnà Akeredolu fún mi ní ìgbájú olóyì - Aláboyún Alaboyun kan ti fẹsun kan olubamọran pataki lori akanṣe iṣẹ si gomina Rotimi Akeredolu ti ipinlẹ Ondo, Ọmọwe Doyin Odebowale pe o fọ oun leti. Obinrin naa, Egbedi Adeola ati ọkọ rẹ ṣalaye fun BBC Yoruba pe gbagede inu ọja ọba ilu Akure ni iṣẹlẹ naa ti waye. Gẹgẹ bo ṣe sọ, Adeola ni iṣẹlẹ naa waye lasiko ti wọn n ṣe eto gbalumọ inu ọja ti wọn maa n ṣe ni gbogbo Ọjọbọ. O ni ""Iṣẹ wolewole ni mo n ṣe ti a si maa n jẹ ki awọn araalu bọwọ fun ofin gbalumọ inu ọja, ṣugbọn o rẹmi lọjọ naa nitori mo jẹ alaboyun."" ""Nigba ti amugbalẹgbẹ gomina ọhun atawọn ẹmẹwa rẹ n bọ, wọn ni ki gbogbo awa ti a joko dide, mo si dide lati gbe ijoko ti mo joko le lori lọ si abẹ afara ọja ọba."" ""Lẹyin naa lo ni ki n gbe ijoko naa silẹ, nigba ti mo ki n wo ẹyin wo bayii, igbaju lo ko fun mi, lẹsẹ kan naa ni oju mi ṣu."" Adeola sọ siwaju si pe ile iwosan ni oun wa lati igba ti iṣẹlẹ naa ti waye nitori oun ko gbadu ara oun mọ, oun si ti n mura lati ṣe ayẹwo ara oun siwaju sii. Nigba ti BBC Yoruba kan si alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ondo, Tee-Leo Ikoro, o ni ko si ẹnikẹni to tii wa fi ọrọ naa to awọn leti. Bo tilẹ jẹ pe o ni awọn yoo gbe iwadii dide lori iṣẹle naa, ṣugbọn igbesẹ awọn yoo da le ọrọ ti wọn ba fi to ileeṣẹ awọn leti, kii ṣe lori ahesọ. Gbogbo akitiyan BBC lati gbọ lati ẹnu ọkunrin ti ọrọ naa kan, iyẹn Ọmọwe Doyin Odebowale lo ja si pabo. Ṣugbọn o sọ ninu ifọrọwerọ pẹlu ileeṣẹ igbohunsafẹfẹ ipinlẹ ọhun, OSRC pe, irọ pata ni ẹsun ti wọn fi kan oun ati pe oun ko fọwọ alaboyun ọhun leti. 'Iṣẹ wá burẹkẹ síi tórí Covid-19, owó ńlá ló wà nínú dídáná sun òkú, ìsìnkú Zoom, Live streaming'",0,yoruba Davido: Yinka Ayefele sọ ìrírí rẹ̀ pẹ̀lú olórin Davido tó fi ní kò dà bí àwọn ọ̀dọ́ olórin kan,0,yoruba #yorubahomographs Àṣá (Hawk) Àṣà (Culture) Aṣa (Wayward/Mannerless being) #learnyoruba #yorùbámadeeasy https://t.co/rmhoY3GPWx,0,yoruba Nínú ìwé rẹ̀ #InAfricasForestAndJungle #SixYearsAmongTheYoruba R.H Stone tú pẹẹrẹpẹ́ẹ̀rẹ̀ oun ojú rẹ̀ rí. @user,0,yoruba RT @user: Ajose wa o ni baje. Ayajo ede Yoruba yi larinrin pupo! Aseyi semin! @user @user #TweetniYoruba #TweetinYoruba #T…,0,yoruba "#iroyin, #yoruba, Ha ! Egbon Olamide, akeko OAU to ku ti soro o, o ni se ni won pa aburo… https://t.co/Rym91MOs0d",0,yoruba Ọ̀rọ̀ọ Nwanze pé àwọn Onígbàgbọ́ ní gúúsù Nàìjíríà ló pọ̀ jù lọ nínú ìwádìí àyẹ̀wò Pew Research kò ṣe é má gbàgbọ́ .,0,yoruba "Manchester United lo wa ni ipo keji ninu idije Premier League Idi abajọ ni pe ọgọọrọ awọn ololufẹ Man U yabo papa iṣere Old Trafford nibi ti wọn ṣe iwọde tako ẹbi Glazer to ra ẹgbẹ agbabọọlu naa lori bi Man U ṣe wa lara awọn ikọ agbabọọlu mẹfa to buwọlu iwe lati yapa lọ da idije European Super League ti ko kẹsẹ jari. Bakan naa ni wọn lo ifẹhonuhan ti wọn ṣe lati sọ fun ẹbi Glazer pe ki wọn yọwọ lọrọ Man United pe ki wọn ta ikọ agbabọọlu naa ni kiakia. Awọn alaṣẹ idije Premier League yoo ṣepade pẹlu Man U ati Liverpool bayii lati sọ ọjọ ti ifẹsẹwọnsẹ naa yoo waye. Niiṣe ni ero kun ita papa iṣere Old Trafford biba, nigba tawọn kan ninu wọn rapala wọle ti wọn si duro sori papa iṣere naa. Awọn alaṣẹ idije liigi naa sọ pe abo awọn eeyan to wa ni papa iṣere Old Trafford lọjọ Aiku lo ṣe koko. Police said groups of protestors began to gather at Old Trafford and separately at the Lowry Hotel, where the Manchester United players were staying Iroyin tiẹ sọ pe ọlọpaa kan ṣeeṣe nibi to ti n dari awọn ololufẹ Man U to yabo papa isẹre Old Trafford. Manchester United lo wa ni ipo keji lọwọ yii lori tabili idije Premier League, nigba ti orogun wọn, Manchester City wa loke tente. Manchester City ko ba gba ife ẹyẹ Premier League lọjọ Aiku to ba jẹ pe Man U fidi rẹmi ti Liverpool ti ere bọọlu naa ba waye. Bi ọrọ ṣe ri bayii, City ni lati jawe olubori ninu ifẹsẹwọnsẹ kan sii lati gba ife ẹyẹ Premier League ti saa bọọlu yii.",0,yoruba "Awọn ololufẹ oṣere Toyin Abraham ati ọkọ rẹ Kola Ajeyemi fi oriṣiiriṣii fọto awọn mejeeji pẹlu ọmọ wọn, Ire, soju opo Instagram, nibi ti wọn ti di kaka di kuuku niluu London. End of Instagram post, 1 Awọn olololufẹ wọn ni, ẹni ti ko ba ti ba idile Toyin Abraham pade, ko gbiyanju lati ṣe bẹẹ nitori idile ti o dara ni. Wọn ni ifẹ awọn si Toyin ati Kola ko le tan laelae, nitori ọmọluabi ni wọn. Sindodotayo Inu ẹni kii dun ki a pa mọ ra. Bẹẹ gẹgẹ lọrọ ri pẹlu oṣere tiata, Tayo Odueke ti ọpọ mọ si Sikiratu Sindodo, to n ṣopẹ fun Eleduwa to mu ri ọjọ ibi rẹ mii. Ọ sọ loju opo Instagram rẹ pe ẹrin keke lo gba ẹni oun lonii ọjọ Ẹti tii ṣe ọjọ ibi oun. Tayo sọ pe oun ko le tori bi ilu ṣe ri ki oun maa dunnu lọjọ ibi oun, bẹẹ lo gbadura pe ki Ọlọrun tubọ maa fi ere si iṣẹ ọwọ oun. Odunlade Adekola Gbajugbaja oṣere Odunlade Adekola fi fọto ara rẹ ati ti olootu rẹ, Mercy Aigbe sori oju opo Instagram nibi tawọn mejeeji ti rẹrin muṣẹ. Odunlade sọ pe Mercy ni olootu ere tiata ti oun kopa ninu rẹ, eyi ti akọle rẹ n jẹ ''DARA.'' Femi Adebayo Salami Aṣọ to gbajugbaja ni oṣere Femi Adebayo Salami fi dawọ idunnu opin ọsẹ. Awọ pupa ni aṣọ ọhun pẹlu fila pipa naa lori rẹ, bata alawọ funfun ni Femi Adebayo fi wọ si ori aṣọ naa. O sọ loju opo Instagram rẹ pe ara ọjọ Ẹti ọsẹ yii ni imura oun duro fun eyi to pe ni ''Friday swag.''",0,yoruba ... Olòṣì n ò ti ẹ̀ lọ mọ́. #June12Protest https://t.co/FvpBC9c671,0,yoruba "Adìyẹ funfun kò mọ ara rẹ̀ lágbà"""""""" Translation: """"""""The white chicken does not respect itself."""""""" #chicken #white #learnyoruba #wisesayings #owe #mondaywisdom #yorubalessons #yoruba #yorubaforbeginners https://t.co/PM9g41XO2W",0,yoruba "Wọ́n tún ṣe bẹ́ẹ̀ , wọ́n mú okùn ìkòkò ìse - ìrẹsì .",0,yoruba "Ṣálángá = pit toilet (Ṣíji búu, ó ní """"""""""""""""ṣálángá lo ma kúsí"""""""""""""""" - Ṣíji abused him, he said """"""""""""""""you will die in pit toilet"""""""""""""""") #Learn #yoruba",0,yoruba "Makinde, Sharafadeen Olùdíje fún ipò gómìnà lábẹ́ ẹgbẹ́ òṣèlú Zenith Labour Party, ZLP, Sharafadeen Alli kò sí níbi ìpàdé ìtagbangba BBC Yorùbá ó si ti kọ́kọ́ jẹ́ ẹ̀jẹ́ pé òun yóò wà. Bakan naa, oludije fun ẹgbẹ oṣelu PDP, Seyi Makinde naa ko yọju sibi ipade ifọrọwerọ naa. BBC Yoruba ti ṣaaju ṣe ohun to tọ lati ranṣẹ pe gbogbo awọn oludije ti awọn ti yoo dibo ni awọn nifẹẹ lati ri nibi ipade ifọrọwerọ naa. Ẹwẹ,. gbogbo awọn oludije to yọju lo wu awọn eniyan lori pẹlu gbogbo alakalẹ aato wọn lọlọkan o jọkan ti wọn ni awọn yoo gbe ṣe bi awọn ba di gomina ipinlẹ Ọyọ. Ẹ̀yin ọmọ Yorùba, kí ló le nínú fí fí àmì sí A-la-pa-n-dẹ-dẹ?",0,yoruba "Ataare, iyọ̀, àádùn, oyin, omi, ìreké, ọtí, orógbó, obì...abbl #isomoloruko #yoruba",0,yoruba "lọ, Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba US Covid-19 Moderna Vaccine:Amẹ́ríkà fí abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 mílíọ̀nù mẹ́rin ṣọwọ́ sí Nàìjíríà,0,yoruba "Eḳọ tí a kọ eḳọ nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ìyá lo ni Nitori eyi, ara eni lo ni.",0,yoruba "Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Princess ni ohun ko to ọmọ ọdun mejidinlogun, ti oun ti n da gbe pẹlu aburo oun ọkunrin, ti ọpọ bukata si wa niwaju oun. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Princess salaye pe oun maa bọ ẹnu oun ati ti aburo oun, pẹlu sisan owo ile ati ileewe aburo oun, lo mu ki oun gba idi wiwa ọkọ akero lọ. O wa gba awọn obinrin nimọran pe ọpọ isẹ wa nilẹ ti wọn lee se lai se owo nabi, yoo si dara ki wọn wa isẹ aje se dipo tita ara wọn fun ọkunrin.",0,yoruba Hijab Day: Orin tàkasúfèé ló wù mí kí n máa kọ ṣùgbọ́n Hijab kò jẹ́,0,yoruba tìkẹ́ gbé joko yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa aráyé: ti o ní wúlò.,0,yoruba gbogbo ẹni tí ìlọsíwájú ètò ilera jẹ lógún ẹ fọwọ́ sí ẹ sì tàn án ká sí àwọn ọ̀rẹ́ yín náà cc,0,yoruba "...nílé ayé yìí yóò jèrè ìwàa rẹ̀ nílùú mìíìn tó bá lọ. Ẹlòmíì tẹ́ ẹ rí tó ń ṣiwèrè kiri níbí, iṣẹ́ ọwọ́ ẹ̀ tó ṣe láyé tó ti kúrò ló ń jìyà ẹsẹ̀ẹ rẹ̀. Béèyàn bá ti kú nílé ayé níbí, ó ń ṣí awọ lọ síbòmìíìn ni. Ó lè lọ s'Ámẹ̀ríkà, ó lè lọ sí India...",0,yoruba àpapọ̀ pàsẹ pé kí ètò kónílé - gbélé bẹ̀rẹ̀ nílùú Àbújá àti àwọn ìpínlẹ̀ méjì tí ààrùn COIVD - 19 ń bá wọ̀yá ìjà .,0,yoruba @user Ẹ lọ kọ níbí https://t.co/9VhVQbyU8a Àti https://t.co/MKk2y9vwvd,0,yoruba "se se. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbfi yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Àwọn aláìì dé sí ìbàdandun láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba gbàgede = field ground venue èrò pọ̀ ní gbàgede ètò people are many on the event ground,0,yoruba "tí a kọ eḳọ nípa ire àti ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn ẹ̀kọ́ ọmọ aláwọ̀ wà níṣẹ̀.",0,yoruba "Ní ní àìlẹ̀, Ìyá ri A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà. ti Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba "Dino Melaye, Smart Adeyemi àti Peter Obi sọ̀rọ̀ sókè lórí ìgbẹ́jọ́ Ike Ekweremadu",0,yoruba "Black friday Koda ọrọ naa kan gbogbo agbaye pẹlu eleyi ti wọn n pe ni ""Black Friday"" Ọpọ ni o si maa n lo anfani eto ayajọ ẹdinwo 'Black Friday"" naa lati fi ra awọn ọja opin ọdun sile. Ẹdinwo ọja yii a maa fa wọlu-kọlu ni ọpọ awọn ile itaja nitori ọpọ ero ti o fẹ ra ọja lowo pọọku. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Bi o tilẹ jẹ pe pupọ awọn ọmọ orilẹ-ede yii ni wọn kopa, ọpọ ni ko lee sọ ni pato, bi eto Black Friday yii ṣe bẹrẹ. Kini o faa ti wọn fi n pe ayajọ yii ni black Friday? Ọpọ ni o si maa n lo anfani eto ayajọ ẹdinwo 'Black Friday"" naa lati fi ra awọn ọja opin ọdun sile Lai deena pẹnu, bi eto ẹdinwo ọja, black Friday ṣe bẹrẹ ṣi ṣokunkun pẹlu oniruuru itan lori bi o ṣe bẹrẹ ṣe n gba aye kan. Ọkan lara awọn itan black Friday ti o gba igboro kan ju ni pe pupọ awọn ọlọja ti wọn kii ri ọja ta pupọ ni wọn maa n ri ọja ta ni ọjọ ti o ba tẹlẹ ọjọ idupẹ ni orilẹede Amẹrika. Awọ dudu si ni awọ ti wọn maa fi n ṣe apẹrẹ pe aje n bu igba jẹ nigba ti awọn pupa fihan pe ọja ko ta to bi wọn ti fẹ. Awọn miran ṣalaye pe ilu Philadephia ni orukọ yii ti bẹrẹ laarin ọdun 1950 si 1960. Ọpọ ni o si maa n lo anfani eto ayajọ ẹdinwo 'Black Friday"" naa lati fi ra awọn ọja opin ọdun sile Ohun ti itan yii sọ ni pe awọn ọlọpaa atawọn awakọ ni wọn maa n lo o Black Friday lati fi ṣe apejuwesunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ ti o maa n waye lasiko ti awọn to wa raja ba fọn si oju popo ni ọjọ ẹti, (Friday) ṣaaju ifẹsẹwọnsẹ bọọlu laaarin ikọ ọmọogun oriilẹ ati ọmọogun oju omi eleyii ti o maa n waye ni ọjọ abamẹta nigba naa. Bi o tilẹ jẹ pe a ko lee sọ ni pato bi o ṣe bẹrẹ, ṣugbọn ohun kan ti a lee fi ọwọ rẹ sọya ni pe ogunlọgọ awọn ọmọ orilẹede Naijiria ni wọn ti n dara pọ mọ eto yii bayii. Ni ilu Ibadan n ṣe ni awọn ero wọ ni kẹtikẹti lọ sawọn ile itaja ti o ṣe eto naa. Ni ibudo itaja igbalode Shoprite, ẹsẹ o gbero pẹlu bi awọn eeyan ṣe bo ibẹ lati ra awọn ohun elo ti awọn alaṣẹ ibudo itaja naa ti kede ni ẹdinwo. Kini awọn eeyan sọ nipa rẹ? Bakan naa ni awọn ọja bii ẹrọ ibanisọrọ, ororo, ohun elo iṣura ara obinrin pẹlu maa n ta pupọ Ọkan lara awọn eeyan to lọ ra ọja nibẹ, Adeọla Ọdọle to ba BBC News Yoruba sọrọ ṣalaye pe igba keji niyi ti oun n kopa ninu ayajọ ẹdinwo ọja Black Friday nibẹ. ""Ko si ẹni ti ko fẹran ẹdinwo nitori ko si owo nilu, ṣugbọn nigba ti wọn kede rẹ ni mo fi wa. Fun apẹrẹ, oro ti a n ra ni ẹgbẹrun meji naira ni wọn ta ni ẹgbẹrun meji o din igba naira. Bakan naa ni ohun mimu milo ti wọn n ta ni ẹgbẹrun kan ni wọn ta ni ẹgbẹrin naira. Ara ohun ti o faa ti awọn eeyan fi pọ yanturu niyi."" Ajyajọ yii ko mọ pẹlu awọn ibudo itaja nikan. Awọn ileeṣẹ itaja ori ayelujara bii Konga, Jumia ati bẹẹbẹẹ lọ pẹlu ti dara pọ mọ ayaju yii pẹlu oniruuru eto ẹdinwo ọja bii ọja kolọ-n-lẹ ko dowo Flash sales ni Jumia ati Konga yakata. Ni ilu Ibadan n ṣe ni awọn ero wọ ni kẹtikẹti lọ sawọn ile itaja ti o ṣe eto naa Awọn ọja wo ni o n ta julọ ni ayajọ ẹdinwo Black Friday? Oṣiṣẹ ileeṣẹ Jumia kan ti o ba BBC Yoruba sọrọ ṣalaye pe""asiko yii ni iye awọn ti o n ra ọja maa n pọ nitori ẹdinwo ori ọja."" O ni awọn ohun elo ile bii ẹrọ ifọṣọ (washin machine) ati mohunmaworan ni o maa n ta julọ lasiko yii. Bakan naa ni awọn ọja bii ẹrọ ibanisọrọ, ororo, ohun elo iṣura ara obinrin pẹlu maa n ta pupọ. Chef Adefunkẹ: Òórùn ewé tí wọ́n n pọ́n ìrẹsì ọ̀fadà si jẹ́ adùn lọ́tọ̀ Fanny gbà kádàrá lórí àwọn orin rẹ̀ kí wọn to ṣe alakọkọ lọdun 2012",0,yoruba mo ki gbogbo ẹ̀yin musulumi lagbaye pe e̩ ku ọdun ibe̩re̩ awe̩ yìí ara,0,yoruba ní nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o nuni ti o nuni ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde.,0,yoruba "jú, àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba ó gba ọ̀dọ adáhunṣe lọ ó sì gba oògùn tí yíò fi bá ajá jà adáhunṣe fún ìjàpá láàdó pé kí ó lọ rì í mọ́lẹ̀ sínú oko rẹ̀,0,yoruba Omoluabi wa ni àbá èwe lo je ti ibile.,0,yoruba "@user Àmí o. Àti gbogbo àwọn tó tẹ̀lé wa. Bẹ́ẹ̀ni, àmọ̀ràn pọ̀ rẹpẹtẹ.",0,yoruba "Níbẹ̀ , wọ́n fi ẹ̀kọ́ kún ẹ̀kọ́ ìmọ̀ ìtàkùrọ̀sọ àti kọ́ nípa ipa àyípadà ojú - ọjọ́ .",0,yoruba ṣe àwọn iṣẹ́ tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa iṣẹ́: ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọmọ lo ni ìgbà àkerekere ye ka yè.,0,yoruba "Mo ba @user yo Ayo ojo ibi o, emi a se pupo e laye, igba ile a lesi, awo ile a le si, aseyi seemii, lase Edumare",0,yoruba "Ó jẹ́ nǹkan ìbànújẹ́ wípé ilé náà ti ṣe tán , ó lè wó nígbàkigbà látorí àìṣàtúnṣe , àìkáràmáìsìkí ohun àjogúnbá , àti ìbàjẹ́ tí àwọn tí ó gbé ilé láì gba àṣẹ ń fà .",0,yoruba pe dara gan wey ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà.,0,yoruba RT @user: @user mmm die niyi ninu awon nkan ti o le sele ti a ba n fi idande won tafala.,0,yoruba "Igba mi owó àkokò, Ọba lo ni ìgbà mi owó àkokò, Alàji lo ìgbà ọkọ.",0,yoruba "Gẹgẹ ba ti gbọ, afojusun ipade ọsan ọjọ Isinmi naa ni lati wa nnkan ṣe sawọn ẹdun ọkan tawọn ọdọ to n sewọde gbe siwaju ijọba, eyi to da lori ọna lati dẹkun iwa kotọ awọn ọlọpaa. Aarẹ ile aṣofin agba, Sẹnetọ Ahmad Lawan pẹlu olori ile aṣofin-ṣoju, Fẹmi Gbajabiamila si lo n ba aarẹ se ipade naa. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Amugbalẹgbẹ fun aarẹ Buhari lori ọrọ ibanisọrọ ori ayelujara, Bashir Ahmad lo fi eyi sita loju opo Twitter rẹ, @BashirAhmad. Wo àwọn ọ̀nà tí o lè gbà láti di ọjọ́ ogbó pẹ̀lú olólùfẹ́ rẹ Lẹyin ipade naa, aarẹ ile aṣofin apapọ, Sẹnetọ Ahmad Lawan ṣalaye fun awọn akọroyin pe, ijọba apapọ ti tẹwọ gba gbogbo ẹhonu awọn ọdọ to n wọde naa. O fikun pe asiko to fun wọn lati dẹkun iwọde naa, ki wọn le fun ijọba lanfani ati aaye lati mojuto awọn ẹhonu ti wọn gbe kalẹ. Ẹ foríjìn wá ọmọ Nàìjíríà, mó mọ̀ pé ẹ̀ ń bínú tórí a kò tètè gbé ìgbésẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ EndSARS- Osinbajo Ẹyin ọmọ Naijiria ẹ jeburẹ o, ẹ forijin wa, lootọọ lo yẹ ki ijọba apapọ ti wa nkan ṣe si ọrọ awọn olufẹhonuhan lori ọlọpaa #EndSARS / End SWAT. Igbakeji aarẹ orilẹede Naijiria, Ọjọgbọn Yemi Osinabjo lo sọrọ yii ninu atẹjade kan to fi sita to si tun wa loju opo Twitter rẹ. Ọjọgbọn Osinbajo ni ''mo mọ pe ẹ n binu, o si yẹ bẹẹ. O ye mi yekeyeke bi ọpọ ọdọ orilẹede ni inu wọn ko dun.'' ''Ọpọ lo ro pe a ti dakẹ ju lọri ọrọ to wa nilẹ wi pe igbesẹ ijọba kudiẹ kaato. Wọn jare wa,'' Osinbajo lo sọ bẹẹ. Igbakeji Aarẹ ni ''ọgọọrọ ọmọ Naijiria ni awọn ọlọpaa ti fi iya jẹ lọna aitọ, eyi ko si bofin mu.'' ''Ojuṣe wa ni lati daabo bo awọn ọdọ papaa julọ lọwọ awọn ti ijọba n sanwo fun un lati daabo bo wọn,'' Ọjọgbọn Osinbajo lo woye bẹẹ. Osinbajo gbagbọ pe iwọde #EndSARS to n lọwọ kaakiri orilẹede Naijiria ju ọrọ awọn ọlọpaa to n dunkoko mawọn ọdọ lọ nikan. O ṣalaye pe ijọba ti n ṣe ipade pẹlu awọn tọrọ kan lati ojutu si ohun tawọn ọdọ to n ṣe iwọde n beere fun. ''Emi fun ra mi ni alaga ipade pẹlu awọn gomina ipinlẹ mẹrindinlọgbọn ati minisita olu ilu Naijiria, Abuja nibi ti a ti gbe igbimọ ti yoo ṣe iwadii iwa ika tawọn ọlọpaa #SARS ti hu. Bakan naa ni igbakeji Aarẹ kẹdun pẹlu idile Jimoh Isiaq ti ibọn ọlọpaa pa niluu Ogbomoso atawọn mii naa to ti ba iwọde #EndSARS lọ. End SARS, End SWAT: Ó pé mi bí SARS kò ṣe sọ mí dolówọ́- Fulani Kwajafa Mi ò mọ̀ nípa àwọn tọ́ọ̀gì tó da ìwọ́de EndSARS Alausa rú, mo ṣì wà lẹ́yìn yín digbí! - Sanwoolu Ijọba ipinlẹ Eko ti ni oun ko lọwọ ninu idaru to waye nibi iwọde EndSARS to waye ni agbegbe Alausa ipinlẹ Eko. Wọn si ni awọn kọ lawọn ṣe onigbọwọ awọn janduku to ṣaadede ya wọ ibẹ lati da iwọde ti awọn ọdọ n ṣe lodi si iwa aburu ti awọn ọlọpaa Naijiria n hu. Kọmiṣọnna eto iroyin ni ipinlẹ Eko, Gbenga Omotoso ninu atẹjade kan to fi sita ni ẹsun naa to n ja ranyin ranyin lori ayelujara jẹ ete awọn ọta lati ko nkan jọ lodi si ijọba. O ni, bẹẹ, ijọba ipinlẹ Eko lo ti n ṣa gbogbo ipa lati yanju iṣoro to wa nilẹ nipa gbigbaruku ti awọn ọdọ ninu akitiyan lati wa alaafia Naijiria. Bakan naa gomina Babajide Sanwoolu fi si oju opo instgram pe oun ni imọlara ohun tawọn ọdọ n ja fun torinaa ko ṣeeṣe ki oun tun ran awọn janduku lati wa da iwọde wọn ru. ""Mo bu ẹnu atẹ lu ikọlu to waye yii mi o si laye laye gbe lẹyin mọndaru ati iwa ipa si araalu"". Gomina Sanwoolu fi idaniloju han pe awọn ti y a ipinlẹ Eko sọtọ lati faaye gba awọn igbesẹ awọn oluwọde tori pe nkan to tọ ni wọn n ṣe. Lowurọ ọjọbọ ọsẹ yii ni awọn janduku ti wọn dira pẹlu ohun ija ṣaadede yabo ibi ti awọn ọdọ ti n ṣe iwọde ni agbegbe Alausa ni Eko nibi to jẹ pe awọn ọdọ kan sun mọju niwaju ọfiisi gomina. Sotitobire: Ọkọ mi kò mọ̀ Jegede PDP rí, kódà kò fa ẹnikẹ́ni kalẹ̀ dípò Akeredolu- Bisola Bi ẹ ko ba gbagbe, igba keji ree ti gomina Sanwoolu yoo yọju si awọn oluwọde koda o tun ba gbe patako soke. Ati pe o tun diidi gbera lọ silu Abuja lati lọ jiṣẹ awọn ọdọ fun aarẹ to si gba esi bọ fun wọn. Ẹ̀yin olùwọ́de, ẹ lọ kọwọ́ ọmọ yín bọṣọ, bí bẹ́ẹ̀ kọ́...- iléeṣẹ́ ológun kìlọ̀ Ẹ lọ ki ọwọ ọmọ bọ aṣọ, bii bẹẹ kọọ, ẹ o kan idin ninu iyọ. Bayii ni ileeṣẹ ọmọ-ogun ori ilẹ ṣe kilọ fawọn to n ṣe iwọde #EndSARS kaakiri Naijiria. Ninu atẹjade ti ileeṣẹ ologun ori ilẹ fi sita, wọn ni awọn sọja ṣetan lati lo gbogbo agbara wọn lati daabo bo ijọba awarawa orilẹede Naijiria. Adele alukoro ile iṣẹ ologun Naijiria, Col Sagir Musa, to fi atẹjade ọhun sita ṣalaye pe ileeṣẹ ologun wa lojufo lati rii pe alaafia jọba ni Naijiria ni gbogbo igba. O sọ ninu atẹjade ọhun to fi si oju opo Facebook ileeṣẹ ologun ori ilẹ pe Aarẹ Muhammadu le fi ọkan tan awọn ọmọ-ogun Naijiria lọjọkọjọ. Col Musa sọ pe awọn omogun oriilẹ Naijiria duro gbọingbọin lẹyin Aarẹ Buhari ati iwe ofin orilẹede Naijiria bakan naa. Ileeṣẹ ologun wa rọ ẹnikẹni to ba fẹ da rogbodiyan silẹ tabi ṣe ohun kohun to le dunkoko mọ ijọba awarawa Naijiria pe ki wọn semẹdọ. Adele alukoro ile iṣẹ ologun Naijiria tun rọ awọn ọmọ-ogun pe ki wọn wa lojufo lai bikita ohun tawọn to n da rogbodiyan silẹ n ṣe. End SARS, End SWAT: Ó pé mi bí SARS kò ṣe sọ mí dolówọ́- Fulani Kwajafa Bakan naa nileeṣẹ ọmogun sọ fawọn araalu pe ki wọn fọkan balẹ, wọn ni awọn ṣetan lati daabo bo wọn. Amọ yii ko ba ọpọ eeyan lara mu lori ayelujara. @peterparne ni tiẹ sọ pe awọn meji lo n tako alaafia ati iṣọkan orilẹede Naijiria lẹyin to kọkọ ki wọn ku iṣẹ. O ni ijọba fun ra rẹ ati ẹgbẹ agbesunmọmi Boko Haram lo n tako alaafia orilẹede Naijiria. Ọpọ awọn ọdọ ti wọn lara awọn to n ṣe iwọde ni wọn fesi pe alaafia lawọn n lepa, ati pe iwọde wọọrọwọ lawọn n ṣe. Eegunjobi Omotanbaje Ajobiewe- Èébú ní wọ́n kọ́kọ́ ń bù mí nígbà tí mo bẹ̀rẹ̀ ẹ̀ṣà pípé ní Wọn ni alaafia lawọn n lepa lo jẹ kawọn maa ṣe ifẹhọnuhan eyi ti ko lodi si ofin. Ẹ wo èrò bìbà níbi ìwọ́de #EndSARS ní ìlú Ibadan Kaka ki ewe agbọn agbọn dẹ, niṣe lo n le koko si. Iwọde #EndSARS ti gberasọ niluu Ibadan naa lẹyin ti o ti mulẹ tan niluu Eko. Opopona mọrosẹ agbegbe Iwo Road ni ilu Ibadan ti kun fọfọ fun ọgọrọ awọn ọdọ to n wọde tako ọlọpaa SARS. Lilọbibọ ọkọ ti dawọ duro lati owurọ oni ọjọ kẹtala oṣu kẹwa ọdun 2020 yii. Pupọ ninu awọn ero ọkọ lo n bọọlẹ ti wọn si n fi ẹsẹ wọn rin lọ si ibi ti ọkọ n gbewọn lọ. EndSars, EndSwat: Ọlọ́pàá ti fi ìbọn lù mí láyà rí torí mó ní 'extra tyre' méjì- afẹ́hònúh Wọnyii ni awọn aworan bi iwọde #endSARS ṣe n lọ niluu Ibadan. Oluwo jọgbọdọ Orunmila àti àwọn eeyan rẹ nibi iwọde #End Sars ati #Sarsmustend to n lọ lọwọ ni ilu Ibadan. coronavirus prevention badge update: Wo òótọ́ àti irọ́ tó wà nínú báàjì àyà náà A máa ná N10.2 bílíọnù fi tún wáyà iná àti inú ilé Aso Rock ṣe- Buhari Wo ìdí tí Tẹni, ọ̀dọ́mọdé olórin obìnrin kìí fi ń ṣí ìhòhò rẹ silẹ̀ Wo ìgbà mẹ́rin tí ìjọba ti tú ikọ̀ ọlọ́pàá SARS ká sẹ̀yín ṣùgbọ́n.... Wọ́n kò pa ẹnikẹ́ni sí ààfin Ṣọun Ogbomosọ, òkú tí àwọn ọdọ́ gbé wa ni ọlọ́pàá wọ́ jáde- Agbẹnusọ Ṣọ̀un Àwọn aṣòfín ní ìpínlẹ̀ Edo ti yọ Abẹnugan Ilé, Francis Okiye bí jìgá Mọ̀ sí i nípa díẹ̀ lára àwọn èèyàn tí ikú wọn 'láti ọwọ́ ọlọ́pàá' milẹ̀ tìtì ní Nàìjíríà Ènìyàn 17 kú nínú ìjàmbá ọkọ̀ mẹ́ta tó ṣẹlẹ̀ ní Osun, òpópónà Ibadan sí Eko àti Delta Ẹ bá mi tú gbogbo àwọn Olùwọ́de #End SARS tí ẹ mu ní ìpínlẹ̀ Eko sílẹ̀- Gomina Sanwo Olu Kò gbọdọ̀ sí ìfẹ̀họ́núhàn EndSARS ní ìpínlẹ̀ Rivers - Gomina Wike EndSARS protest in Nigeria: Mr Macaroni, Falz, Wizkid, Tiwa Savage àtàwọn míì ṣe ìwọde",0,yoruba papa re yóò ri Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "lálai. Nitori eyi, ara eni lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó ga jù.",0,yoruba Ẹgbẹ́ òsèlú APC yọwọ́ olùdíje mẹ́wàá kúrò láwo àwọn tó máa díje dupò aàrẹ Nàìjíríà,0,yoruba nigbogbo ona oluwa loye kama fi ope fun nitori nipa ife ree lafi wa laye,0,yoruba o pataki. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọmọ lo ojú odò.,0,yoruba "Bàbá Leah Sharibu ti fẹ̀si lorí ìròyìn pe ọmọ rẹ ti bímọ fún ọga Boko Haram Laipẹ yi ní ìròyìn ti kò fìdímulẹ̀ kan gbòde pé Leah Sharibu ti bímọ ọkunrin fún adári àwọn ọmọogun Boko Haram àti pé o ti yí pada si ẹsìn Islam. Nínú ìfọ̀rọwérọ pẹlu Baba Leah èyí ti ilé iroyin Channels ṣe lọjọ Aiku ni ọgbẹ́ni Nathan Sharibu ti sọ pe òun kò ṣetan láti fẹèsì kankan lóri ọ̀rọ̀ náà. Human trafficking: Iṣẹ́ irun ṣíṣe ló di iṣẹ́ aṣẹ́wó Baba Leah ni ǹkan to ṣe pàtàkì fú òun ni pé kí òun ri ọmọ òun ki o pàda wále láyọ àti aláfíà ti yóò sì ri bẹ́ẹ̀ àti pé òun ko ni gba ìròyìn òfégè kankan láàyè. Oniroyin Ahmed Sakilda naa da si ọrọ yi nigba ti o sọ sóri àtẹjiṣẹ́ twitter rẹ̀ pé Leah ti di ìyàwó àdari àwọn Boko Haram àti pé o ti bímọ tuntun jòjòló. Bàbá Leah Sharibu ti fẹ̀si lorí ìròyìn pe ọmọ rẹ ti bímọ fún ọga Boko Haram Ti ẹ o bá gbàgbé wọn ji Leah àti àwọn ọgọrun akẹgbẹ rẹ gbé ni ilé ìwé wọ́n ni Science Secondary School Dapchi ìpínlẹ Yobe ni ọjọ kọkàndinlógun, ọdun 2018. Bótilẹ̀ jẹ́ pé wọ́n pada tú àwọn tókù sílẹ̀ wọn ko fi òun silẹ̀ nítori pe wọn ni o kọ láti kọ ẹsìn Kristeni. Awọn ẹgbẹ ọmọlẹ́yìn Kristeni àti àwọn ajáfẹ́tọ ọmọniyan jákejádò àgbáye lo ti n polongo fun ìtúsilẹ̀ rẹ̀.",0,yoruba "Òròmọadìyẹ ńbá àṣá ṣeré, ó rò pé ẹyẹ oko lásán ni. / The chick gullibly plays with the hawk believing it to be an ordinary bird. [Naivety can be risky, if not fatally costly.] #Yoruba #proverb",0,yoruba "Ilumọọka osere tiata nni, Yomi Fabiyi ti sisọ loju rẹ pe oun ti se abẹwo si Baba Ijesha ni ahamọ ọlọpaa, ẹni ti wọn fẹsun sise asemase pẹlu ọmọde kan. Yomi Fabiyi sisọ loju ọrọ yii lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ lori iwọde to fẹ se tako awọn ọlọpaa ti wọn ko ba gbe iya ọmọ ti ọrọ kan lori ẹsun lilo ọmọ rẹ fun asemase lati ko ẹri jọ. ""Emi o mọ ibi ti awọn to ni awọn pupọ ṣẹ n tẹle mi ti ri ero o, mo ti ni ero temi tẹ́lẹ̀, botilẹ jẹ pe ko tii pọ to, awọn to mọ ibẹrẹ mii naa lo fẹran mi to n tẹle mi"". O ni awn to n wọ tẹle oun jẹ awn to rii pe eeyan kan ṣe maa da duro to si jẹ pe ootọ lo n sọ. Yomi Fabiyi ni lasiko abẹwo rẹ si agọ ọlọpaa Panti, nibi ti wọn fi Baba Ijesha pamọ si ni oun ti bi afurasi naa pe ko sọ ootọ to ba jẹ pe o ba ọmọde naa lopọ. 'Iṣẹ wá burẹkẹ síi tórí Covid-19, owó ńlá ló wà nínú dídáná sun òkú, ìsìnkú Zoom, Live streaming' ""Mo gbiyanju, mo lọ si Panti, mo si ni ki wọn jẹ ki n ri Baba Ijesha, mo bii pe se lootọ lẹ ba ọmọ naa sun amọ o sọ fun mi pe ko ri bẹẹ, oun ko ba sun rara. Nollywood: Bẹbẹ ń lọ ní ibùdó yíya sinimá Àgbésọrísùn Mo wa sọ fawọn ọlọpaa pe ki wọn duro si ẹgbẹ mi, ki wọn maa gbọ ohun ta n sọ, mo si tun bi Baba Ijesha pe ẹ jọọ se fidio ta n sọ yẹn, se fidio pe ẹ n ba ọmọ yii sun ni ? Baba Ijesha wa ni Yomi, emi fi n da ẹ loju pe ko ri bẹẹ amọ to ba ri bẹẹ, bẹ ori mi sogun, n ko ba ọmọ yii sun ninu fidio yẹn, amọ mo fi ọwọ kan."" Yomi Fabiyi wa tẹsiwaju pe oun tun bi Baba Ijesha pe se o ti ri fidio ti wọn gbe sita nipa oun ati ọmọde naa, to si ni rara amọ ki oun lọ wo lati se atupalẹ rẹ. Yomi Fabiyi ló ni ki òun àti ìyàwó rẹ̀ yàgò fún ra wọn O ni oun wa bẹ awọn ọlọpaa pe ki wọn jẹ ki oun ri fidio naa amọ wọn ni oun ko le ri, ti oun si sọ fun Baba Ijesha pe yoo dun oun gan, ti ọrọ naa ba de ile ẹjọ, ti asirir si tun pe o sẹ ẹsẹ naa. Gbajumọ osere tiata naa ni oun tun bi afurasi naa pe se wọn n fiya jẹ ni ahamọ ọlọpaa bi, to si ni rara amọ o ni oun ko ti ni agbẹjọro ti yoo soju oun nile ẹjọ. ""Mo tun bi pe bawo lo se n jẹun, ti mo si se iwọnba ohun ti mo le se fun lori eyi nitori emi kii se ajẹnisẹni. Mama Rainbow: iṣẹ́ tíátà kò ta sánsán mọ́ bíi ti ayé àtijọ́ Bi eeyan to sun mọ mi ba sẹ, ẹtọ mi ni lati se atilẹyin fun. Kii se pe ẹnikẹni n gbe lẹyin Baba Ijesha, ohun tawọn eeyan n sọrọ le lori lo da lori ẹri to wa niwaju wọn."" Yomi Fabiyi wa sisọ loju rẹ pe o seese ki Baba Ijesha ti ni agbẹjọro ti yoo soju rẹ bayii ti yoo sọrọ fun nitori ẹni kan ti pe oun lori ọrọ naa. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: O fikun pe wọn ko tii gbọ ọrọ lẹnu Baba Ijesha amọ nigba to ba dele ẹjọ, a o gbọ winrinwinrin lẹnu rẹ. Nigba to n sọrọ lori iwọde to fẹ se, Yomi Fabiyi ni ohun ko le dakẹ lori ọrọ naa nitori ko dara ki wọn maa fi ọmọde ko ẹri jọ, o le sọ wọn di apẹẹrẹ Ajasẹ. O fikun pe bi oun se iwọde, bi oun ko se iwọde, nigba ti ọrọ naa ba de ileẹjọ, gbogbo aye yoo gbọ ẹsun lorisirisi, wọn yoo fi ẹsẹ fẹ. Tóo bá ní ìmọ̀ nípa ǹkan, ran àwọn tí kò ní ìmọ̀ lọ́wọ́ láti mọ̀ - Yomi Fabiyi Gbajugbaja oṣere fiimu Yoruba to ti n gba waju ga ẹyin lati igba ti ọrọ ẹsun ti wọn fi kan Baba Ijesha ti ṣẹlẹ, yomi Fabiyi tun ṣe afiwe ọrọ kan fi yi awọn akẹgbẹ rẹ lara. O jẹ ko di mimọ pe oun mọ nkan ti oun nṣe tabi sọ lori ẹsun naa paapaa lẹyin to ti wo fidio kan to jade ti iroyin ni o ṣafihan bi Baba Ijesha ṣe n fi ọwọ pa ọmọde ti wn ni o ba ṣe aṣemaṣe lara. Yomi to ti kede pe oun yoo ṣe iwọde bi ijọba tabi ọlọpaa ko ba ṣe nkankan ni Iwọde lati ja fun ẹtọ ọmọde lori ifipabanilopọ ni nkan to tọju lati ṣe. ""Iwọde wọọrọwọ lori ẹsun ifipabanilopọ ati aṣemaṣe pẹlu ọmọde yẹ ko jẹ nkan ti yoo di ranto. Ija fun ẹmi Naijiria lo jẹ ati ija fun ọjọ iwaju wa ni"". Fabiyi ni ẹtọ rẹ ni iwọde wọọrọwọ. O ni asiko ti to lati ya awọn to ni imọ, to laju, ti ko gbe sẹyin ẹnikan, to n ja fẹtọ ọmọniyan ati olufọkansin araalu sọtọ kuro lara awọn ti ida keji wọn. ""Ija yii, fun ọmọ rẹ ati awọn ọmọ mii ni"". Yomi Fabiyi fi kun un wipe iṣẹlẹ yii to eyi teeyan n fi gbogbo nkan ji fun. ""Bakan meji ni, yala Naijiria n pada sẹyin tabi lọ siwaju ni. Agbajọwọ wa la le fi sọya nipa fifi ohun kan sọrọ lori gbogbo iwa biba ọmọde ṣe aṣemaṣe, fifi wọn dẹ pakute, ifipaba wọn lopọ ati ilkulọ ibalopọ."" Gbogbo eyi ni Yomi ni o lee mu orilẹede lọ siwaju tabi ko mu u jo ajorẹyin to si ni ẹni ti ko ba ni imọ ko wa a daadaa ko to maa bọ sori ayelujara sọrọ soke.",0,yoruba RT @user: D'banj Ti Fe Le Gaari Ijebu Wole Pelu Koko Garri: D'banj ti se ifilole Garri re eleyii to pe ni 'Koko Garri'. ... http://t.co/g…,0,yoruba lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba "APC,PDP, ZLP àtawọn ẹgbẹ́ miran ni Ondo Ninu idibo naa to waye ni ọjọ Kẹwaa, oṣu Kẹwaa, ọdun 2020 ti Gomina Rotimi Akeredolu ti ẹgbẹ oṣelu APC lo gbegba oroke. Adajọ Umar Abubakar ni yoo lewaju awọn adajọ meji mii ti yoo gbẹjọ ọhun bẹrẹ lati ọjọ Kẹjọ oṣu Kejila ọdun 2020. Agboola Ajayi: Igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo tó fẹ́ yẹ àga mọ́ Akeredolu nìdí Agbẹjọro oludijẹ ẹgbẹ PDP, Eyitayo Jegede tii ṣe Onyechi Ikpeazu lo fiwe pe Gomina Akeredolu ati ẹgbẹ APC fun aṣemaṣe to tako ofin ilẹ yi. Lara kudiẹkudiẹ to mẹnu ba ni pe Gomina Akeredolu kọ ni ẹgbẹ rẹ dibo yan lati ṣoju wọn ninu idibo Gomina. Ni ibamu pẹlu ohun tofin ilẹ yi sọ, o ni Gomina ipinlẹ ko le jẹ alaga ẹgbẹ ti yoo yan ẹlomii lati dije dupo. O salaye pe Gomina ipinlẹ Yobe, Mai Mala Buni lẹni to tako ofin yi nipa pe o di ipo alaga ẹgbẹ APC mu to si tun yan Akeredolu lati dije dupo Gomina. Yatọ si alaye yi gẹgẹ bi kan lara idi ti ko yẹ ki wọn fi gba iyansipo Akeredolu wọle, Jegede tun ni iwa janduku waye lawọn ijọba ibilẹ kan ati aaye idibo lawọn ibomiran. Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ",0,yoruba ilera ṣẹlẹ ni Lagos ti gbogbo eniyan sọ o ṣe pataki. (2007),0,yoruba "fè se, A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà.",0,yoruba ọ̀pọ̀ olóṣèlú ńsùn lé e ó yẹ kí wọ́n máa lo alátagbà tàkòrọ̀sọ pẹ̀lú arálùú àmọ́ púpọ̀ ò ṣe bẹ́ẹ̀,0,yoruba "ni ìbàdandun àtọ́wọ́dá, àwọn oníṣẹ́ ìṣẹ́ ni a ní nípa ire àti ìbàdandun, àwọn aláìì lẹ̀.",0,yoruba ní láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbfi yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba a kú oṣù titun tó wọlé dé wẹ́rẹ́ o,0,yoruba Fàyè gba àwọn ìtasókè,0,yoruba "ègé olóótọ fún àwọn ìkòkò tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba Àwòrán 1 : Àwòrán Túwíìtì kan láti ọwọ́ Coalition of Buhari - Osibanjo Movement tí ó ń fẹ̀sùn kan òbí pé ó ṣe ‘ìdápadà’ àwọn ará àríwá sí ìlúu wọn .,0,yoruba ègé olóótọ fún àwọn ìkòkò tí ó jáde nìlẹ̀̀ní sáàrí ti nípa ìtànká àti ire ènìyàn.,0,yoruba Irú ẹ̀ká ojú ye ka yè. Nitori iṣẹ́ ayin. A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba Bisi Alawiye Aluko: Akọrin ẹ̀mí Bisi Alawiye ní àánú Ọlọ́run ló sọ òun di akọrin,0,yoruba nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó wáyé..,0,yoruba àmójúkúrò ni í mú ẹ̀mí ìfẹ́ gùn willingness to overlook is what makes loving relationships endure be tolerant no,0,yoruba "Gbogbo ọmọ Yorùbá, ìgbà ọ̀tun wọlé dé pẹ̀lú BBC Yorùbá https://t.co/7l56BV4el4 Omidan @user je ikan ninu awon atokun BBC Yoruba https://t.co/g5lxlJJLnO",0,yoruba Ifá ti mọ ẹni tí yóò jẹ ààrẹ Naìjíríà pẹ̀lú iyì àti ìdùnnú - Àdìmúlà Ila Orangun,0,yoruba lọ́rọ̀. ti Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa òkè: ti o ní wúlò.,0,yoruba "Gbajugbaja Asaregbayi nni, Usain Bolt ti gbe oju kuro lara ere sisa lọ sidi ere bọọlu alafẹsẹgba Gbajugba elere ori papa ọmọ ilẹ Jamaica naa, se igbaradi pẹlu awọn agbabọọlu Mamelodi to si tun la wọn lọyẹ lori awọn ọna abuja si ere sisa. Ami nla ni ifarahan Usain bolt ninu ikọ Mamelodi Sundowns jẹ fun idagbasoke ere bọọlu alafẹsẹgba nilẹ Afirika Onigbọwọ kan naa lo nse agbatẹru asaregbayi Bolt ati ikọ agbabọọlu Mamelodi Sundowns, to si jẹ wipe, laifọtape, awọn mejeeji yii lo ti tayọ ninu ohun ti wọn yan laayo. Ami ẹyẹ goolu mẹjọ ni Usain bolt ti gba bọ wa sile lati idije ere idaraya Olympic, eyi to fẹẹ se kongẹ afojusun awọn ikọ Mamelodi, tawọn naa nlepa ami ẹyẹ liigi kẹjọ nilẹ South Africa. Usain Bolt yoo maa gbaradi pẹlu ikọ Mamelodi Sundowns titi di osu kẹta ọdun ""Odu ni ikọ agbabọọlu Mamelodi, inu mi si dun pupọ lati bawọn dowo pọ. Lootọ, mi o lee sọ bi mo ti se yara si pẹlu bọọlu sugbọn bo pẹ, bo ya, emi naa maa de oju iwọn lẹnu rẹ."" Usain Bolt ni, sise igbaradi pẹlu ikọ Mamelodi sundowns ti si oun loju lati rii pe ere ori igi nikan ni ẹdun oun lee saa, ati pe omi nbẹ laamu fun oun lori ọrọ ati gba bọọlu jẹun. Ireti awọn agbabọọlu Mamelodi Sundowns ni pe Usain Bolt lee tọwọ bọ iwe adehun pẹlu ikọ agbabọọlu naa. ""Maa sa gbogbo ipa lati rii daju pe ara mi tete bọ sipo ki n lee dara pọ mọ ẹgbẹ agbabọọlu Borrusia Dortmund ni osu kẹta ọdun. Ninu ọrọ rẹ, agbabọọlu ikọ Mamelodi Sundowns kan, Percy Tau ni, iriri nlanla lo jẹ fun asaregbayi ọmọ ilẹ Jamaica naa lati darapọ mọ awọn.",0,yoruba "ayin. Nitori eyi, ara eni lo ni ìgbà mi owó àkokò, Ọba ri Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba "ojú kakaaki. Nitori eyi, ara eni lo je ti ibile.",0,yoruba Àkójú ọ̀rọ̀ yi kún fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde sí ara ilẹ̀. (Item 127),0,yoruba Ekiti 2022: Kìí ṣe gómínà nìkan ni Ekiti nílò báyìí fún ọjọ́ ọ̀la tó dára- Oluwole Oluyede,0,yoruba "Beeni ti enia ba si ti ri oloro eni oluware yoo di sorosoro""""""""""""""""@user: Awo ti ri awo, olongini ti ri omo ekun,kajo ma se ere o • """"""""""""""""@user",0,yoruba "èwe. Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.",0,yoruba "tèmi. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Ìdá ààdọta o lé ní Mnangagwa fí tayo alátakò rẹ̀ níbí ìdìbo náà Àjọ elétò ìdìbò Zimbabwe sàlàyé pé nínú àwọn ẹkùn mẹ́wàá, Mnangagwa jáwé olúborí nínú ìdá ààdọ́ta ó lé tí adarí ẹgbẹ́ alátakò rẹ̀ Nelson Chamisa sí ní ìdá ogójì àti díẹ̀. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí: Olùdíje gbé APC lọ sílé ẹjọ́ nítorí èsì ìbò Ìbaàrún pe ọdún kan Irú ẹ̀dá wo ni Fẹla Jẹ́? Mnangagwa tó wá láti inú ẹgbẹ́ òṣèluú Zanu-PF, gbàjọba gẹ́gẹ́ bí ààrẹ nínú oṣù kọkànlá ọdún tó kọjá lọ́wọ́ Robert Mugabe. Nínú ọ̀rọ̀ Mnangagwa tó fí ṣọwọ lórí àtẹ̀jíṣẹ́ twitter rẹ̀, o ní ìjáwé olúborí òhun jẹ́ kí òhun tí ní ìrẹ̀lẹ̀ síì Alága ẹgbẹ́ òṣèlú MDC sọ pé kò sí àrídájú ìbò ti wọn kà nítorí ọlọ́pàá ló wá gbé ọ̀pọ̀ ọmọ ẹgbẹ́ alátakò kúro níbi tí àwọn elétò ìdìbò tí ń ka ìbò léyìn èyí ní àwọn ọmọ ẹgbẹ́ alátakò gba ìgboro Harare lati fẹ̀honú han pé màgòmágò wáyé nínú ìdìbò náà, tí ènìyàn mẹ́fà sì ti gbé ẹ̀mi mì. Ìdìbò yíì ní orílẹ̀-èdè Zimbabwe lò láti mú àláfìà padà bọ̀ sípò ní orílẹ̀-èdè náà Ìdìbò yìí ní àkọ́kọ́ lẹ́yìntí wọn yọ Mugabe ẹni ọmọ ọdún márùn-ùn lé láàdọ́rùn kúrò nípò ààrẹ lọ́dún tó kọjá.",0,yoruba @user Mo kúkú ń dúró de ọjọ́ náà,0,yoruba "Oludari ileeṣẹ naa, Abayomi Omomuwasan toun naa farahan niwaju igbimọ aṣedajọ ipinlẹ Eko lori awọn iṣẹlẹ pataki to waye lọjọ Aje fi apoti kan han igbimọ naa eyi to ni ẹrọ ayaworan CCTV wa ninu rẹ to ya fidio gbogbo nkan to ṣẹlẹ ni Lekki Tollgate lọjọ ti wọn yinbọn. Ṣugbọn o ṣalaye pe fidio naa to n wo gbogbo ohun to nṣẹlẹ dede duro ni dede ago mẹjọ alẹ eyi si ni dedee akoko ti iroyin sọ pe ibọn yinyin bẹrẹ. O ni idi ti kamẹra naa fi dakẹ iṣẹ ni pe tori irinṣẹ ti wọn so o mọ ti ni iṣoro nibikan. Wọn ko tilẹ fi fọnran naa han igbimọ tabi araalu loni ti wọn mu u lọ siwaju igbimọ lẹyin ọrọ ti wọn sọ. Bakan naa, Abayomi ni fidio naa ko ni ọrọ labẹ tori awọn kan fi n wo igbokegbodo ọkọ ni... Ọrọ ti pọ bayii lori fidio to wa lori ọrọ ẹrọ ayaworan CCTV gẹgẹ bi iroyin ṣe n fo kiri pe wọn mọọmọ yọ ẹrọ ayaworan ọhun kuro ni Tollgate ṣaaju akoko ti wọn bẹrẹ si ni yinbọn ni. Nigba to n fesi si ibeere, oludari ileeṣẹ naa gba pe wọn yọ ẹrọ ayaworan kuro eyi ti wọn n lo lati fi mọ awọn ọkọ to kọja laarọ ọjọ iṣẹlẹ ibọn yinyin naa. Ọgbẹni Omomuwasan ba sọ fun awọn araa igbimọ ọhun pe ki ẹrọ ayaworan naa ṣi wa lọwọ ile ẹjọ. Ẹwẹ, nipa ti ina ti wọn ni o dede ku ni Lekki Tollgate, o ni ko sẹni to pa ina. O ni ohun to ṣẹlẹ ni pe awọn oṣiṣẹ awọn ni ko tan ina naa silẹ ki wọn to lọ sile nitori konileogbele to wa lode nipinlẹ Eko eyi ti ijọba Eko kede lọjọ iṣẹlẹ yii gangan. Tani àwọn ọ̀dọ́ méjì tí yóò darapọ́ mọ́ igbimọ́ iwadii iṣẹlẹ́ Lekki ní Eko? Lẹyin ifikunluku ati idibo lori ayelujara, agbarijọpọ ẹgbẹ ajafẹtọ ti forukọ ọdọ meji ranṣẹ ni Eko lati jẹ ọmọ igbimọ iwadii to n tọ pipin iṣẹlẹ ikọlu to waye ni Lekki. Lara iṣẹ igbimọ yi ni ki wọn ṣe akojọ ẹsun, fi ọrọ wa awọn eeyan lẹnu wo ki wọn si tun fi idi ododo mulẹ lori ifiyajẹni tabi ipaniyan. Orukọ awọn meji ti wọn yan yi ni Rinu Oduala ati Majekodunmi Oluwaseun. Ṣaaju ki a to bẹrẹ si ni gbe iroyin igbẹjọ igbimọ yii, a ni ki a se atupalẹ iroyin nipa awọn ti wọn yan lati ṣoju ọdọ ati iru akitiyan wọn to mu ki ipo yi tọ si wọn. Rinu Oduala Bi ẹ ba ti n fọkan ba iwọde ENDSARS bọ, yoo ṣoro ki ẹ to ma da arabinrin yi mọ ninu awọn oluwọde ni ipinlẹ Eko. Oduala Olorunrinu kii ṣe ẹni to ga pupọ ṣugbọn bi eeyan ba foju di i, yoo kan idin ninu iyọ. Ajafẹtọmọniyan yi to lewaju paapa ni ile ijọba ni Eko wa lara awọn to kọkọ gbe igba iwọde ki awọn gbajumọ mii to wa darapọ mọ wọn. Rinu jẹ akikanju ti ko fi igba kankan tura silẹ lori ṣiṣe deede laarin ijọba ati ara ilu. Akọṣẹmọṣẹ ni o jẹ nipa biba eeyan polowo ọja loju ayelujara ti a si tun maa da si ọrọ to ni ṣe pẹlu mimu irọrun ba ara ilu. Loju opo rẹ ni Twitter ati Instagram, orisirisi aworan lo wa nibẹ lawọn ibi to ti n kopa ninu iwọde. Lasiko ti wọn bẹrẹ si ni ro wipe o yẹ ki awọn oluwọde ni aṣoju, o wa lara awọn ti wọn dibo yan lori ayelujara ki o to wa pada laanfaani ati jẹ ọmọ igbimọ iwadii. Majekodunmi Temitope Oluwaseun Arakunrin yi ni ẹnikeji ti wọn yan lati ṣoju awọn ọdọ ninu igbimọ iwadii nipinlẹ Eko. Bii ti Rinuola, Temitope naa jẹ ọdọ ti o mu jijafẹtọmọniyan ni ọkunkundun. Loju opo rẹ ni Twitter, o fi ọrọ idupẹ imoore awọn to yan sipo gẹgẹ bi aṣoju ọdọ. O gba ladura pe ki awọn maa ṣe ja ireti awọn to yan wọn sipo kulẹ. Kini awọn ọdọ sọ nipa iyansipo yi? Loju opo Twitter niṣe lawọn ọdọ n fi ọrọ iwuri ranṣẹ si awọn aṣoju wọnyi. Ninu awọn to fi ọrọ adura ati iwuri ranṣẹ ni ilumọọka gbajumọ nii Falz ati awọn mii wa to ni ki awọn aṣoju yi ma gbabọde. Ijoko igbimọ yi yoo maa waye ni gbogbo ọjọ Iṣẹgun,ọjọ Ẹti ati ọjọ Abamẹta ni ile ẹjọ apẹtusaawọ ipinlẹ Eko to wa ni 1A, Remi Olowude Street, Maruwa Roundabout, Lekki. Aarẹ Muhammadu Buhari ti sọrọ nipa igbimọ yi to si ni ''oun wa lẹyin igbimọ naa bi ike'' Aarẹ sọ pe oun ni gbagbọ pe igbimọ yi yoo jẹ ki awọn oluwọde ati ọlọpaa to padanu ẹmi wọn ri idajọ ododo gba.",0,yoruba Africa Eye: Ọmọ ìgboro méje tó ń jò tà di aláṣeyọrí,0,yoruba ènìyàn a yi fi ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba "Èèyàn méjìdínlọ́gbọ̀n ni wọ́n ti yọ láàyè lábẹ́ àwókù ilé alájà náà Gomina Wike ni gbogbo awọn to lọwọ si kikọ ile naa ni wọn yoo fi jofin. O kere tan ẹmi mẹfa lo ba iṣẹlẹ naa rin, ti awọn miiran si fi ara pa. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ""Ẹnikẹni to ba buwọlu ile yii, pẹlu gbogbo awsn ti o lọwọ ninu kiks ọ rẹ ni yoo foju wina ofin."" Gomina Wike to ṣe abẹwo si ile to wo naa ni ọjọ aiku ṣalaye gbogbo awọn oṣiṣẹ ijọba to lọwọ ninu rẹ pẹlu yoo jẹ iya gbogbo to ba tọ. Eniyan mẹfa lo ti ku ninu ijamba ile naa Wike wa rọ awọn oṣiṣẹ adoola ẹmi to n ṣiṣẹ nibẹ lati maṣe kaarẹ titi ti wọn yoo fi yẹ tibu t'oro awoku ile naa lati doola ẹmi awọn ti o ṣi lee wa nibẹ. Titi di asiko yii, eeyan mejidinlogoji ni wọn ti ko jade laaye labẹ awoku ile naa, ṣugbọn eeyan mẹfa miran ti ku. Akọ̀ròyìn BBC tó dé bẹ̀ ní ènìyàn kan ló ti gbẹ́mìí mì tí wọ́n sì ti gbé àwọn mọ́kànlélógún tó fara pa lọ ilé ìwòsàn PortHarcourt pàdánù ọ̀gọ̀ọ̀rọ̀ ẹ̀mí nínú ilé tó wó lulẹ̀ Ẹbí àwọn tó fara gbá níbi ìṣẹ̀lẹ̀ ilé alájà méje tó wó ní ìlú PortHarcourt sọ fún BBC pé àwọn ènìyàn kan ṣì wà lábẹ́ ilé náà tó wó lọ́jọ́ kẹtàlélógún oṣù kọ́kànlá. Ènìyàn kan ló ti bá ìṣẹ̀lẹ̀ náà rìn tí àwn adóòlà ẹ̀mí sì ti yọ ènìyàn méjìlélógún báyìí. Ile alaja meje, Port Harcourt Ilé wo pà 'yàn meji l'Èkó Ilé gogoro tí owó àgbẹ̀ kọ́ Àwọn òṣìṣẹ́ adóòlà ní lọ́jọ́ ẹtì ni àwọn yọ ẹni tó kú jáde tí wọ́n sì yọ ọkùnrin kan tí apá rl gé níbí ìṣlll náà ní agogo mẹ́rin òwúrọ̀ ọjọ́ àbámẹ́ta. Ilé alájà méje náà tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ ń kọ́ lọ́wọ́ wó lulẹ̀ ní ọ̀nà Woji, GRA ní ìlú Port Harcourt tíi ṣe olú ìlú ìpínlẹ̀ Rivers. Ènìyàn tí wọ́n dóòlà Àwọn tó fojú rí ìṣẹ̀lẹ̀ náà ní ó ṣẹlẹ̀ ní ǹkan bíi agogo márùn ún ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ ẹtì nínú èyí tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ alágbàṣe àti àwọn ọlọ́jà pẹ́pẹ̀pẹ́ há sí. Ní ǹkan bí agogo mẹ́jọ alẹ́ ọjọ́ ẹtì, wọ́n ti rí ènìyàn mọ́kànlélógún yọ wọ́n sì ti ń gba ìwòsàn báyìí. Àwọn ènìyàn níbi ìṣẹ̀lẹ̀ náà Àkọ̀ròyìn BBC tó dé 'bi ìṣẹ̀lẹ̀ náà fàbọ̀ jẹ́ni pé àwọn òṣìṣẹ́ elétò ìlera, òṣìṣẹ́ panápaná, ẹgbẹ́ alámì àgbélébùú àtàwọ́n òṣìṣẹ́ aláàbò míì ti wà níbẹ̀ láti túnbọ̀ dóòlà ẹ̀mí àwọ́n tó ṣì há sábẹ́ ilé náà. Àwọn ènìyàn níbi ìṣẹ̀lẹ̀ náà",0,yoruba everything god created is good and awesome gbogbo oun ti olorun da dara dara ni,0,yoruba "Bi awọn ọmọ ogun naa, ti wọn jẹ ẹṣọ to n tẹle ọkọ agboworin, ṣe ri aaye gbe owo naa salọ, ko sẹni to mọ. Amọ ẹnikan nileesẹ ologun fidi rẹ mulẹ fun BBC pe, owo nla kan ti sadeede poora, ati wi pe, wọn ti fi iṣede se ọgagun kan mọle rẹ, ko gbọdọ fi ile rẹ silẹ nilu Abuja. Osisẹ ologun kan, Onyema Nwachukwu, to ba awọn akọroyin sọrọ lọjọ Iṣẹgun ni olu ileeṣẹ ologun fidi rẹ mulẹ pe iwadii nlọ lọwọ , pẹlu afikun pe, ""abajade iwadii naa yoo di mimọ fun araalu ti asiko ba to."" Awọn ipẹẹrẹ ọmọ ologun maarun la gbọ pe wọn ji owo naa gbe. Bi iroyin kan sọ pe, owo naa to yẹ ki wọn fi gbọ bukata ileeṣẹ ologun ni, ni omiran sọ pe ,ọga ologun kan nigbakan ri lo ni owo naa. Iroyin sọ pe, awọn ọmọ ogun naa tẹle ọkọ agboworin kan to gbe owo naa lati ilu Sokoto si Kaduna, lati pese aabo fun. Asiko ti wọn si n lọ lọna ni wọn ja ọkọ gba, wọn bọ aṣọ ọmọ ogun kuro lọrun un wọn, wọn si salọ. Owo kekere kọ ni ijọba maa n ya sọtọ fun ileeṣẹ eto aabo ninu owo iṣuna lọdọọdun, ṣugbọn awọn ọmọ ogun to wa ni oju ija, paapa, awọn to n doju kọ ikọ Boko Haram, maa n fi gbogbo igba pariwo pe, awọn ko ni irinṣẹ, awọn ko si ri owo ajẹmọnu gba.",0,yoruba "lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba "Ààrẹ àti oníròyìn ọ̀hún rán mi l'étí nípa “ ọkọ̀ tó léfòó lórí irọ́ """""""" .",0,yoruba "àkerekere, Ọba ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..",0,yoruba Àwọn àmì-ìwé Galeon/Konqueror,0,yoruba "Jìjìn ọ̀pọ́lọ̀ ni ìbàdandun àtọ́wọ́dá, àwọn oníṣẹ́ ìṣẹ́ ni ohun tí ó wáyé..",0,yoruba Russia Boxer: Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò dágbére fáyé lásìkó ìjà rẹ,0,yoruba "Inú igbó ni Òṣóòsì fi ṣelé, ni ó fi mọ orúkọ tí ewéko àti ẹranko ń jẹ́. Etí odò sì ni ó ti ń na 'jú, ni ó fi di apẹja. #Isese #Yoruba",0,yoruba "onà. ti Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Nitori eyi, ara eni lo ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.",0,yoruba "Nígbà tí Ìyá fè fi, A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà.. Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba Gẹ́gẹ́ bí ẹ ti ṣe mọ̀ pé ilà kan gbọọrọ kékeré lẹsẹ̀ ń tọ̀ lọ́nà k'ó tó di gbalaja. #OleBini #Yoruba,0,yoruba bàbá kérésì ń gún yán ta ní fẹ́ jẹ,0,yoruba "Ní ọjọ́ 21 , àwọn ọlọ́pàá sọ fún àwọn òbíi Deng láti máà gba agbẹjọ́rò fún un .",0,yoruba "Manchester city gba idagiri akọkọ ni saa bọọlu tuntun ti yoo bẹrẹ nilẹ Gẹẹsi lọsẹ to nbọ pẹlu bi Liverpool ṣe ko bo wọn ni ifẹsẹwọnsẹ ife ẹyẹ Community Shield to waye lọjọ Abamẹta. Goolu mẹta si ẹyọ kan ni Liverpool na Manchester city lati gba ife ẹyẹ Community Shield, eyi to jẹ ife ẹyẹ akọkọ lati ṣide saa bọọlu Premier league lọdọọdun lorilẹede England. Liverpool padanu ife ẹyẹ Premier league saa to kọja si ọwọ Manchester City to gba ife ẹyẹ naa lẹyin to fi ami kan la Liverpool. Idije naa to waye ni papa iṣire King power stadium dipo Wembley nitori ifẹsẹwọnaẹ aṣekagba idije ife ẹyẹ Euro tawọn obinrin ti yoo waye nibẹ. Agbabọọlu Liverpool, Trent Alexander-Arnold lo gba goolu akọkọ wọle lẹyin ti bọọlu gba soju ile ba ara Nathan Ake, agbabọọlu Manchester city wọle. Julian Alvarez, ọkan lara awọn agbabọọlu tuntun ti Manchester city ṣẹṣẹ ra lo gba goolu wọle lati daa pada fun Liverpool. Agbabọọlu ọmọ orilẹede Egypt ni, Mohammed Salah lo tun sun Liverpool siwaju pẹlu pẹnariti lẹyin ti ọkan lara awọn adilemu Manchester city, Ruben Dias fi ọwọ kan bọọlu loju ile rẹ. Agbabọọlu tuntun ti Liverpool ṣẹṣẹ ra, Darwin Nunez lo de gbogbo rẹ lade.",0,yoruba "àkokò, Olùwo ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Nasarawa ti fidirẹmulẹ fun BBC pe o ku lẹyin ti awọn agbebọn ji i gbe lọjọ Satide. Agbẹnusọ fun awọn ọlọpaa nipinlẹ naa, ASP Rahman Nansel sọ pe wọn ti gbe oku rẹ lọ si ileewosan, nitori iwadii ṣi n tẹsiwaju. Owurọ ọjọ Aiku ni BBC gbọ iroyin pe awọn agbebọn kan ji alaga ẹgbẹ osẹlu APC gbe. Awọn ọlọpaa sọ pe ni nkan bi aago mọkanla, alẹ Satide ni wọn wọ inu ile rẹ, ti wọn si gbe e salọ. Ati pe ni kiakia ni awọn lọ si ile naa, ti awọn ati awọn agbebọn naa si jọ doju ija kọ ara wọn, amọ wọn papa ri gbe lọ. Ọjọ Aiku si ni wọn ri oku rẹ nibi ti ko jina si ile rẹ. ASP Nansel sọ pe bi awọn ṣe jọ doju ibọn kọ ara awọn fihan pe awọn agbebọn naa pọ gan-an. Iṣẹlẹ ijinigbe ko ṣẹṣẹ ma a waye ni apa Ariwa Naijiria, ati awọn ibomii. The New Pandemic: Kíni àwọn onímọ̀ sáyẹ́ńsì ń sọ nípa rẹ̀?",0,yoruba "fi. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba aráyé: ti o nuni ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba Dejo Tunfulu: Ẹ wo bí Dejo Tunfulu tó dágbéré fún ayé ṣe bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ òṣèré...,0,yoruba "Iwacu ṣàlàyé wí pé àwọn akọ̀ròyìn náà lọ síbi ìṣẹ̀lẹ̀ náà lẹ́yìn tí àwọn aláṣẹ tí fi léde , wọ́n gba ìwé àṣẹ kò sì sí òfin tí ó ní kẹ́nìkan ó máa dé agbègbè ìṣẹ̀lẹ̀ náà .",0,yoruba aláìì dé sí ìbàdandun láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò.,0,yoruba Agbagba pelu Oloye Elesho lori #NigbatiTV #Yoruba #YorubaCulture https://t.co/dfZmRY02hX,0,yoruba Ọba lọ. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún gbogbo.,0,yoruba Àkóbì níjó òní nípa ọ̀rọ̀ ìlú ni nfàn ojú kakaaki.,0,yoruba lojiji. Bàbá lo ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba jésù wọ ìlú jerúsálẹ́mù lónìí ewé igi ọ̀pẹ ni ọmọ màríà olùgbàlà aráyé tẹ̀ wọ̀lú èyí nìdí ọjọ́ àìkú ọ̀pẹ,0,yoruba "Igba mi owó àkokò, Alàji lo se. Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "fi. Nitori eyi, ara eni ni nfàn ojú kakaaki.",0,yoruba afago kẹyin aparo ohun oju nwa loju nri,0,yoruba ORI KERINDINLOGOJI: ÈTÓ ÌGBÓTENU ENI KI ATO DÁJÓ (GBO TI IDA KEJI) #Law2go #HumanRightsinNigeria #Section36 #Yoruba,0,yoruba "ÀFIN ÌṢẸ̀M̀BÁYÉ ÀKÚRẸ́ Ní àsìkò 1150 ni wọ́n kọ́ àfin náà. Ọba mẹ́ta dín l'áàdọ́ta (47) ni ó ti gun orí ìtẹ́ nínú àfin yìí, láti orí ọba àkọ́kọ́, ọba Ọ̀mọrẹ̀mílẹ́kún Aṣọdẹbóyèdé. Wọ́n ṣì ń lo àfin náà, fún àwọn ètùtù oríṣi kan. Àwòrán: Tribune online https://t.co/YajhhkoaxB",0,yoruba ẹ̀yin tí ẹ ò ṣòpò gbìyànjú iyè ti yín náà ò ní ra o yóò máa lékún síi ni lágbára ọba amòye,0,yoruba iṣẹ́ ni ìwájú lojiji. Bàbá lo tun se mú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba RT @user: Ìgbé ò léegun sùgbón ení bátèé á tiro #TweetYoruba,0,yoruba Mo kí gbogbo èyàn wa l'ókè òkun àti lẹ́hìn odi gbogbo. Ẹkú àìgbàgbé ilé o.,0,yoruba "Ṣe ẹ ranti Baba Onilu Ibadan ti ọdọkunrin agunbanirọ ya fọto rẹ to si ta a lori ayelujara fi pa miliọnu kan naira? BBC Yoruba ti wa àti baba onilu ati agunbanirọ naa kan lati fọrọ wa wọn lẹnu wo. Baba naa, Adeniji Ayangbenle jẹ agbalagba to maa n lọ kaakiri ibi inawo tabi apejọpọ lati lu ilu fi gba owo. Agunbanirọ naa, Adisa Olashile ni awọn n ṣe iṣẹ ilu lọwọ gẹgẹ bi agunbanirọ tawọn si ṣẹ pari ni baba wa lu ilu fun awọn. Ọlọ́run mi ló ní kí n bèèrè fún N310,000 lọ́wọ́ àwọn ọmọ ìjọ mi láti kó wọn lọ sí ọ̀run - Pásítọ̀ Noah Abraham Àgùnbánirọ̀ ya fọ́tò Bàbá Onílù láti tà á, òjò owó rọ̀ fún bàbá Kàyèéfì! Ẹ wo ẹni tó ní ìpèníjà ojú tò ń tún ẹ̀rọ̀ ńlá tó ń sọ omi di yìnyín ṣe Bí wọ́n ṣe pa Sójà méjì tó ń lọ fún ìgbéyàwó ara wọn ní ìlú Ìgbà mélòó ló yẹ ko máa pàrọ̀ ‘bedsheet’ rẹ? Wo ǹkan 21 tó yẹ kí obìnrin mọ̀ nípa ojú abẹ́ rẹ̀, Vagina ""Ọrẹ mi fun baba ni N100 amọ emi o ni owo ti mo le fun wọn, mo wa fi anfani pe ọrẹ mi ti fun baba ni ọgọrun naira, mo fi ya fọto baba"". Bi ọrọ fọto lasan ti baba ro pe Adisa ni ki oun rẹrin niwaju igi elewe ṣe di eyi to sọ baba di oloriire niyẹn. Adisa sọ fun baba pe oun yoo pada wa o si ṣe bẹẹ. O ri anfani lati ta fọto naa lorii aapu ori ayelujara kan ti wọn n pe ni Open Sea gẹgẹ bi ẹda aworan NFT eyi to tumọ si iṣẹ ọna to dara. Baba Ayangbenle sọ pe ojoojumọ ni oun maa n ṣe adura fun ọmọ Agunbanirọ to mu inu oun dun. Amotekun Ondo fi ṣìkùn òfin mú afurasí 37 lórí ẹ̀esùn ìjínigbé, ìdigunjalè àtàwọn ẹ̀sùn míì Èmi nìkan ni ikú Alaafin dùn jù ní gbogbo ayé yìí torí èmi nìkàn ṣoṣo ni mo mọ̀ ǹkan ... - Baba Kekere",0,yoruba pe nilo ayẹwo wey ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba "Àṣìlò èròjà codeine àti awọn òògùn mi i maa n ṣe àkóbá fún ara Eyi waye lẹyin ayẹwo atigbadegba kan ti ajọ to n mojuto ipese ounjẹ ati oogun lilo ni Naijiria, NAFDAC, ṣe. Igbesẹ naa gẹgẹ bi minisita fun eto ilera, Ọjọgbọn Isaac Adewọle ṣe sọ, jẹ ọna lati ti tubọ fi ipinnu ijọba apapọ lati f'opin si aṣilo oogun ikọ olomi to ni codeine ninu, ati awọn oogun mi i l'orilẹede Naijiria han. Fídíò òògùn ikọ́ Codeine: Àpọ̀jù rẹ̀ ń ya ọ̀dọ́ ní wèrè Iwe iroyin Nigerian Tribune jabọ pe, Ọjọgbọn Adewọle sọ eyi di mimọ nilu Abuja lasiko to n tẹwọ gba abọ iwadi igbimọ ti ileeṣẹ eto ilera gbe kalẹ lati mojuto aṣilo oogun ikọ olomi to ni eroja codeine ninu. Abọ iwadi naa fihan pe ogún ninu mẹtalelogun awọn ileeṣẹ to n ṣe oogun oyinbo ti wọn ṣe ayẹwo si lo jẹbi ọrọ naa. Ati pe ibudo ti awọn ileeṣẹ naa n ko awọn ọja wọn si ni ọwọ ti tẹ awọn oogun ikọ naa.",0,yoruba "Ṣàṣà lọmọdé tí kì í fẹ́ràn láti mu èso yìí, àwọn àgbàlagbà alára fẹ́ràn-an rẹ̀ ẹ́ pọ̀, nítorí adùn un ẹ̀. #Agbalumodun🍊 👌",0,yoruba RT @user: @user Rara ko si o,0,yoruba "RT @user: Ọba tí kì í fẹ́ gba ìmọ̀ràn, irú wọn kì í pẹ́ fi ẹsẹ̀ kọ. / Any king who despises wise counsel, hardly takes long befo…",0,yoruba "Baalu naa ti awọn alaṣẹ ni o gbe eeyan mọkanlelaadọsan ati awọn oṣiṣẹ baalu mẹfa ja lulẹ ni papakọ Sabiha Gokcen to wa ni Istanbul. Minisista feto irina Mehmet Cahit Turhan sọ pe ko si eeyan kankan to ku ninu ijamba ọhun. Bẹẹ naa ni Gomina Istanbul,Ali Yerlikaya sọ pe wọn ti ṣaaju sare gbe eeyan mọkanlelogun lọ si ile iwọsan toun ti bi awọn oṣiṣẹ pajawiri ṣe n ba iṣẹ lọ. Awọn iwe iroyin ilẹ Turkey jabọ pe lasiko ti ojo n rọ ni baalu ti ile iṣẹ ọkọ ofuurufu Pegasus naa gbiyanju lati balẹ lyin to gbera kuro ni agbegbe iwọ oorun Izmir. Wọn ti gbe awọn ero kuro ninu baalu naa ṣugbọn awọn oṣiṣẹ pajawiri ṣi n gbiyanju lati yọ awọn to ha sinu rẹ. Lori ẹrọ ayelujara, awọn eeyan n ṣalabapin fọnran fidio kan to ṣafihan ina to n jo ninu baalu naa amọ awọn panapana pada pa ina ọhun.",0,yoruba Ọba ri Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.,0,yoruba ẹni tí ọdún bá bá láyé ó yẹ kí ó yọ̀ èyí ni gbogbo wa ní ẹ̀ka èdè ọmọlúàbí fi ń kí àwọn olólùfẹ́ẹ wa kú ọdún iléyá ọ̀pọ̀ ọdún la ó ṣe láyé láàyè lọ́láa wáhídù lókè báríkà dè salà ẹ kú ọdún o,0,yoruba RT @user: @user @user ema yo mi ni setting. Emi na ngbadun lilo ede Yoruba. Mo wa ni sepe sepe. Mo fe ko lilo ede Yoruba…,0,yoruba pa Bàbá lo ni àṣà ìdílé lo je gbogbo ise ibile tèmi.,0,yoruba "Afeez Fashola ti gbogbo eniyan mọ si Naira Marley ti gbe awo orin tuntun kan jade to n jọba oju opo ayelujara lọwọlọwọ. ẹni ọdun mẹẹdọgbọn yii ti ṣe ọpọlọpọ orin to gbode kan jade lagbo orin ni Naijiria bii 'Issa Goal' ati eyi to ṣẹṣẹ gbe jade yii 'Soapy'. Ninu fọnrán fídíò náà ti Marley fi sita loju opo Instagram rẹ, o jo iru ijo kan ti o mu ọwọ lọ si apa ibi nkan ọmọ kunrin rẹ eyi to fi n ṣapejuwe ọrọ inu orin rẹ. Ọsẹ diẹ sẹyin ni wọn tu Marley silẹ lẹwọn nibi to wa fun ọjọ diẹ latari ẹsun ole ori ẹrọ ayelujara ti EFCC fi kan an eyi ti wọn n pe ni Yahoo Boy lorilẹede Naijiria. Marley ni oun o jẹbi gbogbo ẹsun ti wọn fi kan an. Ẹwẹ lati igba ti orin tuntun yii, Soapy ti jade lawọn ọmọ Naijiria ko ti sinmi ẹnu lori ẹrọ ayelujara. Bi awọn kan ṣe n gba tiẹ ti wọn n gbe lẹyin rẹ lawọn kan n ni kii ṣe m to ṣee fi yangan. ""Emi o tilẹ ni wo fọnran orin naa rara. NAiraMarley ki lohun to n ti ẹ gbọngbọn gan?"" ""Naira Marley yii ko lọpọlọ rara, ẹni to n kọrin lodi si aidaa ijọba, lori iṣoro awọn eeyan, aidaa awnọ ọlọpaa, laasigbo, o tilẹ n ṣe bii pe o ni iru ẹmi orin Bob Marley diẹ ṣugbọn Soapy lo n kọ. Ko lawọn eeyan gidi to yi i ka."" ""Nigbẹyin gbẹyin mo ti ri orin ti mo le foju jọ, Soapy ti Naira Marley.""",0,yoruba "Muhammad Buhari , Ààrẹ orílẹ̀ - èdè Nàìjíríà .",0,yoruba "òní.. Nitori eyi, ara eni lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó ṣe pàtàkì.",0,yoruba "Stray Bullet: Bàbá ọmọ ni ogún náírà péré ni àwọn ọlọ́pàá fi lọ òun àmọ́ òun kò gbàá Baba ọmọdebinrin kan, Mariam Sobukola, ti asita ibọn ba, lasiko iwọde kan to waye lagbegbe Ipaja nilu Eko, lati tako bi ijọba se wọgile wiwa ọkada ati kẹkẹ, ti kigbe tọ BBC Yoruba wa. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Lasiko to n ba wa sọrọ, Mukaila Sobukola ni awọn ọlọpa to yinbọn mọ ọmọ oun ko tiẹ tara nipa isẹlẹ naa rara, oun nikan si ni oun n da gbọ bukata wahala yii. Sobukọla ni dokita yọ ọta ibọn lara ọmọdebinrin naa, to si fi le oun lọwọ, amọ o ni, lọjọ kẹta ni dokita tun n bẹ oun pe ki oun mu ọta ibọn naa wa pada, ti wọn ko si fun oun mọ. O fikun pe ọlọpa obinrin kan yọju si awọn sile iwosan, to si na ẹgbẹrun lọna ogun naira si awọn, amọ oun ko gbaa lọwọ rẹ, lati igba naa wa, awọn ko gbọ ohunkohun mọ.",0,yoruba ẹṣeun ó ti yé wa ọ̀rọ̀ pàtàkì lẹ sọ ọlọ́run ọba ò ní padà lẹ́hìn yín o,0,yoruba "Igba mi owó àkokò, Olùwo ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba "Apá lará, ìgúnpá ni'yèkan. Kí ni iyèkan? #ibeere #owe #Yorùbá",0,yoruba Ṣé ojú ogun ni? @user @user #EkitiDecides,0,yoruba Ìpànìyàn ní àárín àwọn ènìyàn,0,yoruba "tí Bàbá fè fi, A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà.",0,yoruba ".@user eku ori ire, abayin yo. Igba wo ni Awon oluko ati osise ile eko giga ipinle Ekiti ma gba owo osu mefa ti eje won? https://t.co/BOlPl9uwET",0,yoruba RT @user: Gbé | Gbè | Gbẹ | Gbe | Gbẹ́ • #InYoruba #learn #Yoruba #language https://t.co/FKfzBCGo8t,0,yoruba ỌJỌ́ ÌTÀN – Ikọ̀ ọkọ̀ òfuurufú,0,yoruba obìnrin a yi fi ti o ní wúlò fún gbogbo.,0,yoruba iṣẹ́: ti o nuni ti o ní wúlò.,0,yoruba "RT @user: 5. Ní ilẹ̀ẹ Yorùbá, ẹnìkan ṣoṣo ni kì í dọ̀bálẹ̀ fún ọba aláṣẹ igbá-kejì òrìṣà, ta ni ẹni náà? #Ibeere #Yoruba",0,yoruba "àti ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìṣẹ́ ọ̀pọ́lọ̀.",0,yoruba ìbàdandun láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó wáyé..,0,yoruba "RT @user: O rewa, ojoju.""""""""""""""""@user: Ẹ wo àwòrán tí mo yà lórí afárá kan. Ẹ wo bí odò yí ṣe dágún tó wá rẹwà gbáà. http://t.co/ ...",0,yoruba "Tí kì í bá ṣe ọ̀kánjúwà, omi òkun tó láti mu gààrí. If It is not for greed, the ocean water is enough for someone to drink garri.",0,yoruba "àwọn oníṣẹ́ ìṣẹ́ ni a ní nípa ire àti ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn ẹ̀kọ́ ọmọ aláwọ̀ wà níṣẹ̀.",0,yoruba "RT @user: @user @user E seun, modupe. E ba mi ki o. E so fun wipe inu wa dun gan ni @user fun kiki re.",0,yoruba 2020 Prayer by Leguru Ajisa at Ile Aje (Wealth Shrine ) in London Taju Bello Aseyi Shamodun lagbara Edumare Amii Ase Koikimedia bringing the world closer to your doorsteps 1st January 2020 #culture #yoruba #Africa #African #nigeria https://t.co/Y9puoXFZFi,0,yoruba olóótọ fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ẹkọ́: ti o dara.,0,yoruba "Tí lágídò bá ńfò láti orí igi kan sí èkejì, àwọn tó ńwòó ló rò pé eré ló ńṣe; òun fúnra ra rẹ̀ mọ̀ pé akọ iṣẹ́ lòun ńṣe @user #Yoruba",0,yoruba "RT @user: @user asa kasa ti awon eyan ko ni odo awon oyinbo tiko mu ogbon wa, koda rara,atipe ounse okunfa alebu ati arun",0,yoruba "Bí Adeleke bá lé àwọn alága ìbílẹ̀ tuntun, ilé aṣòfin yóò yọ òun náà nípò gómìnà - APC Osun",0,yoruba "Lánàá òde yìí, lórí afá kẹta Èkò ọmọ mú aboyún kan, o rọbí, wọ́n gbẹ̀bí ẹ̀, ó sì sọ̀ láyọ̀. Ní'fẹ̀, orúkọ ọmọ bẹ́ẹ̀ yíó máa jẹ́ 'Abíọ́nà'",0,yoruba fi. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba ọsẹ àlùfáà. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba "Ọyẹ́ ti dé apá ọ̀dọ̀ wa ní Nàìjíríà, báwo ni lọ́dọ̀ tiyín? Harmattan is here... How's it at your end? #Season #Harmattan #Ọyẹ́ #yoruba https://t.co/iCv1SroK0F",0,yoruba @user bóo lònìí o? Á dára fún wa :),0,yoruba "Eyi ni idajọ ileẹjọ kotẹmilọrun niluu Abuja lori ẹjọ ti Maryam Sanda ti ileẹjọ gíga ti dajọ iku fun tẹlẹ lori ẹsun pe o gun ọkọ rẹ pa. Ileẹjọ naa sọ pe ko si ohun kan to f'ẹsẹ mulẹ ninu ẹjọ ti Maryam pe. Nitori naa, oun naa gbọdọ ku nipa sisọ okun sí lọrun lẹyin to jẹbi ẹsun pe o gun ọkọ rẹ, Bilyamimu Bello ti ṣe ọmọ alaga gbogbo ẹgbẹ oṣelu PDP tẹlẹ, Haliru Bello pa. Amọ, agbajẹro Maryam, Joe Gadzama (SAN), tí ṣọ pe awọn yoo gbe ẹjọ naa lọ si ileẹjọ to ga julọ ni Naijiria. Bakan naa, agbẹjọro ileeṣẹ ọlọ́pàá, James Idachaba gboṣuba fún ileẹjọ lori idajo rẹ. Kayeefi: 'Ọkọ mi ṣẹ̀ṣẹ̀ ní kí n lọ se mọ́í-mọ́í, tó ṣẹ̀ bá mi ṣeré tán ni mo gbọ́ pé ""Mopol"" yìnbọn pa á' Ọgbẹni Idachaba ni awọn naa ṣetan lati pade Maryam ati agbẹjọro rẹ nile ẹjọ to ga julọ. Niiṣe ni Sanda bu s'ẹkun gbagada lẹyin ti adajọ ka idajọ rẹ tan. Amọ, Sanda ni adajọ Yusuf Halilu ṣegbe lẹyin ẹnikan ninu idajọ rẹ, nitori naa oun ṣetan lati gbẹjọ oun lọ si ileẹjọ to ga julọ ni Naijiria.",0,yoruba Dare Adeboye: Ọ̀pọ̀ ọmọ ìjọ RCCG ń ṣèrántí olóògbé Pásítọ̀ náà lẹ́yìn ọdún kan to jáde láyé,0,yoruba "kan. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "O mọ ẹní mọ ọkọ̀ọ́ wà; Ajah » oko Ado » sangotedo, ilé-iṣẹ́ olómi inú ọ̀rá kan ń wá awakọ̀. Pe 09095322018 | """"""""""""""""@user",0,yoruba "tó kún jú, àwọn ènìyàn ni ó pa Ọmọ lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni A.",0,yoruba Owo oṣu tuntun fawọn oṣiṣẹ Igbesẹ naa waye lẹyin ti igbimọ to n ri si alekun owo oṣu oṣiṣẹ tuntun jabọ fun ile. Gbogbo ile lo fọwọ si pe ki ijọba bẹrẹ si san ẹgbẹrun lọna ọgbọn naira gẹgẹ bi owo oṣu tuntun fun oṣiṣẹ to kere julọ fawọn oṣiṣẹ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Falana: Awọn to n dije dupo ìdìbò 2019 fẹ́ fa ogun si Naijiria Eleyi wa ni ibamu pẹlu aba ti igbimọ ti Aarẹ Muhammadu Buhari gbe kalẹ lati ṣiṣẹ lori alekun owo oṣu tuntun fawọn oṣiṣẹ da. Aarẹ Buhari ti kọkọ fọwọ si ẹgbẹ mẹtadinlọgbọn naira tẹlẹ ṣugbọn awọn oṣiṣẹ kọ jalẹ pe ẹgbẹrun lọna ọgbọn naira lawọn yoo gba gẹgẹ bi owo oṣu oṣiṣẹ to kere julọ.,0,yoruba "mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba Ọkan tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó ṣe pàtàkì.,0,yoruba "Ọmọ fè mú, Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba ìdílé. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba èkó aṣà. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba oruko mi ni simileoluwa omo abi mi si onipanu ni ipinle eko omo eko ni awon obi mi omo rere ni mi e ka ro,0,yoruba Ìyè ni Ara - jíjẹ àti ẹ̀jẹ̀ mímu .,0,yoruba Gómìnà Zamfara ní kò sí ìdáríjí fún àwọn jàndùkú mọ́ ní ìpínlẹ̀ òun,0,yoruba Nse Ikpe-Etim sọ̀rọ̀ lórí ìpènijà rẹ̀ lẹ́yìn tó pàdánù ilé ọmọ rẹ̀,0,yoruba àwọn irúnmọlẹ̀ wọnnì ni elédùmarè ń bẹ̀ lọ́wẹ̀ tí ń ṣiṣẹ́ fún n mélòó wá ni wọ́n,0,yoruba "ègé olóótọ fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba "ìbadandun. Nitori eyi, ara eni lo ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..",0,yoruba kabiesi o lapoka,0,yoruba Ọkan tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọba lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun.,0,yoruba "Oṣerebinrin to gbe sinima Ikú Ni jade, Olufunmi Bakare, ti tọrọ idariji lọwọ awọn ẹlẹsin Islam ti sinima naa bi ninu. Saaju ni ẹgbẹ́ ajafẹtọ ẹsin Musulumi kan, Ta'awunu Human Rights of Nigeria, THURIST ti fi ẹhonu han lori sinima naa ti wọn lo tabuku bá ẹsin awọn. Ninu sinima naa ni wọn ti safihan obìnrin ẹlẹha kan to ya were, to si n hu iwakiwa. Eyi si lo mu ki ẹgbẹ THURIST fi ikilọ ati idunkooko sita fun Odunlade Adekola, to jẹ ọkan lara awọn oṣere to kopa ninu sinima naa, ti wọn ro pe oun lo kọ ọ. Sugbọn oṣerebinrin Olufunmi ti ṣalaye pe oun ni oun kọ sinima naa. Ninu fidio to fi si ori ayelujara Instagram rẹ ni ọjọ Aiku ati ọjọ Aje, lo ti ṣalaye pe ọmọ idile musulumi ni oun, ti oun naa si n ṣe ẹsin naa. Arabinrin Olufunmi Bakare sọ pe oun ko gbe sinima naa jade lati tabuku ẹsin naa. Ìdí tí Ooni Ogunwusi fi gbé ọmọ rẹ̀ obìnrin tó ṣe ọjọ́ ìbí 28 sáyé àti bó ṣe tọ́ ọ dàgbà Ìgbìmọ̀ tí ìjọba ìpínlẹ̀ Eko gbé kalẹ̀ lórí #ENDSARS ti parí ìṣẹ́, àbọ̀ rèé O ni iṣẹ owo ni Odunlade ṣe ninu sinima naa, kii ṣe oun ni oludari tabi ẹni to kọ sinima naa. O sọ pe idi ti oun fi ni ki obinrin were naa wọ aṣọ ẹlẹha ni pe ki awọn eero inu ọkọ to wọ̀ ma ba a dá mọ. Bakan naa lo sọ pe ki gbogbo awọn ẹgbẹ́ ẹsin Islam ti sinima naa ba binu darijin oun. O tun sọ pe oun ti yọ sinima naa kuro ni gbogbo ojú opo to n ṣe afihan rẹ, ki awọn le ṣe atunse to yẹ lori rẹ. Ẹgbẹ ajafẹtọ ẹsin Musulumi kan, Ta'awunu Human Rights of Nigeria ti tun wu ọrọ irunu mii sita lorii fiimu ti gbajugbaja oṣere, Odunlade Adekola gbe jade eyi ti wọn ni o tabuku awọn obinrin ẹlẹsin Islam. Nibayii wọn tun ti lọ́ ẹsun ọhun mọ obinrin to ko ipa Ẹlẹhaa ninu fiimu naa, Arabinrin Olufunmi Bakare. Wọn yari pe Odunlade mọọmọ ṣe fiimu naa jade lati tabuku awọn obinrin to n boju ninu ẹsin Islam ni to tun ni ibi ti Ẹlẹhaa ọhun n wọ motọ lọ ninu fiimu naa, Iyanna Ọrun, ko sibi to n jẹ bẹẹ nibikibi ni Naijiria. Ẹgbẹ THURIST ni awọn ti gbọ oniruuru ọrọ ti awọn eeyan n sọ kiri nigba ti awọn fi aidunu han si nkan ti oṣere naa ṣe. ""A fẹ jẹ ki gbogbo eniyan mọ pe a ti gba ọpọlọpọ esi ati ipe ti awọn eeyan fẹ fi ṣi awọn araalu lọkan pe gbajumọ oṣere nni Odunlade Adekola ko ipa ribiribi ninu fiimu naa oun naa si ni o ni fiimu naa. A fẹ ki gbogbo eeyan mọ pe a ni ikọ ọtẹlẹmuyẹ tiwa to maa n fun wa ni iroyin kikakia to si ṣee gbagbọ torinaa a o le jẹ ki ọrọ ti ko lẹsẹ nilẹ ka lroi ayelujara to ṣẹ jade lẹyin taa fẹsun kan wa gbona ju ohun taa n sọ lọ. A ti fi ẹsun kan to si jẹ ootọ, a ṣi n duro lori ọrọ wa"". Wọn ni oṣere naa ba wa gbagbọ pe ẹsun odi lawọn fi kan an, ko jade wa lati sọrọ ni gbangba. ""Bakan naa, a fẹ ki gbogbo eeyan mọ pe ni ibamu pẹlu jija fẹtọ ẹni ni ẹgbẹ yii fi tun fi ẹsun kan Arabinrin Olufunmi Bakare pẹlu Ọgbẹni Odunlade Adekola ati ẹgbẹ TAMPAN to n ṣakoso awọn oṣere fiimu Yoruba pe wọn kuna lati yẹ fiimu ọhun wo tabi fofin de iru rẹ"". Wọn ni awọn da obinrin naa ati Odunlade papọ ninu ẹsun yii tori pe o ṣeeṣe ki Odunlade ti beere lati lo obinrin naa Olufunmi ki ọwọ ofin ma baa muu. ""Amọ a fi n daa yin loju pe gbogbo ẹnikẹni to ba kopa ninu ere naa yala ipa kekere tabi nla, Musulumi ni tabi kii ṣe Musulumi lai fi ti ipo wọn ṣe la o ko pọ bi asiko ba to tori inu bi wa gidi fun ọna ti wọn gba ṣafihan Ẹlẹhaa naa. Fun idi eyi, awọn koko mẹrin ti a n beere fun laarin ẹgbẹ TAMPAN ati Ọgbẹni Odunlade Adekola niwọnyii: 1. Dida gbogbo ipele to ba ku ninu sinima ""Iku Ni"" duro ki wọn si ko o kuro lori gbogbo awọn oju opo ayelujara to ba wa to fi mọ Youtube laarin ọjọ meje. 2. fifi iya to tọ jẹ ẹni to gbe fiimu naa jade, odunlade Adekola ni ibamu pẹlu ohun ti ofin ati alakalẹ ẹgbẹ TAMPAN sọ. 3. Ṣiṣe ayẹwo fiimu gbogbo awọn oṣere to ba tun fẹ gbe iru nkan bayii jade. 4. Ki wọn pọn ọn ni dandan fun oṣere to ni fiimu naa lati tuba fun ẹgbẹ Musulumi ọhun fun iru fiimu to gbe jade yii nipasẹ ilana ti tile toko yoo rii. ""Inu wa dun pe BBC Yoruba jẹ ka mọ pe aarẹ ẹgbẹ TAMPAN Ọgbẹni Bolaji Amusan ti a mọ si Mr Latin ti ni oun yoo to sọrọ sita lori ipẹjọ wa yii"". Wọn ni awọn fẹ ki gbogbo eeyan mọ pe ipẹjọ awn ko i ku lori ọrọ yii o pe o ṣi wa laaye am pabanbari ohun tawọn fẹ ni ki ati Ọgbẹni Odunlade ati TAMPAN tọrọ aforijin ni gbangba laarin ọjọ meje. Eyi waye ninu atẹjade ti Agbẹjọro AbdulHakeem Abdul-Lateef ati Agbẹjọro Abdulsalama Abdul Fattah jọ fọwọ si ti wọn si ni bi Odunlade ati TAMPAN ko ba ṣe nkan tawọn n fẹ, awọn yoo gbe igbesẹ to lagbara ti awọn o si ni sọ bayii.",0,yoruba "ri Nitori eyi, ara eni lo je ti ibile.",0,yoruba "lòdì Ìbàdàn. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Nitori eyi, ara eni lo ni ẹ̀ká àwẹ eyti o gbe lori ọ̀run dídì.",0,yoruba mansa musa ẹ kú ajálẹ́ o ẹ jọ̀ọ́ ṣé mo rí wúrà díẹ̀ mo ní ṣíṣe kan lọ́jọ̀ àbámẹ́ta ńjẹ̀bú,0,yoruba kí ní fà á tí a fi pé ọmọlẹ́hìn islam ni ìmàle,0,yoruba olóògbé ẹni + tó + ṣe + ègbé fún àpẹẹrẹ alhaji fatai yusuf ọkọ olóyún ti di olóògbé,0,yoruba fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò.,0,yoruba Ìbàdàn. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde nìlẹ̀̀ní sáàrí ti nípa ìtànká àti ire ènìyàn.,0,yoruba "eni lo ni ìgbà mi owó àkokò, Ọmọ lo tun se se.",0,yoruba "RT @user: @user @user “Gomina ana ni ipinle kwara Sen Bukola Saraki nje wo esun bi o se nawo ipinle na bayi, alaye…",0,yoruba Ìjẹ̀. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó ga jù.,0,yoruba "RT @user: Bi Ise ko ba peni, akii pe isẹ́ http://t.co/Kt40tdP5",0,yoruba ènìyàn: ti o nuni ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó wáyé..,0,yoruba "òní. ti Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba "Gbajumọ oluṣọaguntan ijọ aguda nipinlẹ Enugu, Ẹniọwọ Ejike Mbaka ti ọpọ mọ si Fada Mbaka ti ṣalaye awọn to wa nidi bo ṣe di awati fun ọjọ meji. Nigba to n ba awọn olujọsin ijọ rẹ sọrọ nileejọsin Adoration ministries ni Umuchigbo Nike nilu Enugu, Fada Mbaka ṣalaye pe awọn alaṣẹ daosisi ijọ Aguda nilu Enugu lo wa nidi bi oun ṣe dawati. O ni Bisọbu agba ijọ aguda nibẹ lo pe oun sibi ipade kan, ibẹ si ni wọn ti fi oun si abẹ ahamọ. O ni ara ẹsun ti wọn ka si oun lẹsẹ̀ ni pe oun gbadura fun Nnamdi Kanu, aṣiwaju ẹgbẹ agbesunmọmi IPOB. Gẹgẹ bi o ṣe sọ fawọn ọmọ ijọ rẹ, ọgbọn ọjọ ni wọn gbero lati fi fi oun si ahamọ ki o to di pe awọn ọmọ ijọ rẹ pariwo sita ti wọn fi tu oun silẹ. Fada Mbaka ṣalaye pe oun ti wọn sọ fun oun ni pe oun yoo wa lahamọ fun oṣu kan fun oun lati gbadura ki oun si ṣe aṣaro lori iṣe oun. O ni oun rọ wọn lati fun oun laaye lati ba awọn eeyan ijọ oun sọrọ ki oun si ti ilẹkun ileejọsin naa ""ṣugbọn wọn ni rara, ẹ gbami laaye lati ṣe isin oni fun awọn olujọsin ijọ mi, mi o tilẹ ni sọ fun wọn pe mo wa labẹ ibawi, wọn ni rara. Maa kan sọ fawọn ọmọ ijọ mi ni pe mo n lọ fun adura ọlọgbọn ọjọ, a o pada wa gbogbo wa yoo si bọwọ fun gbogbo nnkan ti wọn ba sọ, wọn ni rara"" O ni oun tilẹ bẹ wọn pe ki wọn gbe iranṣẹ Ọlọrun miran lọ si ijọ naa, sibẹ wọn kọ ni. Ni Ọjọru ni okiki kan nigba tawọn ọmọ ijọ Adoration ministries ti Fada Mbaka n ṣe oluṣọaguntan fun wọde nilu Enugu ti wọn si n pariwo pe ki wọn ba awọn wa Fada Mbaka ti wọn ji gbe. Ninu ọrọ rẹ, Fada Mbaka ni awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ agbofinro DSS kọ lo gbe oun gẹgẹ bi awọn eeyan kan ṣe ro. Wọn ti ri ojiṣẹ Ọlọrun, Fr Ejike Mbaka. Ṣaaju ni iroyin jade pe alufaa naa to ni ijọ Adoration Ministry nilu Enugu ti di awati fun bi ọjọ meji. Iṣẹlẹ yii n waye lẹyin ọjọ diẹ ti Mbaka pe ki Aarẹ Muhammadu Buhari fi ipo silẹ nitori bi eto aabo ṣe ri ni Naijiria. Bi iroyin ṣe jade pe wọn ko ri Mbaka, ni awọn alatilẹyin rẹ ti tu jade fun iwọde lọ si ile Olori alufaa ijọ Aguda nilu Enugu. Botilẹ jẹ pe a ko ti i le sọ nkankan nipa bi alufaa naa ṣe pada si ilu tabi ibi to ti n bọ, tilu-tifọn, tijo tayọ ni awọn eeyan fi pade rẹ. Awọn to wa ni ayika alufaa naa sọ pe o ti le ni ọjọ meji ti awọn ti ri Mbaka gbẹyin. A gbọ pe o dagbere fun to sunmọ pe pun n lọ si ile Alufaa Agba ijọ Katoliliiki ni ẹkun Enugu, ṣugbọn wọn ko ri i lati igba naa. Fr Mbaka kọ ẹ̀yìn sí Buhari nítorí kò rí nǹkan jẹ lábẹ́ rẹ̀ - Iléeṣẹ́ Ààrẹ Fr Mbaka, ọmọ ìjọ rẹ̀ kọ̀lu akọ̀ròyìn BBC, wọ́n lù wọ́n ní àlùdojúbolẹ̀ Lasiko ti BBC ṣe abẹwo si inu ọgba ijọ rẹ, Adoration Ministry, niṣe ni eero pe jọ sibẹ, ti wọn si n beere pe nibo ni Father Mbaka wa. Ṣugbọn, BBC ko ti i le sọ ni pato boya wọn ji alufaa naa gbe lọ ni, boya o farapamọ ni tabi wa ni ọdọ awọn agbofinro. Bakan naa ni awọn alaṣẹ ijọ Aguda nilu Enugu sọ pe awọn ko ti i gbọ nipa iṣẹlẹ naa. Alufaa kan to sunmọ Mbaka naa sọ pe oun ko gbọ nipa didi awati rẹ, ṣugbọn ko gbe ipe oun si ori ẹrọ ibanisọrọ rẹ. Iṣẹlẹ yii si ti mu ki awọn ọmọ ijọ rẹ bẹrẹ iwọde.",0,yoruba "ẹkọ́: ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "tí Alàji fè joko, Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó ṣe pàtàkì.",0,yoruba "tí Ọmọ fè se, Nitori eyi, ara eni lo je ti ibile.",0,yoruba olóótọ fún àwọn ìkòkò tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni.,0,yoruba "Àjọ tó ń gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà ( NCDC ) ló kéde yìí lóríẹ̀rọ Twitter wọn , @ NCDC .",0,yoruba Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó ṣe pàtàkì. (Item 71),0,yoruba da ti o nuni ti o ní wúlò.,0,yoruba "asin. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ìyá lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba KI ARA DE MI DEDE L'ODUN TUNTUN http://t.co/62s9A3m5,0,yoruba "Awọn ibeji yii wa lara itan aṣeyọri ninu eto ilera lorilẹede Naijiria. Ọkan ninu ibeji to lẹpọ ye isẹ abẹ ni Bauchi Ọdún ìbejì sọkutu-wọ̀wọ̀ ní Igboọrà, àṣírí bí wọn ṣe ń bí ìbejì tú Ìbejì Oníbẹ̀mbẹ́ Òru tí kò yara wọn lẹ́yìn ọgọ́ta ọdún Iṣẹ rèé lọ́wọ́ dokita aadọrin. Wakati mejila gbako lo gba awọn dokita naa. ""Nígbà tí Goodness nìkan kọ́kọ́ jádé nínú yàrá iṣẹ́ abẹ, ìrètí mi gaa... bi Mercy ko ṣe tii jade wa"" Ẹwẹ, nigba ti gbogbo ẹ di aṣeyọri, baba ati iya ọmọ to fi mọ awọn dokita to ṣe iṣẹ abẹ naa atawọn ijọba lo n ṣe ajọyọ pe wọn ri wọn pinya pẹlu aṣeyọri. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:",0,yoruba Àlọ̀ nígò ìjápe ni ìtan orìkì òrìşà...,0,yoruba "Adẹyinmu fun ẹgbẹ agbabọọlu Liverpool, Virgil Van Dijk lo gbami ẹyẹ agbabọọlu UEFA to pegede julọ ni saa bọọlu to lọ. Van Dijk fẹyin Cristiano Ronaldo ti Juventus ati Lionel Messi ikọ Barcelona gba lẹ gba ami ẹyẹ naa. Van Dijk wa lara awọn agbabọọlu to pegede nigba ti Liverpool na Tottenham pẹlu ami ayo meji sodo ninu ifẹsẹwọnsẹ aṣekagba idije UEFA Champions Laegue ti saa to lọ. Agbabọọlu Van Dijk to jẹ ọmọ orilẹde Netherlands lo ti n fakọyọ lati to ti darapọ ikọ Liverpool lati Southampton loṣu kinni ọdun 2018 fun pọun marunlelaadọrin(£75m). Agbabọọlu naa ki awọn akẹgbẹ rẹ atawọn ti wọn ran an lọwọ lati gbami ẹyẹ naa. O ni ti ko ba si awọn akẹgbẹ oun, ko lee ṣeeṣe fun oun lati pegede gbami ẹyẹ naa mọ Messi ati Ronaldo lọwọ. Ṣé Van Dijk lè borí Ronaldo àti Messi nínú ìdíje UEFA? Loni ni igbimọ adari ere bọọlu alafẹsẹgba UEFA yoo kede ẹlẹsẹ ayo tọdun yii nilẹ Yuroopu. Awọn akọni mẹta ni wọn jọ n du ami ẹyẹ yii: adiẹyin ẹgbẹ agbabọọlu Liverpool, Virgil Van Dijk, Cristiano Ronaldo ti Juventus ati Lionel Messi to n gba bọọlu fun Barcelona. Luka Modric lo yọ lara Ronaldo ati Messi lati gba ami ẹyẹ Ballon d'Or lọdun to kọja. Opo n lero pe o ṣeeṣe ki Van Dijk gbegba oroke mọ Messi ati Ronaldo lara lọdun yii. Lionel Messi ati Cristiano Ronaldo ni wọn ti n gba ami ẹyẹ yii mọ ara wọn lọwọ lati ọdun bii mẹwaa sẹyin. Lọdun 2011 ti wọn kọkọ yan ẹlẹsẹ ayo UEFA. Ronaldo ti gbaa ni ẹẹmẹta iyẹn ọdun 2014, 2016 àti 2017. Nigba ti Lionel Messi ti gba a lẹẹmeji lọdun 2011 ati 2015. Ronaldo lo ran Juventus lọwọ ti wọn fi bori ni Seria A nigba ti Messsi ran Barcelona lọwọ lati gba Liga. Laarin ọjọ kọkanlelọgbọn, oṣu keje, ọdun 2018 si ọjọ kọkanlelọgbọn, oṣu keje, ọdun 2019 ni esi abajade ifakọyọ awọn mejeeji ti fihan. Messi ti gba goolu mẹrinlelaadọta sáwọn nigba ti Ronaldo ti gba mejilọgbọn sawọn. Van Dijk ló ti jé akọni pataki ni Liverpool lati igba to ti kuro ni Southampton nibi ti wọn ti bori Champions League ni saa to lọ. Bakan naa ni o ṣe iranwọ fun Manchester City lati gba Premier League. Van Dijk ni agbabọọlu adiẹyin mu akọkọ ti wọn yoo maa wo boya o le gba ami ẹyẹ naa. Van Dijk ti kopa ninu idije mọkandinlọgọta to si ti gba ọpọlọpọ goolu sawọn. Oun tun ni ẹlẹsẹ ayo Liverpool ati agbabọọlu to tii pẹ ju lagbaye (4,465). Ilu Monarco lorilẹ-ede Faranse ni ikede ẹlẹsẹ ayo naa yoo ti waye.",0,yoruba "Ajọ ilera agbaye ti pariwo sita nipa awọn oogun ikọ mẹrin kan, ti wọn ni o ṣeeṣe ko nii ṣe pẹlu iku ọmọde mẹrindinlaadọrin,mẹrindinlaadọrin lorilẹede Gambia. Ajọ WHO ni oogun ikọ naa ni wọn ti fihan pe o nii ṣe pẹlu ọgbẹ inu, kidinrin ati iku awọn ọmọde mẹrindinlaadọrin naa. Ileeṣẹ apoogun kan lorilẹede India ti orukọ rẹ n jẹ Maiden Pharmaceuticals, ni wọn sọ pe o po ogun naa. WHO ni ileesẹ naa si lo ti kuna lati fi ẹri kalẹ nipa alaafia awọn to lo o. Lasiko ti iroyin yii fi jade, ileeṣẹ apogun naa ko tii sọ ohunkohun lori rẹ. Ileeṣẹ BBC ti kan si ileeṣẹ apogun Maiden Pharmaceuticals fun alaye tiwọn lori eyii. Awọn alaṣẹ lorilẹede India ni awọn ti kan si ajọ ilera agbaye, WHO pe ko fi ẹri to so iku awọn ọmọde naa, pọ mọ ogun ikọ ti ileeṣẹ naa ṣe ṣọwọ si awọn. Ajọ WHO ni orukọ awọn ogun ikọ naa ni Promethazine Oral Solution, Kofexmalin Baby Cough Syrup, Makoff Baby Cough Syrup ati Magrip N Cold Syrup. Ajọ agbaye naa ṣekilọ pe elo ogun naa lee fa ọgbẹ tabi iku, paapaa laarin awọn majesin. Ajọ eleto ilera lagbaye wa yan pe wọn ti ri awọn ogun ikọ mẹrẹrin yii lorilẹede Gambia. Who ni awọn oogun ikọ naa tun ti gba ọja okunkun fayawọ tawọ si awọn orilẹede miran tabi awọn agbegbe miran ni Afirika. Ajọ WHO da si ọrọ naa nigba ti awọn alaṣẹ lorilẹede Gambia kẹẹfin pe iye awọn to n ni ọgbẹ inu ati aisan kidinrin pọ sii laarin awọn ọmọde ti ọjọ ori wọn ko ju ọdun marun un lọ loṣu keje. Lati igba naa ni awọn alaṣẹ ijọba lorilẹede Gambia ti fofin de lilo ogun olomi naa, to si tun ni awọn eeyan rẹ ko gbọdọ lo oogun ikọ onikoro to jẹ ti ileesẹ apoogun naa. Ajọ WHO sọ pe ayẹwo ogun naa nibudo ayẹwo igbalode fihan pe “ o ni eroja diethylene glycol ati ethylene glycol ninu wọn pẹlu odiwọn ti ko dara to”. Awọn alaṣẹ eto ilera lorilẹede Gambia sọ pe loṣu to kọja, ọpọ awọn ọmọde lo ṣalaisi lai sọ iye wọn ni pato. Ninu ọrọ to sọ nilu Geneva, oludari agba ajọ ilera agbaye, Tedros Ghebreyesus sọ pe: “Ohun to kọja ibanujẹ ati iporuru ọkan ni iku awọn majesin naa jẹ fun awọn mọlẹbi wọn.” Ileeṣẹ akoroyinjọ AFP sọ pe gẹgẹbi  ohun to jẹyọ ninu lẹta ori ayelujara kan ti ajọ ilera agbaye naa fi sita, ajọ to n ṣe ayẹwo ati amojuto ogun ni India sọ pe o ṣeeṣe ko jẹ pe awọn ogun to ni eroja kotọ ninu wọn, ni ileeṣẹ apoogun yii ko ranṣẹ si orilẹede Gambia. Ajọ WHO sọ pe o dara ki gbogbo agbaye mọ nitori pe ileeṣẹ apoogun yii tun lee lo awọn eroja ti ko dara to yii, sinu awọn ogun miran to n pin lorilẹede naa tabi pin kaakiri si oke okun.",0,yoruba "Lasiko ti wọ̀n n ba akọroyin BBC sọrọ, ọpọ eeyan lo tun ni awọn ni iwe ẹri to yẹ, amọ ti isẹ oojọ di isoro. Fun apẹẹrẹ, ni ipinlẹ Rivers, ti epo rọbi sodo si julọ lorilẹede Naijiria, ọpọ olugbe ipinlẹ naa lo ni ko si owo lọwọ, ko si isẹ lati se, ti ebi si n pa awọn. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Koda, wọn ni awọn ni iya ati baba to yẹ ki awọn maa fun lowo, amọ ti ebi n pa wọn, nitori airi isẹ se awọn. Amọ awọn miran tiẹ fikun pe, o lee jẹ iṣẹ kan pere ni awọn n ri se ni odidi ọṣẹ kan. Ni bayii ti aarẹ Muhammadu Buhari si ti bẹrẹ saa keji rẹ lori aleefa",0,yoruba Àkójú ọ̀rọ̀ yi kún fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde sí ara ilẹ̀. (Item 184),0,yoruba ài: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó ga jù.,0,yoruba "Ìle-Ìfẹ̀. Nitori eyi, ara eni lo ni ẹ̀ká àwẹ eyti o gbe lori ọ̀run dídì.",0,yoruba @user @user Ẹ jẹ́ kí ng bá yín fi àmì sí i,0,yoruba ilera ṣẹlẹ ni Eko ti gbogbo eniyan sọ o dara. (1995),0,yoruba Ènìyan ti nilo iyalẹnu fun ilera tabi ibini.,0,yoruba RT @user: Corona words in #Yoruba: ÈDÈ ÌPERÍ FUN ÀRÙN KÒRÓNÀ NÍ ÈDÈ YORÙBÁ @user •Quarantine - àhámọ́alárùn •Sanitizer - ohu…,0,yoruba "Ẹlòmíràn tún ti lùgbàdì àrùn Corona Virus nílùú Abuja àti Eko O ti di eeyan ọgbọn bayii to ti lugbadi arun naa lorilẹede Naijiria. End of Twitter post, 1 Ajọ NCDC ṣalaye pe eeyan meji ninu wọn lo ti kuro ni ile iwosan lẹyin ti wọn gba itọju tan. O ti di eeyan mẹrin to ti lugbadi arun coronavirus bayii, nigba ti ipinlẹ Eko ko mọkandinlogun ninu rẹ, eeyan meji lo karun naa nipinlẹ Ogun, eeyan kọọkan larun naa nipinlẹ Oyo ati Ekiti. Àrùn coronavirus wọ ìpínlẹ̀ Oyo Ajọ NCDC ti kede tẹlẹ pe eeyan miran to ni aarun coronavirus lorilẹede Naijiria. Gẹgẹ bi atẹjade kan ti ajọ naa fi soju opo twitter rẹ lowurọ ọjọ Aiku, eeyan kan naa sọ iye awọn ti wọn kede pe wọn ni arun naa ni ọjọ Aiku nikan di mẹrun bayii. Coronavirus symptoms: Èèyàn mẹ́ta míràn ti ní àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà Eeyan mẹta miran tun ti ko arun Coronavirus lorilẹede Naijiria bayii. Ajọ to n gbogunti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ṣalaye pe o ti di eeyan marundinlọgbọn to ti ni arun naa bayii. Iroyin naa fi idi rẹ mulẹ pe ipinlẹ Eko ni awọn mẹta tuntun ti wọn ṣẹṣẹ ṣawari naa ti wa. Bakan naa ni wọn tun fi kun un pe, awọn mẹtẹẹta lo ti rinrinajo lọ sawọn orilẹede ti arun yii ti wọpọ lagbaye laarin ọjọ meje sẹyin. Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹede Naijiria, NCDC ko ṣai fi da awọn eeyan loju pe akitiyan n lọ bayii lati ṣawari gbogbo awọn eeyan ti wsn ti ni ajọṣepọ pẹlu awọn eeyan mẹta yii. Ajọ naa wa n rọ awọn ọmọ Naijiria to rinrinajo pada wa sorilẹede Naijiria laarin ọjọ mẹrinla sẹyin si asiko yii lati fi ara wọn sabẹ igbele fun ọjọ mẹrinla lati mọ boya wọn ni arun naa tabi ara wọn da ṣaka.",0,yoruba kí ni ẹyẹ òwìwí ń wá nínú ìpàdé ìgbìmọ̀ ìjọba tanzania,0,yoruba "Ìhùwàsíi Buhari burú jáyì , ó ní ẹ̀tàn nínú , kò sì ní orí kò sì ní ìdí .",0,yoruba ni òun tí a ní nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o pataki.,0,yoruba ba nìkan. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ẹkọ́: ti o ní wúlò.,0,yoruba "Fún àpẹẹrẹ [ lára àwọn àtòpọ̀ ẹ̀rọ yìí ] , a ní ètòo gbígba ìwé àṣẹ ní àwọn agbègbè yìí [ tí ó ń bá wa dènà ] àìlègbẹ̀rí àwọn iléeṣẹ́ jẹ́ àti àìtó agbára ìjọba láti kápáa wọn nínú ìpínlẹ̀ náà .",0,yoruba "Ise logun ise, ore mi, Mura sise Ojo nlo..... #yoruba #ibadanlawa #ibadanprenure",0,yoruba "lo lọ. Nitori eyi, ara eni lo ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.",0,yoruba "Ìgbìmọ̀ amúsẹ́yé ẹgbẹ́ òsèlú APC ti polongo Dapo Abiodun gẹ́gẹ́ bí olùdíje sípò gómìnà lẹ́gbẹ́ òsèlú APC ní ìpínlẹ Ogun. Bi Dapo Abiodun ba jawe olubori ni idbo gbogboogbo ti ọdun 2019, oun ni yoo gba ijọba lọwọ gomina Ibikunle Amosun ti ipinlẹ Ogun. Ọjọ kọkandinlọgbọn, Osu Karun, ọdun 1960 ni wọn bi ọmọọba Dapo Abiodun lati ijọba ibilẹ Iperu-Remo ni ipinlẹ Ogun. Awọn ohun marun nipa oludije sipo gomina ni ipinlẹ Ogun fun idibo ọdun 2019. ìpàdé ìtagbangba ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò pẹ̀lú àwọn olùdíje sípò gomina ní ìpínlẹ̀ Eko.",0,yoruba "Awọn obi to ba BBC sọrọ ni lootọ ni aisan bẹ silẹ ni Queens College Obi kan sọ fun BBC pe, ọmọ oun wa lara awọn ọmọ to fara kaasa aisan naa, bo tilẹ jẹ pe o ti gbadun bayi. O ni ""Wọn pe mi lori ẹrọ ilewọ lati wa gbe ọmọ mi, nigba ti mo de ibẹ, mo ri ọpọlọpọ awọn ọmọ ti wọn fun laye lati lọ sile latari aisan ọhun."" Damian tẹ siwaju pe, ọmọ oun n fẹ lati pada sile iwe bayi, sugbọn wọn fẹ ki ara rẹ bale diẹ sii. Bi o tilẹ jẹ pe awọn obi kan ni ahesọ lasan ni ọrọ naa, sugbọn awọn obi ti BBC ba sọrọ fidi rẹ mulẹ pe lootọ ni aisan bẹ silẹ nile iwe naa. Arabinrin kan ti orukọ rẹ n jẹ Ekanem to jẹ ọkan lara awọn obi ọhun ni, ọmọ oun to wa ni ileewe naa sọ pe ọpọlọpọ lara awọn ọmọ ileewe ọhun n ṣaisan, sugbọn ṣaka lara ọmọ oun le. Awọn eleto ilera ipoinlẹ Eko ti ṣabẹwo sileewe ọhun Ijọba ipinlẹ Eko ni oun ti bẹrẹ iwaadi lọwọ lati mọ okodoro ohun to ṣẹlẹ nile iwe yiii, ati pe oun yoo bẹ awọn ile iwe miran wo fun ayẹwo. Ikọ BBC to ṣabẹwo sile iwe Queens College foju ganni awọn eleto ilera to yọju sile iwe naa latari iṣẹlẹ ọhun. Awọn alakoso Queens College kọ lati ba BBC sọrọ, bẹẹ ni wọn ko gba akọroyin wa lati wọ inu ọgba ile iwe ọhun. Lara awọn akẹkọ Queens College to fọrọjomitoro ọrọ pẹlu BBC ni, ile iwe ati yara igbọnsẹ wọn nilo atunṣe ni kiakia. Queens College Lagos: Ọmọ 85 dùbúlẹ̀ àìsàn lẹ́ẹ̀kán nàa ní Ilé ìwé Queens College! Ẹgbẹ́ àwọn ọmọ ilé ìwé náà tẹ́lẹ̀rí ní àìsàn tó ń se àwọn ọmọ ile iwe naa ko nii se pelu omi mimu abi lilo. Ile iwe Queens College ni ipinlẹ Eko ti gbe ọmọ marundinlaadọrun lọ si ile iwosan lati igba ti wọn ti wọ ile iwe ti saa yii lọsu kẹsan an ọdun. Agbẹnusọ ẹgbẹ awọn obi ati awọn olukọ ile iwe Queens College, Ify Nwoye ni lati bii ọsẹ kan ni oun ti n gbọ iroyin pe wọn n gbe awọn ọmọ digbadigba lọ si ile iwosan. Amọ, Akowe ile iwe naa, Ayomide Onakoya ni lati igba ti isẹlẹ naa ti bẹrẹ ni awọn ti bẹrẹ si ni se iwadii. Onakoya ni iwadii igbimọ awọn eleto ilera naa fihan wi pe aisan naa ko nii se pẹlu omi ti wọn mu gẹgẹ bi awọn kan ṣe sọ, nitori ọna ọfun wọn ni aisan naa ti n ba wọn ja, kii se ni inu. Intersextuality: Dokita ni ká mu èyì tó wù wá nínú jíjẹ́ akọ tàbí abo Ile iwe naa fikun un wi pe lara awọn ami ti awọn ọmọ naa n fihan ni ikọ ati Catarrh pẹlu ẹfọri ati ara gbigbona. Opọlọpọ iwadii ti awọn igbimọ eto ilera ile iwe Queens College ti ṣe ni wọn gba pe o yẹ ki o fi ọkan obi ati alagbatọ balẹ pe kii ṣe ajẹkalẹ arun lo n ṣẹlẹ lọwọ ni ile iwe naa. Blacksmith: èmí ni ìran keje tó jogún iṣẹ́ àgbẹ̀dẹ yii- Alatiṣe Bakan naa ni wọn fikun un wi pe, ile-isẹ eto iwosan, ẹgbẹ awọn obi ati ẹgbe awọn ọmọ ile iwe naa tẹlẹri n sisẹ papọ lati ri i wi pe opin ba aisan ni ni ile-iwe Queens College! Nigeria Independence Day: Sé ẹ mọ̀ pé ọdún 1956 ló yẹ́ ká ti dòmìnira ṣùgbọ́n....",0,yoruba "Ká máà bá Òpó lọ ilé Olórò, ṣàṣà ni ohun ìjẹ tí ẹ̀dá ọmọ aráyé ń jẹ lóde òní tí ò ní èròjà àjèjì ń'nú, kí la ó wa ṣe? #AyajoOjoIle #Earthday",0,yoruba "Phillip Lühl sọ pe awọn ọmọ rẹ yi ko ni orileede ti wọn le pe ni ilẹ wọn lẹyin ti ileeṣẹ abẹle Namibia kọ lati fun wọn ni iwe irinajo pajawiri lọsẹ to kọja. Labẹ ofin biba eeyan gboyun ni South Africa, awọn ọmọ ti wọn ba gba ọna yi ti di ọmọ orileede ibi tawọn obi wọn ba ti wa. Lori ọrọ to wa nilẹ yi, ofin naa gbe ipo obi yi fun ọgbẹni Luhl ati ọkọ rẹ ọmọ orileede Mexico Guillermo Delgado. 'Òde ìnáwó làwọn èèyàn ma ń rò bí wọ́n bá rí Ankara, ìgbà tí wọ́n rí i lára àga tí mo ṣe, ẹnu wọn ò padé mọ́' Ninu iwe ibura ọgbẹni Lühl ni ileeṣẹ eto abẹle ni ki ohun ṣafihan bi o ṣe jẹ pe oun lo ni awọn ọmọ meji yii. O ni oun gbagbọ pe wọn gbe igbesẹ naa nitori pe oun ṣe igbeyawo ibalopọ akọ si akọ ati pe idẹyẹsi ni iwa yi jẹ si oun. Ẹwẹ,o ni iwe ofin orileede Namibia ko pọn ni dandan pe eeyan gbọdọ finu ara rẹ bimọ ki wọn to mọ pe oun lobi ọmọ naa. Ni Namibia, ofin ilẹ naa tako ibalopo akọ si akọ bo tilẹ jẹ wipe awọn to n ṣe bẹ kii foju wina ofin lọpọ igba. Bakan naa ni ko si ilana kankan to de gbigboyun ẹlomiran sikun nilẹ naa. Awọn ajafẹtọmọniyan n palẹmọ lati ṣe iwọde niwaju ile ẹjọ giga Namibia lỌjọbọ lati fẹhonu han idẹyẹsi ọkan lara awọn ti iṣesi wọn yatọ. Bí Oduduwa Republic bá bẹ̀rẹ̀, a ò ní ṣe aburú fún àwọn tó takò wá, ìlànà ààtẹ̀lé rèé - Banji Akintoye",0,yoruba "ojú onà. ti Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "Ẹ kú déédéé àsìkò yìí ẹ̀yin ènìyán àti ènìyàn lóríi Twitter, ṣé àlàáfíà ni?",0,yoruba Fi Férémù _Yìí Nìkan Hàn,0,yoruba "Ọmọ fè lọ, A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..",0,yoruba "Iroyin ahesọ kan jade sigboro lowurọ Ọjọru pe aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari ti gba iṣẹ lọwọ gomina Banki apapọ orilẹede naa, Ọgbẹni Godwin Emefiele. Oniruuru iroyin lo si ti jade lẹyin rẹ bi awọn ọmọ Naijiria kan ṣe n kan sara ni awọn kan n woye pe igbesẹ naa ko tọna. Godwin Emefiele bọ si agbami iroyin paapaa julọ lori ayelujara nigba ti iroyin gbe e pe oun naa fẹ dije ati pe awọn ẹgbẹ kan ti ko ara wọn jọ lati ra fọọmu idije fun un. Gbogbo eeyan lo pariwo sita nigba naa pe o ku diẹ kaato. Awọn eekan bii Oby Ezekwesili, Amofin agba Fẹmi Falana, SAN, ẹgbẹ oṣelu PDP atawọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ ni wọn pariwo pe ko fi ipo silẹ to ba fẹ dije fun ipo kankan gẹgẹ bi ẹtọ rẹ gẹgẹbi ọmọ Naijiria labẹ ofin. Lẹyin igba naa ni Emefiele gba ile ẹjọ lọ lati bere fun alaye lori boya oun lẹtọ tabi oun ko lẹtọ labẹ ofin lati dije fun ipo aarẹ Naijiria lai kọwe fi ipo silẹ gẹgẹ bi gomina banki apapọ Naijiria. Gbogbo iroyin to n jade lati ileeṣẹ aarẹ orilẹede Naijiria ko fi idi iroyin yii mulẹ. Eeyan kan to sunmọ ileeṣẹ aarẹ pẹkipẹki ṣalaye fun BBC pebi awọn eeyan ṣe ji gbọ iroyin naa loju opo Twitter ni pupọ awọn naa gbọ ọ ati pe irọ to jina si otitọ ni. Lasiko ti a fi n ko iroyin yii jọ, ko tii si atẹjade kankan lati ileeṣẹ ijọba Naijiria to fi idi rẹ mulẹ pe Aarẹ Muhammadu Buhari ti yọ Emefiele nipo gẹgẹ bi gomina banki apapọ Naijiria. Amọṣa bi eeyan ba wo ofin to de idasilẹ ati akoso banki apapọ Naijiria, ko si ọna ti aarẹ lee fi ṣa dede gba iṣẹ lọwọ gomina banki apapọ Naijiria. Abala kọkanla iwe ofin Centra Bank Nigeria Act 2007' sọ ọ di mimọ pe ida meji ninu mẹta gbogbo awọn aṣofin agba Naijiria ni lati fọwọ si yiyọ gomina Banki apapọ Naijiria ki aarẹ to lee yọ ọ nipo.",0,yoruba Ìle-Ìfẹ̀. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ àti ìbi tí wọn wà.,0,yoruba "Funmilayo Ogunsola tí ọ̀pọ̀ ènìyàn mọ̀ sí ""Mama Ijẹwuru"" ti fi ayé sílẹ̀ ní ilé rẹ̀ ní Ibadan. Ijẹwuru ni iyawo kẹrin fun gbajugbaja osere tiata kan to ti di oloogbe, Ishola Ogunsola, to jẹ ọkan gboogi ninu awọn oludasilẹ ẹgbẹ awọn oni tiata lorilẹede Naijiria. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Wọn ko ni nkan ṣe fún ipinlẹ Ọyọ ni' #BBCGovDebate Molebi arabinrin naa, Adebisi Ogunsola lo fi isẹlẹ naa lede loju opo ikansiraẹni Facebook rẹ. Ọpọlọpọ eniyan mọ obinrin naa bii ẹni to ma n se bi odi ninu ere tiata. Awọn akẹẹgbẹ rẹ ni Jimoh Alihu, Charles Olumo, ati Afolabi Afolayan (Jagua) to ti papoda.",0,yoruba si ìlú.. A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà.,0,yoruba "Bí a bá lè kọ àwọn ìró ohùn gbólóhùn inú ètò, àfihàn tàbí eré ìtàgé àgbéléwò sábẹ́ ojú amohùnmáwòrán tàbí lórí àwọn ẹ̀rọ mìíràn ní èdè Gẹ̀ẹ́sì tàbí ní àwọn èdè àgbáyé tó kù, è é ṣe tí a kò leè ṣe bẹ́ẹ̀ fún èdè… https://t.co/WnnQ9MJrHJ",0,yoruba "In the spirit of the history of ONÍKÒYÍ OF ÌKÒYÍ, we bring to you, the Eulogy of Ẹ̀ṢỌ́ ÌKÒYÍ (GUARDS OF ÌKÒYÍ) 😊 Ká pìtàn, ká mọ̀ ìtàn, ni ń mú orí wú. Ká wá fi Oríkì lé ìtàn, ni ń mú ara yá gágá. Ẹ fi Oríkì ONÍKÒYÍ TI ÌKÒYÍ gbé ìtàn rẹ̀ lárugẹ 😊 By @user https://t.co/7Mv5JLGFTC https://t.co/geujz8DEuI",0,yoruba ẹ ti gbìyànjú ẹ tún bọ̀ ṣe díẹ̀ si kí ẹ fi parí rẹ̀,0,yoruba níbo wá ni àwọn tó lo ayé lánàá lọ lẹ́hìn tí ikú lù wọ́n ní kùmọ̀ ṣe pé ọ̀run kọ́ lọ́ lọ ọ̀run àpáàdì ni,0,yoruba @user @user A ò kí ń ṣe ẹni burúkú nítorí a jẹ́ oníṣẹ̀ṣe. https://t.co/ePAs0YoH4u,0,yoruba "ọ̀ṣun ìlú. Nitori eyi, ara eni lo ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "Nígbà tí Bàbá fè fi, Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.",0,yoruba "joko. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba RT @user: @user @user Are Jonathan se ipade pelu awon oga eleto abo ile wa lati dekun aawon jamba to nsele ni oril…,0,yoruba "Lẹ́yìn ìwádìí , àwọn ọlọ́pàá ṣe àrídájú wípé ọmọ - ọ̀dọ̀ kan láti ilẹ̀ òkèèrè tí ó ń bẹ̀rù wípé ọ̀gá òun yóò lé òun ni ẹnu iṣẹ́ bí ó bá mọ̀ wípé òun ní oyún ni ìyáa rẹ̀ .",0,yoruba mo kàwé àgbẹ̀ sì ni mí ìwé tí mo kà ò díṣẹ́ oúnjẹ lọ́wọ́ mò ń ran orílẹ̀èdè mi lọ́wọ́ ni ìwọ náà darapọ̀ mọ́ wa,0,yoruba "Akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ onímọ̀ ìṣirò owó ni Lateefat, ẹni ọmọ ọdún mẹ́rìndinlọgbọ̀n Wọ́n rí Adewura nínú adágún omí ńlá kan lẹ́yìn ti òkìkí tàn kálẹ̀ pé wọ́n ń wá. Ọmọbìnrin náà ní àwọn ara àdúgbò naa gbe sórí ẹ̀rọ ayélujára pé àwọ̀n ri ninu àgbàrá òjò. Wọn ni eyi ṣẹlẹ lẹ́yìn ti wọn ti gbà wọ̀n ní ìmọ̀ràn láti máa tẹ̀síwájú nínú ìrìnàjò wọ́n lọ́jọ́ náà, sùgbọ́n ní kété ti wọ́n tẹ̀síwájú ni àgbàrà òjò gbá ọmọbìnrin náà lọ àmọ́ orí kó ọlọ́kadà yọ. Ẹgbọ́n olóògbé Suga: Wọ́n yìnbọn fún Suga lójú mi, n kò sì lè dá wọn dúró Ní kété ti wọ́n rii ni wọn fa ọlọ́kadà náà lọ sí àgọ́ ọlọ́pàá ti agbegbe Mọṣálásí ti wọ́n si rọ ẹbí ọmọ náà láti ṣe àbẹwò si àgọ ọlọ́pàá láti jẹ́ kí ọlọ́kadà ọhun ṣàlàyé ìrú ẹni tó gbé. Èyí ní ẹbi Adewura ṣe ti wọ́n fi rí òkú Adewura ní inú adágún omí ǹlá (Canal) ní àgbègbè Iyana Ipaja ni ipinlẹ Eko. Bó tilẹ̀ jẹ́ pé, agbẹnusọ ọlọ́pàá, Bala Elkana sọ fún àwọn akọ̀rọ̀yìn pé, kò tii sí àrídájú pé òkú Adewura ní wọn ri àfi ti ìwádìí ba parí níwọ̀n ìgbà to jẹ́ pe òkú rẹ̀ ti ń jẹra. 'Ohùn gooro ló gbé mi dé ọ̀dọ̀ ààrẹ̀ Bush, Obama, Obasanjo, Goodluck, Buhari' Ó ní ""lóòtọọ́ a rí òkú kan ní inú adágunní Ipaja ṣùgbọ̀n a kò tíì le fi ẹnu ọ̀rọ̀ jóná báyìí nítorí òkú rẹ̀ ti ń jẹrà. 'Àsìkò Amojúẹ̀rọ Seyi ni ló fi wọlé l'Oyo, kìí ṣe àsìkò èmi Omobolanle' Orọ awọn agbofinro ni pe: ""Lọ́wọ́ ti a wà yìí, ìgbẹ́kèlẹ̀ ọlọ́pàá ni abájáde ǹkan ti àwọn oníṣègùn oyinbo bá sọ lẹ́yìn àyẹwò wọ́n, nítori à ti gbé òkú náà lọ si ilé ìwòsàn fún àyẹwò"". Toma Unu: Ọmọbìnrin tó ń fi ẹsẹ̀ rẹ̀ ya àwọran nítori pe ó ni ìpènija ọpọlọ Ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ Nàìjíríà ló ti ń ṣelédè lẹ́yìn ọmọbìnrin náà lójú òpó Twitter Contortionist: Mo lè gbé ìfun mi pamọ́ ki n tún se èémí!",0,yoruba ìròyìn tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa aráyé: ti o nuni ti o dara.,0,yoruba Presidential Candidates: Ọ̀rọ̀kọ́rọ̀ ni àbọ̀ EU lóri ìbò 2019,0,yoruba gblọ yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba "Bàbá fè lọ, A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..",0,yoruba "Adari ajọ INEC nipinlẹ Osun, Ọjọgbọn Abdulganiyu Raji ba BBc Yoruba sọrọ ni igbaradi de eto idiibo gomina ti yoo waye ni ipinlẹ Osun lọjọ Satide ọjọ Kẹrindinlogun, oṣu Keje ọdun 2022. Ninu ọrọ rẹ, Ọjọgbọn Raji ni ""Abdulganiyu Raji ni tẹ́ẹ bá ni ká dìbò báyìí báyìí, INEC ti ṣetán torí àwọn a ti kọ ẹ̀kọ́ lára ìdìbò ọdún 2018 àti 2019"". O ni nigba ti awọn ṣe agbeyẹwo, awọn pe awọn tọrọ kan jọ, awọn si ti jọ ṣe awọn ilana ilọsiwaju fun apẹrẹ, ""Aye idibo 753 la ti ni bayii eyi to pọ ju ti atijọ lọ"". Raji ṣalaye ohun to yẹ ki awọn ara ipinlẹ Osun ṣe bi awọn oloṣelu ba wa lati ra ibo wọn. O tun ṣalaye awọn ofin to wa nikalẹ fun ẹnikẹni to ba ṣe ohun ti ko tọ lasiko idibo.",0,yoruba Aarẹ Buhari ti saaju pase ki awọn osise alabo pẹtu si aawọ naa Aarẹ Buhari parowa yìí nigba to n ṣe ìpàdé pẹlú awọn alenuloro ni ìpínlè náà lọjo ìṣẹgun. Buhari ni ipaniyan to gbérí padà ní Plateau jẹ́ òun tó n kọni lominu ati pé ìjọba òun yóò wá wọ̀rọ̀kọ̀ fí ṣada láti dẹkùn rẹ Ọpọ èèyàn ló ti pàdánù ẹmí wọn nínú ikọlù láàrin àgbẹ àti darandaran. Ìṣẹlẹ yìí sí ti mu kí ọpọ bẹnu àtẹ lú ètò ààbò lorílẹ̀-èdè eleyii ti wọn ní ko gbámúsé. Ṣáájú ní igbákejì ààrẹ Yemi Osinbajo ti ṣe àbẹwò sí ìpínlè náà.,0,yoruba "radionet Luis Carlos Díaz , ti wà nínú àtìmọ́lé agbófinró Ìlú .",0,yoruba Àwọn ẹ̀kọ́ dídì yìí ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa aráyé: ti o tẹ.,0,yoruba "Nígbà àkerekere, Ọba fi. Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.. Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba "ojú onà. ti Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Baàlè ri Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba @user 📝 àkẹ́sàn báálẹ́ ọjá ✖️ Akẹ̀sán baálẹ̀ ọjà ✔️ #learnyoruba https://t.co/wAyPaGVK5v,0,yoruba Kò lè ṣí fáìlì ojú-iṣẹ́ %s fún aṣàfilọ́lẹ̀ pánẹ́ẹ̀lì %s%s,0,yoruba ìṣẹ̀: ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó ṣe pàtàkì.,0,yoruba ORIKI OFFA... EULOGY OF OFFA... #owe #oweleshinoro #oyo#osun #omoluabi #osogbo #ekiti #lagosstate #lagos #ondo #ogun #ilorin #ife #alafinofoyo #ibadan #throwbackthursday #yoruba #ikire #love #abeokuta #oshodi… https://t.co/t7EMK66yYz,0,yoruba "Ọmọ ijọ Sotitobire kan, to wa nile ẹjọ lọjọ Aje, lasiko ti igbẹjọ asaaju ijọ naa n lọ lọwọ lori ẹsun ijọmọgbe ti ba BBC Yoruba sọrọ. Ninu ifọrọwerọ naa, eyi to da lori ipo ti ijọ ọhun wa lasiko yii ti olori ijọ, Alfa Babatunde wa lọgba ẹwọn, ọmọ ijọ naa, to pe orukọ ara rẹ ni Yetunde salaye pe nkan ko dabi bo se n waye tẹlẹ rara. Yetunde ni lootọ ni isin n waye nile ijọsin Sotitobire amọ awọn ko lee lu ilu rara nitori gbogbo rẹ ni awọn oluwọde kan ti sun nina, lasiko ti wọn se iwọde wa sile ijọsin naa. ""Isìn ń tesiwaju pelu pé kò sí Àlùfáà Babatunde ni itosi, amọ lóòótọ́, kò dabi ìgbà tí bàbá wá nílé, kò sì ìlú lílu nítorí pe gbogbo àwọn èròjà wonyii ni wọn ti jo nina."" Igbẹjọ Alfa Babtunde si n lọ lọwọ, a mu ẹkunrẹrẹ iroyin naa wa fun yin laipẹ. Iléẹjọ́ kún fọ́fọ́ fún èrò nítẹ̀síwájú ẹ̀ṣùn ìjọ́mọgbé tí wọn fi kan aṣaájú ìjọ Sotitobire Ileẹjọ giga ilu Akurẹ tun kun fọfọ lọjọ Aje nitẹsiwaju ẹjọ Asaaju ijọ Sotitobirẹ, Alfa Babatunde, tijọba ipinlẹ Ondo fi ẹsun ajọmọgbe kan. Bẹẹ ba gbagbe, lati osu kẹjọ ọdun 2019 ni isẹlẹ kan ti waye ninu ijọ Sotitobire nilu Akure pe, ọmọ ọdun kan, Gold Kọlawọle sọnu ninu ijọ naa, ti wọn ko si ri di akoko yii. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Eyi lo mu ki ijọba ipinlẹ Ondo fi gbe asaaju ijọ naa ls sile ẹjọ lẹyin ti gbogbo aayan lati ri ọmọdekunrin naa ja si pabo. Nibi igbẹjọ losu to kọja, ni adajọ ile ẹjọ giga, to gba ẹjọ naa lọwọ ileẹjọ majisireti ti sun igbẹjọ siwaju di ọjọ Aje, ọjọ Kẹrindinlogun, ikẹtadinlogun ati ikejidinlogun osu kẹta ọdun yii. Ni deede aago mẹsan aarọ si ni awọn osisẹ ọgba ẹwọn ti gbe Alfa Babatunde de sileẹjọ ati awọn afurasi ọmọ ijọ rẹ miran ti wọn fi ẹsun ajọmọgbe kan pẹlu rẹ. Asọ alawọ eweko, tii se asọ ọgba ẹwọn si ni Babatunde wọ wa sile ẹjọ, ti wsn si fi ọkọ ọgba ẹwọn bọọsi kan gbe wa sibẹ. Coffee Painter: Adebukola ní kò sí ìrànwọ́ lẹ́yìn ẹ̀kọ́ girama lòun ṣe ń ya àwòrán Bi igbẹjọ naa ba se lọ, ni BBC Yoruba yoo maa mu wa fun yin.",0,yoruba "Yàtọ̀ sí ká fi bọ́tọ ṣe ajílẹ̀ fún nǹkan ọ̀gbìn, ó tún níhun à á fi í ṣé. #Eleboto",0,yoruba "Pẹ̀lú àtìlẹ́yìn àwọn onínúure tí ó ti dáwó fún iléèwé náà , owó tí ó kù ní sísan ṣì pọ̀ tó bẹ́ẹ̀ tí ó fi jẹ́ wípé , ó ṣe é ṣe kí ilẹ̀kùn - un iléèwé náà tí ó wà nínú Ilé Àwọn Ẹ̀ṣọ́ Aṣọ́bodè Àtijọ́ .",0,yoruba ọkunrin ri pe jẹ́ pàtàkì wey ti o nuni ti o ní wúlò.,0,yoruba Ìyá fi. Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.,0,yoruba Àkóbì níjó òní nípa iṣẹ́ aláwọ̀ lo je ti ibile.,0,yoruba "Họnọrebu Adebo Edward Ogundoyin ati Họnọrebu Olakunle Taiwo Oluomo Ni ipinlẹ Oyo, Họnọrebu Adebo Edward Ogundoyin ti ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party to n ṣoju ẹkun idibo Ila Oorun Ibarapa nipinlẹ Oyo lo bori. Bakan naa ni wọn yan Họnọrebu Abiodun Muhammed Fadeyi to n ṣoju ẹkun idibo Ona Ara ni igbakeji adari ile aṣofin ipinlẹ Oyo. Iba Gani Adams: Bẹ́ẹ gbé màláíkà kan lọ sí Aso Rock, kò lè ṣàṣeyọrí Ẹwẹ, bo ṣe n waye nipinlẹ Oyo naa lo n ri bakan naa ni Oke-Mosan, Abeokuta ipinlẹ Ogun nibi ti Họnọrebu Olakunle Taiwo Oluomo jawe olubori gẹgẹ bii adari ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Ogun. Olakunle n ṣoju ẹkun idibo Ifo 1 nile igbimọ aṣofin ipinlẹ Ogunti wọn si yan an lai ni alatako kankan. Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun Bẹẹ si ni wọn yan Họnọrebu Abiodun Muhammed Fadeyi to n ṣoju ẹkun idibo Ijebu North II gẹgẹ bii igbakeji adari ni ipinlẹ Ogun. Idibo awọn mejeji si igbimọ aṣofin ikẹsan waye lai si alatako kankan.",0,yoruba Fún àpẹẹrẹ: olojò. Victim ni olojò. #Yoruba @user @user @user @user @user @user,0,yoruba àwọn iṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jẹ́ dára jù...,0,yoruba Tolulope Adeleke Aire: Mo wòye pé àwọn ọkùnrin Nàìjíríà kò fi bẹ́ẹ̀ mọ̀ nípa ìtọ́jú ọmọ tuntun,0,yoruba "Ọpọ awọn ọrẹ rẹ ti wọn dijọ n sisẹ tiata ni wọn ti n salaye nipa iru eeyan ti Arigbabuwo jẹ ati bo se lo igbe aye rẹ nigba to wa loke eepẹ. Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, ọkan lara awọn ọrẹ timọtimọ Toyọsi Arigbabuwo ti wọn jọ n sisẹ tiata, Alhaji Musiliu Dasọfunjo salaye pe Arigbabuwo jẹ akikanju eeyan pupọ pupọ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Isẹ aransọ ni Toyọsi kọkọ kọ nigba aye rẹ ko to ya si idi isẹ tiata, to si n fi ẹsa ẹkun iyawo kewi, eyi ti awọn eeyan mọ si, ko to wa da ẹgbẹ tiata tiẹ silẹ taa mọ Toyọsi Arigbabuwo Theather Group ni adugbo Alekusọ-Oritamẹrin nilu Ibadan. Oloogbe Sẹgun Olubukun, toun naa jẹ ilumọọka osere ori itage ni ọga to kọ Arigbabuwo ni isẹ tiata. Lẹyin ti Arigbabuwo si da ẹgbẹ tiata tiẹ silẹ lo bẹrẹ si ni se ere fun ileesẹ mohunmaworan ijọba apapọ lasiko to wa ni WNTV ko to wa di NTA bayii. O to si tun maa n kewi fun awọn ileesẹ Redio kaakiri, paapa ni Radio Nigeria to wa nilu Ibadan to fi mọ awọn eto miran lorisirisi. Ti a ba si n sọrọ nipa ihuwasi oloogbe Arigbabuwo, Dasọfunjo ni o jẹ onisuuru pupọ pupọ, ti kii ba eeyan kankan ja, ti ohunkohun kii si bi ninu, paapa ninu isẹ tiata. Dasọfunjo salaye pe 2018 ni Arigbabuwo kọkọ bẹrẹ aisan, to si se isẹ abẹ nile iwosan UCH, amọ aisan yii tun pada lọdun 2019, to si tun se isẹ abẹ fun igba keji, lẹyin eyi si ni ko lee jade sita mọ titi ti ọlọjọ fi de baa. Nigba to n sọrọ lori ipa ti ẹgbẹ awọn osere tiata ko lati seranwọ fun Arigbabuwo lasiko to wa lori idubulẹ aisan, Dasọfunjo ni ohun ko lee sọ pato ohun ti ẹgbẹ Tanpan abi ANTP se lati ran Arigbabuwo lọwọ. Amọ o ni ẹnikọọkan gẹgẹ bii ọrẹ Arigbabuwo lo dide lati sa ipa tiẹ fi seranwọ fun oloogbe naa. Dasọfunjo ni manigbagbe ni Arigbabuwo jẹ ninu isẹ tiata, to si ti kọ ọpọ eeyan nisẹ tiata, koda ọkan lara wọn ti di ọjọgbọn ni ọgba fasiti bayii. O wa fọwọ gbaya pe awọn ti n seto lati da ajọ alaanu kan silẹ, taa mọ si Foundation loruks oloogbe Toyọsi Arigbabuwo, eyi ti wọn yoo maa fi se iranti rẹ, ko maa ba parun. Bakan naa, ọrẹ minu miran fun Arigbabuwo ninu isẹ tiata, Gbọlagade Akinpẹlu, tawọn eeyan mọ si Ogun Majek naa sọ tẹdun tẹdun fun BBC Yoruba pe, isẹ tiata ye daada, o lee sere, o lee kọrin, to si tun lee kewi. O ni Arigbabuwo jẹ eeyan jẹjẹ, ti kii fa wahala lẹsẹ abi se ijangbọn ti awsn yoo si maa ranti rẹ fun ọgbọn to maa fi n pari ija laarin ẹgbẹ ati sna alaafia to maa n san laarin awọn eeyan. Àlàyé rèé lórí ikú tó pa Toyosi Arigbabuwo Iku doro, iku ti sika, iku tun ti mu ọkan lara awọn ọlọpọlọ pipe, osere ori itage, Toyosi Arigbabuwo lọ. Iroyin to tẹ wa lọwọ salaye pe irọlẹ ọjọ Aje ni Toyọsi mi kanlẹ lẹyin aisan olosu mẹfa to ti n baa finra, ti okiki si gbalẹ kan lasiko kan pe o wa lori aisan nile iwosan nla UCH nilu Ibadan. Toyọsi Arigbabuwo, ẹni ti wọn bi soke eepẹ lọjọ kẹta osu Kẹta ọdun 1948, eyiun ọdun mejilelọgọta sẹyin, lasiko to wa loke eepẹ jẹ ilumọọka nidi isẹ tiata, to si maa n fi ẹkun iyawo dabira lasiko ere sise. Bakare Mubarak: ọ̀pọ̀ èèyàn ló máa ń fẹ́ dúró sí ẹgbẹ́ mí tójú si máa n tì mí O maa n ke ewi, to si tun jẹ ẹni to gbe ẹsin Islam sori titi to fi tẹri gbasọ, koda oun ni alarina fun ẹgbẹ awọn musulumi to wa lagbegbe Apẹtẹ-Awọtan nilu Ibadan. Ọsan oni ni wọn yoo fi ara rẹ fun ilẹ nile rẹ to wa ni Awọtan nilu Ibadan",0,yoruba ni a ní láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba RT @user: @user Eni to ba rin ni abata. O ti di dandan ki won fi ekolo lo abi ki o ba ara re ninu iho akan. Eje ki a gbe igbe …,0,yoruba "Lẹyin ọpọlọpọ iforigbari, ile asofin agba buwọlu awọn orukọ ọga agba tuntun fajọ INEC Awọn oga agba tuntun fun ajọ INEC ti wọn buwọlu orukọ wọn ni, Baba Abba Yusuf (Borno), Dr. Uthman Abdulrahman Ajidagba (Kwara), Mr. Segun Agbaje (Ekiti), Dr. Cyril Omorogbe (Edo), Yahaya Bello (Nasarawa), Dr. Emmanuel Alex Hart (Rivers), Mohammed Mogaji Ibrahim (Gombe). Awọn asofin agba orilẹede Naijiria buwọlu orukọ wọn lọjọbọ lẹyin ti igbimọ tẹẹkoto to n mojuto ọrọ ajọ INEC nile asofin agba ti se ayẹwo lori awọn orukọ naa. Bi a ko ba ni gbagbe, nibẹrẹ ọdun 2017 ni awọn asofin agba orilẹede Naijiria tẹsẹ bọ sokoto kannaa pẹlu ileesẹ aarẹ lori bo se kuna lati yọ olori ajọ to n gbogun tiwa ibajẹ lorilẹede yi, EFCC, Ibrahim Magu, ẹni tawọn asofin ti kọkọ wọgile orukọ rẹ gẹgẹbi alaga ajọ EFCC nitoripe gẹgẹbi iwoye ati iwadi wọn, Magu ko kunju iwọn lati lewaju ajọ to se pataki bii EFCC. Eeyan mẹsan nile asofin agba kede orukọ wọn gẹgẹbii ọga agba tuntun fajọ INEC Ọjọ pẹ ti awuyewuye ti n waye lori iyansipo awọn ọga agba tuntun fajọ INEC Sugbọn ileesẹ aarẹ orilẹede Naijiria kọ jalẹ wipe afori afọrun, Magu n lawọn fẹ nipo ọhun eyi ti ko dun mọ awọn asofin agba nin, ti wọn ni bi adiyẹ da mi loogun nu, maa fọ lẹyin lawọn yoo fi ọrọ naa se. Wọn tun fi kun pe bi ileesẹ aarẹ ba faake kọri lori ọrọ naa, awọn pẹlu ko ni buwọlu awọn orukọ awọn ọmọ igbimọ lajọlajọ gbogbo tileesẹ aarẹ ba mu tọọ wọn wa, bẹrẹ pẹlu orukọ awọn ti wọn fẹ yan sipo lọgalọga lẹnu isẹ ajọ eleto idibo apapọ orilẹede Naijiria. Loju opo Twitter rẹ, aarẹ ile asofin agba Bukọla Saraki ni oun nireti pe igbesẹ ile asofin agba naa yoo seranwọ lati ko ipa si ifsẹmulẹ eto idibo to mọyan lori jakejado orilẹede Naijiria.",0,yoruba "Lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, Ikimot ní kẹ́kẹ́ Marwa ni obinrin kan fi ji oun gbe salọ, nigba ti oun n pada bọ lati ile ẹkọ ni Ebute Mẹta. O ni obinrin naa ta oun ni ẹgbẹrun lọna ọtalelọdunrun o din mẹwa naira (₦350,000) fun ẹlomiran, Christiana Onuchukwu, to n gbe ni adugbo Fadeyi, to si n fi oun se isẹ agbara ati iya ajẹkudorogbo. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Iya yii lo ta oun nidi kan lati pada wa sile lẹyin ọdun marun ti wọn ti ji oun gbe lọ silẹ ibo. Ninu ọrọ tiẹ naa, Mama Ikimot salaye pe awọn ọrẹ Ikimot ti wọn dijọ n pada bọ lati ileẹkọ sọ pe, ipanu ‘Cheese ball’ ni obinrin kan fun Ikimot, to fi gbe sinu kẹkẹ Marwa. O ni oun gba Ikimot wo lẹyin ti iya rẹ ku ni, bẹẹ ni oun gbinyanju lati wa ọmọ naa, toun si ta awọn goolu oun lati wa a, sugbọn oun sọ ireti nu lẹyin ọdun meji, ko to fi ẹsẹ ara rẹ rin pada wale.",0,yoruba ẹ̀ká ojú. Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.,0,yoruba "ọmọ ri pe lẹ ìkòkò wey ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn ẹ̀kọ́ ọmọ aláwọ̀ wà.",0,yoruba ojú òní. ti Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìṣẹ̀: ti o nuni ti o wulo.,0,yoruba ó wáyé. ti Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jẹ́ dára jù...,0,yoruba Diego Maradona: Ọlọ́pàá 200 ni yóò máa ṣọ́ ibojì Maradona torí àwọn olè,0,yoruba lojiji. Alàji lo ni ìgbà mi owó àkokò eyti o gbe lori àìmọ́ kọ.,0,yoruba yii nípa iṣẹ́ aláwọ̀ lo je ti ibile.,0,yoruba "Odun 2020 lo yẹ ki idije ere idaraya Olimpiki Tokyo 2020 ko waye, sugbọn wọn sun siwaju nitori aarun coronavirus si 2021. Gẹgẹ bi awọn ere idaraya Olimpiki Tokyo yii yoo ṣe bẹrẹ ni ọjọ kẹtalelogun (23) oṣu keje, 2021, a n fi asiko yii wo awọn elere idaraya ilẹ Afrika to yẹ ko wo ninu idije yii. Awọn elere idaraya wọnyi ni a yan lati orisirisi ere idaraya leyi ti wọn kò ṣe awọn miran ni apa ilẹ Afrika ati wipe ara awọn olukopa yii leti ni iriri olimpiki tẹlẹ ri tabi kò jẹ fun igba akọkọ wọn.ii. Ilana ta lo: Awọn elere idaraya Afirika wọnyi ṣe aṣoju awọn oriṣiriṣi awọn agbegbe nílẹ Afrika. Wọn yan wọn lori iriri wọn ní Olimpiki, awọn ami ẹyẹ ti wọn gba ati iyasọtọ ti iṣẹlẹ ere idaraya wọn. Igboriyin: Olootu atẹjade Nkechi Ogbonna, Princess Abumere pẹlu Muthoni Muchiri. Ayaworan Olaniyi Adebimpe àti Millicent Wachira. Iṣẹ ayelujara: Purity Birir. Atilẹyin afikun: Sally Morales and Celestine Karoney. Aworan: Getty Images, The International Basketball Federation, AFP, Nigerian News, Nigerian Rowing Canoeing and Sailing Federation, Nigerianews, Mekseb Debesay, Sailing Club of Mozambique, Giana Farouk, EPA, Press Focus/News Pix via PA, Erwythereyet via Twitter, Bruce Viaene via Olympics, ClimbZA, DW via Club of Mozambique.",0,yoruba "Ṣùgbọ́n lásìkò àjàkálẹ̀ ààrùn Coronavirus yìí, ọ̀pọ̀ aboyún ni ẹ̀rù ń bà. Ṣáájú ni ààrẹ àwọn agbẹ̀bí Franka Cardee tí ké sí gbogbo àwọn obìnrin tí ó lè máa bẹ̀rù bí wọn yóò ṣe rùú là lásìkò yii, àti ọ̀nà tí yóò gbà láti dáàbò bo ara wọn. Ṣe ó tọ̀nà láti máa lọ fún àyẹ̀wò ìgbàdédéìgbà àwọn aláboyún? Ọ̀pọ̀ àwọn aboyún ni ẹ̀rù ń bà láti láti lọ sí ilé ìwòsàn fún àyẹ̀wò ìgbàdédéìgbà tí ó yẹ kí wọn máa lọ fún nítorí wọn fẹ máa tẹ́lẹ̀ àṣà sún - fúnmi - ń - sún fún ọ. Bó tilẹ̀ jẹ́ pé ọ̀pọ̀ ǹkan lọ tí yí padà lágbàáyé lẹ́nu lọ́lọ́lọ́ yìí, ọ̀pọ̀ àwọn nọ́ọ̀sì agbẹ̀bí lọ sì ti ń ṣe ìrànwọ́ fún àwọn aboyún lat máa dá wọn lóhùn láti orí aago ìbánisọ̀rọ̀. Cadée gba àwọn aboyún níyànjú láti wádìí lọ́dọ̀ àwọn olùtọ́jú wọn ọ̀nà tí ó dára jù lásìkò yìí láti ṣe ètò àyẹ̀wò ìgbàdédéìgbà tí alaboyun máa ń ṣe Bi mo bá láàrùn COVID-19, ṣé mo leè ko ran ọmọ láti inú oyún ? Wọn ò tí rí kòkòrò Covid-19 ni ojú ara ìyá, tàbí lára ìwọ́ ọmọ tàbí láti inú omi ọyàn abiyamọ"" , ìwádìí ń lọ lọ́wọ́ lórí èyí ṣùgbọ́n àwọn onímọ̀ kò tíì salábàpàdé Covid-19 nínú olubi ọmọ nínú ẹ̀jẹ̀ .Nkan ti o se pàtàkì jù lọ ní pe ki aboyún sá gbogbo ipá rẹ̀ láti dènà níní ààrùn Coronavirus, àmọ́ óò, tí ó bá lóyún tàbí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ bímọ, ó ṣe pàtàkì láti àwọn elétò ìlera kí ó sì tẹ̀lé ìlànà tí wọ́n bá ní kí ó tọ̀ Mo ń ròó láti bímọ sí ilé ìwòsàn, ṣe ìpinnu tó tọ̀nà ni? Ó ṣe pàtàkì láti bèrè lọ́wọ́ àwọn agbẹ̀bí tàbí dókítà wọn ibi tí ó dára jù láti bímọ sí. Cardee ni èyí dálé ipò tí obìnrin náà wà, irú ìdojúkọ rẹ̀ àti bí ilé ìwòsàn ètò ìlera àgbègbè rẹ̀ bá ṣe rí Ṣe àwọn ẹbí mi le wà pẹ̀lú mi ti mo bá fẹ́ bímọ? Fún irú nkan báyìí oríṣiríṣi orílẹ̀-èdè lọ ní àṣà tí wọn. Ṣùgbọ́n Cadée nígbà gbọ́ pé ó ṣe pàtàkì kí aláboyún ni ẹni tí yóò wà ní àyíká rẹ̀ lásìkò ìrọbí níwọ̀n ìgbà tí ẹni náà bá ti dáàbò bo ara rẹ̀, bí àpẹẹrẹ kí ó wọ ìbòjú-bomu ni yàrá ìgbẹ̀bi kí ó sì máa fọ ọwọ rẹ lóòrè kóòrè pẹ̀lú ọmọ àti ọșẹ Ẹ̀rù ń bà mí láti bímọ, kíni mo fẹ́ ṣé, ní àsìkò yìí ? Ṣe eto bí ose fẹ́ kí gbogbo nkan ó rí, èyí yóò mú àdínkù bá ẹ̀rù. Gba nọ́mbà ìbánisọ̀rọ̀ ẹni tí ó fẹ́ láti bá sọ̀rọ̀ nígbà tí ọmọ bá ti ń mú ọ, mọ ẹni tí fẹ́ kí ó ràn ọ lọ́wọ́ lásìkò ìrọbí, máa ṣe àwọn ǹkan bí eré ìdárayá nínú ilé, èyí yóò máa mú kí ara rẹ balẹ̀ tí yóò sì mú ọkàn rẹ kúrò níbi ẹ̀rù. Máa ṣe eré ìdárayá èémí, pee nọ́ọ̀sì agbẹ̀bí rẹ tí ó bá kojú ìṣòro kankan. Tọju ara rẹ dáadáa, jẹun dáadáa, mumi dáadáa, feyinti kí inú rẹ sì máa dùn pé ó ní oyún. Irú ìbéèrè wo ni mo le bí àwọn elétò ìlera mi? Tí àsìkò bá ti tó láti bímọ, ó ṣe pàtàkì kí ó bere àwọn ìbéèrè tí ó bá wù ọ Cadee sọ pé ó lè béèrè àwọn ìbéèrè wọ̀nyìí: Kini nkan ti obìnrin tó bá fẹ́ lọ bímọ nílé ìwòsàn yẹ kí o gbé dání? Obìnrin kò nílò láti gbé tí ó pọ̀ ju bó ṣe yẹ lọ, ìwọ̀nba èyí tí àwọn òṣìṣẹ́ ìlera bá ní kí ó mú wá náà ni, ó sì gbọdọ sọra gidi. Ní kété tí mo bá ti bímọ kí ló yẹ kí n ṣe láti dáàbò bo ọmọ mi? Nkan ti o dára jù ni pé ṣókí ni, ìwọ àti ẹbi rẹ lọ ṣe pàtàkì jù kii se àkókò láti máa jẹ ki àwọn àlejò wò "" Tí ó bá ti ní àwọn ọmọ nílé, má ṣe gba wọn láàyè láti bá àwọn míràn ṣeré. Rí dájú pé ebi rẹ ń fọwọ́ wọn pẹ̀lú omi àti ọṣẹ lóòrèkóòrè. Ìmọ̀ràn Cardee Aláboyún ni mí, báwo ni n o ṣe dáàbò bo ara mi ni àsìkò Covid-19 yìí. Ìwádìí tí fi hàn pé, àwọn aláboyún kò sì lára àwọn tí àsìkò yìí ni ewu fún jùlọ láti ni ààrùn Coronavirus ṣùgbọ́n nítorí àwọn àyípadà tó dé bá ara ati èròjà tó ń f'ára lókun tí yóò ti gbọ̀jẹ̀gẹ́, ó ṣe pàtàkì lat ṣọ́ra. Ó gba àwọn obìnrin ni ìyànjú láti máa tẹ́lẹ̀ àwọn ìlànà yìí: Àwọn òbí ń fún ọmọ wọn lọ́yàn ""Ní nkan ti a mọ̀, kò sì ewu nínú kí ọmọ máa mú ọyàn daada, gẹ́gẹ́ bí Cadee ṣe sọ gbogbo ìwádìí tí wọn ti ṣe kó sì àfihàn pé àwọn ọmọ lè kó aarun Coronavirus láti ara ọmú mímú, nítorí náà ìyá leè fún ọmọ lọ́mú Kini mo ní láti ṣe tí mo bá ń gbé ilé Kojú-sí - mi-kín-kojú-sì-ọ? Ọ̀pọ̀ àwọn obìnrin ni wọn ń gbé ilé tí ó súnmọ́ ara wọn èyí sì mú kí ìsúnfúnraẹni kí ó nira díẹ̀. Ó ní kí àwọn ènìyàn gbìyànjú láti má súmọ́ ẹni tí ó bá ní oyún, tí ó bá sì ṣeé ṣe kí wọn pèsè yàrá ìgbọ̀nsẹ̀ tí ó yàtọ̀ fún aláboyún Bákan náà lọ fi kún pé ó ṣe pàtàkì kí a máa fí omi àti ọṣẹ fọ ọwọ ni gbogbo ìgbà. Orísun: Unicef",0,yoruba nípa àlùfáà. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jẹ́ dára jù...,0,yoruba tí yóò rò papa re yóò ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "RT @user: Ǹjẹ́ ìwọ́ mọ̀ wípé bí ẹni ń forin kíkọ ṣe agbe (tọrọ owó) ni ọ̀ràn náà rí, ni a fi pe àwọn òǹkọrin/olórin ni """"""""""""""""""""""""""""""""alágbe""""""""""""""""""""""""""""""""? Àṣàa…",0,yoruba Afirika. Ibo lò ń lọ? Ibi tí o kọrí sí yìí ò tọ̀nà ire rárá o. Àyípadà pọn dandan báyìí o. !!,0,yoruba RT @user: Kí orí wa má se gbàbòdè. Kí elédàá wa gbémi dé èbúté ire àti ayò. E se Àmín ńlá sí Àdúrà Òwúrò yìí. @user @user …,0,yoruba Kí ni ìyàtọ̀ bàtà àti sálúbàtà? #Ibeere #Yoruba,0,yoruba toò gbogbo yín ẹ ṣe o ẹ ṣeun fún ìwé tí ẹ fi ranṣẹ àti ìfe tí ẹ ni si wa ire ni tiwa o,0,yoruba "Yup, YOU got this! Maferefun Orisa! #orisha #santeria #lukumi #yoruba https://t.co/143IUjuCgb #family https://t.co/b7ciYyZEv3",0,yoruba Ìlú yorubá lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba @user Yó yẹ yín o jàre,0,yoruba "fun ipilẹ̀ ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Nitori eyi, ara eni ni nfàn ojú kakaaki.",0,yoruba "Ile ẹjọ giga to kalẹ si ilu Akure ti sun igbẹjọ pasitọ ijọ Sotitobire Miracle Centre, Alfa Babatunde Sotitobire si ọjọ kẹrinla, oṣu Kẹsan an ọdun 2020. Igbesẹ yii lo waye lẹyin ti pastitọ naa atawọn mẹfa miran ti wọn fẹsun kan pari awijare wọn niwaju ile ẹjọ ọhun. Eyii n tumọ si pe o ṣeeṣe ki ile ẹjọ naa fi ọjọ ti yoo ṣe idajọ rẹ lede lọjọ naa. Lẹyin ti ẹlẹri ikarundinlogun ti olujẹjọ pe sọ tẹnu rẹ tan, adajọ to n gbọ ẹjọ ọhun, Olusola Odusola mu Sotitobire si ọjọ kẹrinla, oṣu Kẹsan an ọdun 2020 gẹgẹ binọjọ to kan ki ọjọ idajọ to de. O ni oun ko ni gba ki agbẹjọro ijọba tabi agbẹjkọro Sotitobire da oju ẹjọ ọhun ru nitori pe idajọ odo ni ou n fẹ lori ọrọ na. Wolii Sotitobire atawọn ọmọ ijọ rẹ mẹfa miran dẹni to n kawọ pọn tojọ niwaju adajọ lẹyin ti ọmọ ọdun kan, Kolawole Gold, dede poora ninu ijọ rẹ lopin ọdun 2019. Sotitobire Latest news: Adájọ́ yarí lórí bí àwọn ẹlẹ́rìí ṣe ń fi ẹjọ́ falẹ̀ Ile ejọ giga tipinlẹ Ondo, to kalẹ si ilu Akure, ti fari ga lori bi igbejọ Alfa Babatunde se n fa nilẹ bii igbin. Adajọ Olusegun Odusola to n gbọ ẹjọ ẹsun ijọmọgbe ti wọn fi kan wolii ijọ Sotitobire naa, lo woye bẹẹ lasiko igbẹjọ to waye lọjọ Isẹgun. Adajọ Odusola wa fajuro lori bi agbẹjọro fun olujẹjọ, Alfa Babatunde, se tun beere pe ki wọn sun ẹjọ naa siwaju nitori ailera rẹ. Adajọ naa ni igbẹjọ ẹsun ijọmọgbe naa gbọdọ wa si òpin kí oṣù keje tó ń bọ̀ ó to parí. Ikede yii si ni adajọ naa tun fi n sọ ero ọkan rẹ, lori bi awọn ẹlẹrii ti olujẹjọ naa pe, se n mu isunsiwaju ati ifasẹyin ba ẹjọ naa. Adajọ Odusola wa sun igbẹjọ náà siwaju di ọjọ́ Kẹrìnlá, ikẹẹdogun àti ìkẹrin dínlógún oṣù keje ọdún 2020. Wọn ti sún igbejo sì ọlá ọgbọ́n ọjọ́ oṣù kẹfà fún ìparí gbígbé jọ àwọn ẹlẹri wòlíì Alfa Babatunde. Adajọ tí wá ṣàlàyé pé, kí wọn gbìyànjú láti jẹ ki awon Ẹlẹ́rìí náà pọ ni iye bíi bẹẹ kọ, ilé ẹjọ́ yóò pé àwọn ẹni a fẹ̀sùn kan, ní pàtàkì Alfa Babatunde láti jẹ ẹlẹ́rìí ara rẹ nítorí wọn fẹ ki igbejo náà tètè parí. Ṣáájú ni àwọn eleri méjì tí sọ̀rọ̀ gbé sẹ́yìn Alfa Babatunde dípò àwọn mẹta tí ó yẹ kí o sọ̀rọ̀. Èyí ló mú kí Adajọ Olusegun Odusola pé àkíyèsí ilé ẹjọ́ pé, tí àwọn Ẹlẹ́rìí kò bá pè dáadáa lọ́nà, olórí ẹni afesunkan ni yóò ṣe ẹlẹ́rìí ara rẹ. Wolii Babatunde Sotitobire tun de ile ẹjọ giga ipinlẹ Ondo lonii lati jẹjọ nipa Gold Kolawole ọmọ ọdun kan to di awati nile ijọsin rẹ l'Akure. Gẹgẹ bo ti maa n ṣe ni kete to ba ti de ile ẹjọ nipa fifọ ọwọ ati lilo sanitaisa ko to wọ ile ẹjọ lọ. Ọjọ pẹ ti ọrọ bi ọmọ ọdun kan to sọnu ni ie ijọsin kan nipinlẹ Ondo eyi ti Wolii Alfa Babatunde Sotitobire n dari ẹ ti n waye. Lonii, ile ẹjọ giga ipinlẹ Ondo tun ti pe Wolii Sotitobire atawọn to pe ni ẹlẹri rẹ ki wọn wa wi tẹnu wẹnu wọn. Lọsẹ to kọja, iyawo rẹ ti kun awọn ẹlẹri to si sọ ohun to mọ, bakan naa ni awọn eeyan ogun mii naa ti n jẹri ohun ti wọn mọ. Nile ẹjọ, wọn wo awọn fọran kọọkan lori ifọrọwanilẹnuwo to waye pẹlu Wolii naa. Bakan naa lọsẹ to kọja, ijọba ipinlẹ Ondo ti ni A kò ní fara mọ́ fífi àkókò ṣòfò lórí ẹjọ́ Sotitobire - Ìjọba Ondo Bí ìgbẹ́jọ́ wòlíì Sotitobire ṣe ń lọ lọ́wọ́ nílé ẹjọ́ lónìí rèé Ẹ tẹti leko lonii lori ikani yii, BBC Yoruba fun ẹkunrẹrẹ bo ba ṣe n lọ nile ẹjọ.",0,yoruba a pọ̀ tí a sùn lálẹ́ àná ojú orun ni àwọn kan gbà dé ojú ikú àmọ́ àwa ò gba ojú orun wọ sàárè bàbá a dúpẹ́ pé o pa wá mọ,0,yoruba Bebelu ojú omi; ewé yìí a máa yọ sí orí omi ni ìparí ọdún (lásìkò ọyẹ́). #Bebeluojuomi #waterhyacinth #InYoruba http://t.co/reIx0QJCqw,0,yoruba lòdì Àbẹ́òkúta. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba o ó làlùyọ láyé dúndùn dúndùn lọsàn wa yóò máa so àṣẹ,0,yoruba àwọn alákòó. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ẹkọ́: ti o nuni ti o ní wúlò.,0,yoruba Èyí ni òun tí a kọ eḳọ nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o nuni ti o ní wúlò.,0,yoruba mo ranti orin yii daada nigba ewe mi,0,yoruba "Awọn ara adugbọ to sọrọ ni arabinrin Olufisayo Fagbemi ji laarọ kutu bi aagọ marun un lati fọ aṣọ ni iwaju ile, ki wọn to ba a ninu agbara ẹjẹ. Lẹyin ti wọn sa a ni ada ni iwaju ori ni Ọjọru. Awọn ara adugbo wi pe ẹni karun un ni yii laarin oṣu kan ti wọn ti da ẹmi wọn legbodo lagbegbe yii. Bẹẹ ni wọn kesi ijọba lati ṣeranwọ fun wọn, ki oju awọn aṣebi yii tete han sita.",0,yoruba "Kò sí ẹni tí kò ní kú, kò sì ẹni tí ìta baba rẹ̀ kò ní hu koríko. Gbajúgbajà oní wáàsí ẹ̀sìn Islam, Alfa Buhari ọmọ Musa ti rọ gbogbo àwọn ènìyàn pàápàá àwọn oníṣẹ́ tíátà láti máa rántí ikú nínú gbogbo ìṣe wọn. Alfa Musa sọ èyí níbi àdúrà ọjọ́ mẹ́jọ fún olóògbé Kunle Adetokunbo, tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ mọ̀ sí Dejo Tunfulu. Ní ilé Dejo Tunfulu ní ìpínlẹ̀ Eko ní àdúrà Fidau náà ti wáyé láti fi ṣẹ̀yẹ ìkẹyìn fún olóògbé náà. Ní ọjọ́ Kìíní, oṣù Kẹrin, ọdún 2022 ni Dejo Tunfulu jáde láyé lẹ́yìn àìsàn ráńpẹ́ díẹ̀. Kìí ṣe àwọn òṣèré tíátà nìkan ni ikú ń pa: Alfa Buhari ọmọ Musa ní kí àwọn onítíátà rí ikú tó ń pa àwọn akẹgbẹ́ wọn gẹ́gẹ́ bí àdánwò nítorí kìí ṣe agbolé tíátà nìkan ni ikú ti ń ṣọṣẹ́ ṣùgbọ́n nítorí tí àwọn onítíátà lókìkí ni ariwo ikú wọn ṣe máa ń pọ̀. Alfa Buhari rọ àwọn onítíátà láti máa fi ikú tó ń pa àwọn ojúgbà ṣe ọgbọ́n nítorí ikú tó ń pa ojúgbà ẹni òwe ló ń pa fún ni. Bákan náà ló ní nǹkan kan ni yóò pa èèyàn láyé nítorí gbogbo ẹ̀dá ni yóò tọ ikú wò, gbogbo ohun tó ń ṣe ẹ̀mí ni yóò di ìtàn ní ọjọ́ kan. Àti wí pé kò sí ẹni tí ó mọ ọjọ́ tí òun yóò lọ nítorí òjijì ni ikú máa ń dé bá ni àti wí pé ta ló mọ ẹni tí ikú kàn lágbo eré tíátà. Ó wá pàrọwà sí gbogbo ènìyàn láti máa ṣe iṣẹ́ rere ní gbogbo ìgbà nítorí kí ikú le ká iṣẹ́ rere mọ́ wọn lọ́wọ́ lásìkò tí ọlọ́jọ́ bá dé àti pé kí àwọn ènìyàn le máa ròyìn wọn pẹ̀lú ìwà dada lẹ́yìn tí wọ́n bá lọ tán. Ẹ máa rántí àwọn ọmọ Dejo Tunfulu: Alfa Buhari rọ àwọn òṣèré tíátà láti ṣẹ̀yìn Dejo Tunfulu gẹ́gẹ́ bí wọ́n ṣe ṣojú. Ó pàrọwà sí wọn láti máa tọ́jú àwọn ọmọ tí olóògbé náà fi sáyé nítorí ẹni tó ṣojú kò dàbí ẹni tó ṣẹ̀yìn. Bẹ́ẹ̀ náà ló tún rọ wọ́n láti ṣe àwọn ohun mánigbàgbé fún àwọn ọmọ náà. Bákan náà ló rọ àwọn ọmọ náà láti ṣe ara wọn lọ́kan, tó sì rọ àkọ́bí Dejo láti kó àwọn àbúrò rẹ̀ mọ́ra nítorí ẹ̀jẹ̀ kan ni gbogbo wọn. Ó gbà wọ́n lámọ̀ràn láti tẹ apá mọ́ṣẹ́ nítorí kò sí ẹni tó le ṣe ìṣe bàbá fún wọn mọ́ àti wí pé gbogbo ènìyàn náà ló ní bùkátà láti gbọ́. Àwòkọ́ṣe ni àwọn onítíátà jẹ́ fún àwọn ènìyàn Alfa Buhari ọmọ Musa tún tẹ̀síwájú láti sọ wí pé àwòkẹ́ṣe ní àwọn onítíátà jẹ́ fún àwọn ènìyàn nítorí ọ̀pọ̀ ló máa ń wo àwọn sinimá wọn láti fi mú ọgbọ́n kan tàbí òmíràn kọ́. Ó fi kun pé iyọ̀ ayé ni wọ́n jẹ́ àti pé Àlùfáà ni wọ́n pẹ̀lú nítorí ọ̀pọ̀ ìdílé ló ti tò nítorí fíìmù tí wọ́n wò. Bákan náà ló wá kọminú wí pé ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn tó ṣe wàhálà nídìí iṣẹ́ tíátà ni kò dúró jẹ pàápàá àwọn olùdarí eré, olóòtù àti àwọn òṣèré tí wọ́n bẹ̀rẹ̀ eré tíátà ní ìpìlẹ̀. Alfa Buhari ṣèrántí wí pé àwọn ènìyàn kìí tẹ̀lé àwọn onítíátà ní ìbẹ̀rẹ̀ pẹ̀pẹ̀ ṣùgbọ́n ó wú Ọlọ́run ló ṣe fi wọn hàn lásìkò yìí àti pé àlùbáríkà tí wọ iṣẹ́ náà ju ti àtẹ̀yìnwá lọ. Alfa buhari ṣàdúrà fún Kemi Afolabi Níbi wáàsí náà ni Alfa Buhari ti tún ṣe àdúrà fún Kemi Afolabi, ẹni tí àìsàn lupus ń yọ lẹ́nu. Alfa Buhari ka àwọn ẹsẹ̀ Àlùkùránì láti fi tọrọ lọ́wọ́ Ọlọ́run fún Kemi Afolabi láti gbà á lọ́wọ́ àìsàn tó ń ṣe. Ó ní Ọlọ́run nìkan ló mọ ibi tí ọ̀rọ̀ rẹ̀ yóò jásí àmọ́ kí àwọn akẹgbẹ́ rẹ̀ máa fi àdúrà ráńṣẹ́ si.",0,yoruba "Adajọ ni ki wọn ko awọn afurasi mejeeje naa lọ si ọgba ikọ ọlọpaa to n tako iwa idigunjale, SARS nilu Ibadan. Awọn mejeeje ni wọn fẹsun kan pe wọn ji awọn ọmọ naa ko ni ọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu kẹrin, ọdun 2020. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Orukọ wọn ni Mohammed Bashir, ẹni ọdun mẹtalelọgbọn, Oyeleye Opeyemi ẹni ọdun mẹẹdọgbọn, Olumide Ajala ẹni ọdun mẹrindinlogoji ati Taiwo Rildwan ẹni ọgbọn ọdun. Ìlànà IVF là fi bí ìbejì tẹ gbé lẹ́yìn idaduro ọdún méjìlá, ẹ jọ̀ọ́, ẹ tú wọn ṣílẹ̀ - Akeugbagold, aya rẹ bẹ̀bẹ̀. Awọn yoku ni Rafiu Mutiu ẹni ọdun marundinlogoji, Fatai Akanji ẹni ọdun mọkandinlaadọta ati Rafiu Modinat ẹni ọdun mọkandinlọgbọn. Ọga ọlọpaa Adegboye to ṣafihan awọn ọdaran naa nile ẹjọ majisireeti ọhun ni, wọn gba miliọnu mẹrin owo itanran lọwọ baba awọn ibeji naa, ki wọn to fi awọn ọmọ naa silẹ. Inú jìn! Akitiyan ọmọ'ṣẹ́ mi tó wà lára àwọn tó jí ìbejì mi gbé kò kéré níg Ẹsun marun un ni wọn fi kan meji lara awọn afurasi naa, eyiun, Rafiu Mutiu ati Rafiu Modinat, ti wọn gba pe kawọn afurasi ọhun fi awọn ibeji ọhun pamọ sinu ile wọn. Afurasi kẹfa, Fatai Akanji, nikan ni agbejọrọ wa ṣoju rẹ nilẹ ẹjọ naa, ti awọn to ku ko si ni agbẹjọrọ to n soju wọn. Igboho, Ajimobi, Makinde àti àwọn ọlọ́pàá ṣe bẹbẹ kí n tó rí ìbejì mi gbà padà Adajọ Emmanuel Idowu kọ lati gba oniduro fun gbogbo wọn. Lẹyin ti ko gba pe wọn ko jẹbi lo ni ki wọn ko gbogbo wọn lọ si ọgba ẹwọn ọlọpaa SARS, ti o si sun igbẹjọ naa si ọjọ kejila, oṣu kẹwaa, ọdun yii. akeugbagold video",0,yoruba "Kì í ṣe ohun tí ó kàn wá lórí àwọn ajàfúnẹ̀tọ́ obìnrin , kì í sì í ṣe ọ̀rọ̀ àgbélẹ̀rọ tàbí ọ̀rọ̀ òfìfo , LÓÒÓTỌ́ NI !",0,yoruba "Àkọ́kọ́, Alàji joko lòdì Ìbàdàn. Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.. Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "Ìlú tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Gùdẹ̀gùdẹ̀ yìí tún gbòde bí i t'àná. Ojú ọjọ́ tí ń mú ara ẹni lọ́ tìkọ̀tìkọ̀, tí ara ẹni kò ní yá sí ohunkóhun ní ṣíṣe, àfi bí oorun bí oorun ni yóò máa ṣ'èèyàn. https://t.co/KL5IwvU6la",0,yoruba "RT @user: *orin* o do wuro, ki a sun ji, ki angeli oluwa so gbowa, layo layo lan lole ko luwa so wa po ☺""""""""""""""""@user: Orun ya... (=|""""""""""""""""",0,yoruba RT @user: @user àwọn olólùfẹ́ẹ̀ rẹ ní kí n máa kí ẹ o. Wọ́n láwọn ń gbádùn 'Yorùbá Ìkíni' n. @user #Yoruba https://t.co…,0,yoruba "Pantami sọ loju opo Twitter rẹ pe, ile iṣẹ iroyin to gbe iroyin ọhun jade yoo foju ba ileẹjọ fún ibanilorukọ jẹ. Laarọ ọjọ Aje ni iroyin naa lu ori ayelujara pa pe, Amerika darukọ minisita eto ibaraẹnisọrọ gẹgẹ bi ọkan lara awọn to n ṣe onigbọwọ ẹgbẹ agbesunmomi. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Iroyin kan tiẹ ṣalaye pe, ẹka ileeṣẹ ọtẹlẹmuyẹ ilẹ Amerika sọ pe ki Pantami to de ipo minisita, lo ti jẹjẹ lati maa ṣe atilẹyin fún ẹgbẹ Al-Qaeda. Iwe iroyin naa tun sọ pe, Pantami ni ibaṣepọ pẹlu olori akọkọ fun ikọ Boko Haram, Mohammed Yusuf at'awọn olori ẹgbẹ Abu Quatada Al-Filistini ati Al-Qaeda. Amọ, minisita naa ni fun bi ọdun mẹẹdogun loun ti n ṣe idanilẹkọ tako awọn alakatakiti ẹsin. Pantami ni lori ọrọ lilo kaadi idanimọ NIN lati fi koju eto abo to mẹhẹ, o ni ijọba ko ni boju w'ẹyin. Ẹwẹ, iwadii fihan pe orukọ Pantami ko si ninu awọn orukọ awọn to niṣe pẹlu ẹgbẹ agbesunmomi ti awon ọlọpaa FBI fi lede. Agbẹnusọ fun minisita feto ibaraẹnisọrọ naa, Uwa Suleiman sọ fun BBC pe, iwe iroyin to gbe iroyin naa jade fẹ fi ba minisita lórúkọ jẹ lasan ni. Suleiman ni onimọ nipa ẹsin Islam ni Pantami, o sí kẹkọọ kaakiri orilẹ-ede agbaye to fi de orilẹ-ede Saudi Arabia. Female Car Painter: Èmi ní obìnrin àkọ́kọ́ tí yóò máa ṣiṣẹ́ akunmọ́tò ní Ibadan O ṣalaye pe koko miran to fihan pe Pantami ko mọ ohun kan nipa awọn ẹgbẹ agbesunmomi ni fidio ti olori Boko Haram Abubakar Shekau ṣe ninu eyi to ti sọ pe Pantami wa lara awọn eeyan ti oun fẹ pa. O ni Shekau sọ ninu fidio ọhun lọdun 2020 pe Pantami lọ darapọ mọ ijọba bo tilẹ jẹ pe onimọ nipa ẹsin musulumi ni.",0,yoruba ni òun tí a kọ eḳọ nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o nuni ti o nuni ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tó gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ àti ìbi.,0,yoruba "fè mú, Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa àwọn ènìyàn: ti o nuni ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Bàbá lo tun se fi.",0,yoruba ìyẹ̀ alẹ́. Èyí ni òun tí a kọ eḳọ nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó ṣe pàtàkì.,0,yoruba "kún jú, àwọn ènìyàn ni ó pa Ọba lo ni ìgbà mi owó àkokò, Alàji lo ìgbà ọkọ.",0,yoruba "joko. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "nípa ài: ti o nuni ti o nuni ti o nuni ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "RT @user: Hmm! Afi ki Eledua maa fi iso e so wa""""""""""""""""@user: Ọdún ń yí lọ biribiri.""""""""""""""""",0,yoruba Ọmọ lo ni àṣà yorubá eyti o gbe lori ọ̀run dídì.,0,yoruba ♫ èrò ọjà olówó jàlòlò jàlòlò èrò ọjà ọlọ́mọ jàlòlò jàlòlò ẹ mà mà bá mi rí ọmọ mi jàlòlò ♫,0,yoruba "Àjọ EFCC ti bu ẹnu àtẹ́ lu ìròyìn tó ní pé àjọ náà fi páńpẹ́ ọba mú Adájọ́ Àgbà Nàíjíríà, Walter Onnoghen. Walter Onnoghen bu ẹnu ẹtẹ lu iroyin naa gba ẹnu oluranlọwọ pataki fun un lori ọrọ to jẹ mọ eto iroyin, Arakunrin Awassam Bassey, ti o si pe e ni iroyin ẹlẹjẹ. Minisita tẹlẹri fun ọrọ irina ofurufu, Oloye Femi-Fani Kayode lo kọkọ gbe iroyin ẹlẹjẹ naa jade pe Ajọ EFCC ti yabo ile Adajọ Agba Walter Onnoghen to wa ni Abuja to jẹ olu ilu orilẹede Naijiria. Bakan naa saaju ni ajọ EFCC ti fi atẹjade si ita wi pe irọ lasan ni iroyin wi pe awọn fi panpẹ ọba mu Adajọ Agba, Walter Onnoghen. Oduduwa Alphabet: òmìnira èdè ti dé fún Port Novo báyìí",0,yoruba 'Gbogbo èèyàn 43 tó súnmọ́ ẹni tó kó Monkey Pox wọ Kwara láti rí',0,yoruba "Gẹgẹ bi awọn alasẹ ijọ Synagogue Church of All Nations (SCOAN) se sọ lasiko ti wọn n kede iku oludasilẹ ijọ naa, Wolii TB Joshua, bẹẹ ni ọrọ iku rẹ ri. Ijọ naa lo kede ni owurọ ọjọ Aiku pe Ọlọrun kii se nnkan, ko ma kọkọ fi han awọn wolii rẹ saaju. Bakan naa ni ọrọ ri pẹlu Wolii kan, to ti kọkọ sọ asọtẹlẹ ni osu kan sẹyin pe Ọlarun ti setan lati mu Wolii Temitope Balogun Joshua lọ sile ayeraye. Ninu fidio kan to gba awọn oju opo ayelujara kan, ni ojisẹ Ọlọrun kan Apostle M.E Paul ti n sasọtẹlẹ pe oun ri awọn angẹli, ti wọn wa gbe wolii TB Joshua lọ kuro laye. ""Ọlọrun fi iran igba ikẹyin kan han mi, ẹ tẹti si mi, mo duro silẹ, a si gbe mi lọ si ọrun, ferese ọrun si silẹ fun mi, mo si duro lati boju wo isalẹ ilẹ nile aye. Mo ri awọn angẹli mẹfa ti a ran lati ọrun wa sile aye pe ki wọn lọ gbe wolii Joshua wa, ohun ti mo ri ni mo n sọ. Awọn angẹli mẹta mu dani ni ọwọ ọtun ati mẹta ni ọwọ osi, ti wọn gbe wolii TB Joshua soke tente, to si mu ife ẹyẹ kan dani."" Wolii Paul ni oun wo ibi ti awọn wolii naa duro si, ti wọn si ya si apa ọtun, oun naa ba woju wo apa ọtun, amọ oun ko ri oju ẹni to joko sori itẹ. Bakan naa ni Apostle M.E Paul ni oun gbọ ohun Ọlọrun to n sọ fawọn angẹli naa pe ki wọn gba ife ẹyẹ naa lọwọ Wolii Joshua, ki wọn si mu wa fun oun. Bakan naa lo ni ki wọn mu wolii naa lọ sibi to yẹ fun. ""Lọgan ni mo ri awọn agba angẹli to tun ju awọn ti isaaju lọ, ti wọn n duro sẹba itẹ Ọlọrun, wsn wa gba ife ẹyẹ naa lọwọ wolii TB Joshua, ti wọn si gbe lọ siwaju itẹ Ọlọrun. O ni Oluwa ni ki awọn angẹli yii si gbe wolii si ibi to yẹ ko wa nitori o ti pari ire ije rẹ nile aye.",0,yoruba "Ṣugbọn, ọjọ kẹsan-an, oṣu Kọkanla, ni ireti wa pe ajọ naa yoo kede erongba rẹ. Ọpọ ninu awọn aṣoju orilẹ-ede ninu ajọ naa, to parapọ mọ awọn ọmọ igbimọ lati yan Ọga Agba tuntun, lo fọwọ si iyansipo Okonjo-Iweala. Orilẹ-ede America nikan ni aṣoju ti ko faramọ iyansipo rẹ nibi ipade to waye l'Ọjọru. Kété tí wọ́n bá ti báa yín sùn tàn torí pé ẹ tóbi, ẹ gbà pé ìfẹ́ yẹn ti parí - Auntie Remi Ọlọ́yàn ńlá Kini idi ti ilẹ America ko fi ṣe atilẹyin fun? Gẹgẹ bi Akọroyin BBC lori eto ọrọ aje, Andrew Walker, ṣe ṣalaye, oludije fun ipo naa lati orilẹ-ede South Korea, ni America faramọ, nitori ""iriri to ni nipa okoowo, ati ipá lati ṣe amojuto daadaa"". Wọn ko sọ idi ti wọn fi tako Okonjo-Iweala. Ṣugbọn, o di igba ti igbesẹ to kẹhin ba waye, ki ijiroro to o tan. Nibo ni nkan yoo yọri si? Bi ọrọ naa ṣe n lọ, lootọ ni Okonjo-Iweala, ni ibo to pọju, amọ iyansipo rẹ ko ti i fi ẹsẹ mulẹ. Ijiroro ṣi n lọ lọwọ lori boya ajọ WTO faramọ ẹni to ni ibo to pọju lọ. Àwọn obìnrin mánigbàgbé sáà ìjọba tiwantiwa yìí Ọwọ́jà coronavirus yóò ṣì wà pẹ̀lú àgbáyé fún ìgbà pípẹ́- Ngozi Okonjo-Iweala Wo imọran Fọlọrunṣọ Alakija fun awọn ọdọ adulawọ Ọkan lara awọn akọroyin lati Naijiria to ni anfaani lati mojuto eto idibo naa, Oluwamayowa Tijani, sọ fun BBC Pidgin pe ""iṣoro to wa nibẹ ni pe orilẹ-ede America ko faramọ Okonjo-Iweala"". ""Nkan ti orilẹ-ede America si le ṣe lati gbe erongba wọn lẹyin, ni lati wa awọn orilẹ-ede mii ti yoo darapọ mọ wọn lati tako o."" Ajọ̀ WTO lo ma n mojuto ijiroro ati adehun okoowo laarin awọn orilẹ-ede. Nibẹ si ni awọn orilẹ-ede ti le yanju aawọ to ba waye laarin wọn nitori okoowo. Okonjo, to ti fi igba kan jẹ minisita fun eto inawo ni Naijiria, ni obinrin akọkọ to de ipo naa lati ọdun mẹẹdọgbọn ti wọn ti da ajọ WTO silẹ. Adetoun Ogunṣẹyẹ: ìrìnàjò ẹ̀kọ́ mi títí dé òkè kò rọrùn rárá Oun naa si tun ni ọmọ ilẹ Africa akọkọ to de ipo naa. Apapọ ibo mẹrinlelọgọrun ni oun nikan ni, ninu ibo mẹrinlelọgọjọ ti awọn aṣoju di. Eyi yoo mu ko fi ẹyin minisita fun okoowo l'orilẹ-ede South Korea, Yoo Myung- he, ti wọn jọ de ipele to kẹhin. Bi ipinnu Ngozi Okonjo-Iweala lati di Oludari ajọ WTO ṣe n jọ ọ bọ̀ diẹdiẹ Ipinnu Minisita feto ọrọ aje Naijiria tẹlẹ Ngozi Okonjo Iweala lati di ipo adari ajọ idokowo lagbaye WTO mu n sunmọ mimu ṣẹ bọ diẹ diẹ. Eyi ko sẹyin bi o ti ṣeeṣe ki wọn kede orukọ rẹ lojobọ lara awọn meji to tẹsiwaju de abala ìkẹyìn eto iyansipo tó n lọ lọwọ. Ni bi nkan ti ṣe ri yi, oun ati ọmọ orileede South Korea Yoo Myung- he ni wọn yoo fi orukọ wọn ṣọwọ ninu awọn marun un to ṣẹku tẹlẹ. Obinrin ni awọn mejeeji. Bi o ba fi le jawe olubori yoo jẹ obinrin akọkọ lati Afrika ti yoo di ipo yi mu. Àwọn onwoye si n sọ pe yiyan ọmọ Afrika si ipo yi yoo mu idagbasoke ba karakata nilẹ naa eyi ti o daduro si ida meji si mẹta idokowo lagbaye. Bakan naa ni adari ajọ naa tuntun ti wọn ba yan yoo ni lati pẹtu saawọ idokowo laarin Amerika ati China. Ṣaaju ni aarẹ Trump ti kọdi iyansipo awọn adajọ si igbimọ ipẹtusaawọ ajọ naa. Eyi si n ṣakoba fun ajọ naa nipa ṣiṣe iṣẹ rẹ lẹkunrẹrẹ. Loṣu to n bọ ni wọn yoo kede ẹni ba pegede fi ipo olori WTO. Ondo Elections 2020: Ọgọ́rùn-ún ọdún tí a máa lò lórí oyè l'Ondo, ẹ ó rí àrà - Ojon YPP Ta ni Ngozi Okonjo-Iweala to dupo olori ajọ okowo agbaye WTO? Ọjọgbọn Ngozi Okonjo-Iweala jẹ minisita ijọba meji lorilẹede Naijiria-2003 si 2006 labẹ aarẹ Oluṣẹgun Ọbasanjọ, 2011 si 2015 labẹ iṣejọba aarẹ Goddluck Jonathan. Banki agbaye ni Ọjọgbọn Ngozi Okonjo-Iweala ti n ṣiṣẹ ki aarẹ Oluṣẹgun Ọbasanjọ to pe e wa sile wa ṣe minisita fun eto iṣuna lorilẹede Naijiriaoun ni obinrin akskọ ti yoo ṣe minisita fun eto iṣuna ati minisita fun ọrọ ilẹ okeere lorilẹede Naijiria. Pupọ ọmọ orilede Naijiria ni ko ni gbagbe minisita 'alaṣọ ankara' yii pẹlu gele 'ipakọ o gbọ ṣuti' rẹ Ọkan lara awọn eekan to lagbara labẹ iṣejọba aarẹ Ọbasanjọ laarin ọdun 2003 si 2006 ni Okonjo-Iweala, o si ko ipa ribiribi ninu bi awọn igbimọ orilẹede agba kan lagbaye ṣe wọgile gbese biliọnu mejidinlogun dọla, $18bn ti orilẹede Naijiria jẹ ṣaaju igba naa. Pupọ ọmọ orilede Naijiria ni ko ni gbagbe minisita 'alaṣọ ankara' yii pẹlu gele 'ipakọ o gbọ ṣuti' rẹ.",0,yoruba àìmọ́. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba RT @user: @user. E wo nise ni mo nla gun be eni ti won ribomi. Ko si ina. Jenareto gan o wulo mo. Ilu ti dojuru. Oba Ed ...,0,yoruba wúlò. ti o nuni ti o nuni ti o nuni ti o nuni ti o tẹ.,0,yoruba Ko ma ragba fun English. #yoruba legit❤️ https://t.co/lYI7t4SIPy,0,yoruba dara. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó ṣe pàtàkì.,0,yoruba ẹni tí a ó fẹ́ nílé ẹ ń jìnà,0,yoruba "àkokò, Ọba ri Nitori eyi, ara eni lo ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Bákanáà, ẹ̀wà àti ọ̀pọ̀lọpọ̀ epo pupa ni oúnjẹ àwọn èjìrẹ́; ìbejì tí à ń sè lọ́dọọdún. #Epopupa #Ibeji #Twins #Yoruba #Ewa #Beans",0,yoruba da ti o nuni ti o nuni ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún gbogbo àwọn aráyé lẹ́.,0,yoruba a ní ìjọba wa mọ̀ọ́mọ̀ má pèsè iná aláyòlé fún wa ni o,0,yoruba "Isẹ Oluwa, awamaridi ni nitori ọna rẹ, ko si ẹni to ye tabi ẹni to mọ, bo si se wu Oluwa lo n se ọla. Nibi ti awọn eeyan kan ti n fi ojoojumọ sunkun si Ọlọrun lọrun fun ẹbun ọmọ, ni Ọba Oke ti fi ibarun ta idile Idowu ati Funmilayo Oluwadara lọrẹ. Awọn tọkọ-taya yii lo ti kọkọ bi ọmọ marun tẹlẹ, ki oore ibarun tun to wọle de, ti iya wọn si bi wọn wọọrọwọ lai se isẹ abẹ. Nigba ti tọkọtaya Oluwadara n ba BBC Yoruba sọrọ nilu Ogbomoso, wọn ni ibẹta ni dokita kọkọ ni oun yoo bi, ki ibarun to wa, ọkunrin kan ati obinrin mẹrin. Ni ọjọ karun tawọn ọms naa dele aye la gbọ pe ọkunrin kan soso laarin awọn ibarun naa jade laye. Tọkọ-taya naa ti wọn jẹ alagbaro, ni ko ti wa ri owo ile iwosan san lati maa lọ sile, bi o tilk jẹ pe dokita ti yọnda wọn. Wọn wa n bẹbẹ fun iranwọ owo lọdọ awọn ẹlẹyinju aanu, lati sanwo ile iwosan ati fun itọju awọn ọmọ mẹrin to ku pẹlu awọn ẹgbọn wọn nitori ọna abayọ.",0,yoruba óyá ẹ jẹ́ ká pòwe obe ti bale ile kiije awon omo ile le je,0,yoruba gbfi yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "Bíi ẹgbẹ̀rún kan àbọ̀ ènìyàn ni ó ti kú ní Benue láti 2013 Àwọn afurasí darandaran náà ni a gbọ́ pé ó ṣe ikọlù náà sí St. Ignatius Quasi Parish, Ukpor-Mbalom ní bíi aago mẹ́fà àárọ̀ ọjọ́ ìṣẹ́gun nígbà tí àwọn olùjọ́sìn ìjọ náà lọ sí ìjọ́sìn àárọ̀. Terver Akase ti ó jẹ́ agbẹnusọ fún Gomina Samuel Ortom sọ fún BBC Yorùbá pé, awon fadá ti o padanu ẹ̀mi wọn ninu ikolu naa ni Fadá Joseph Gor ati Fadá Felix Tyolaha. Akase so wí pé lẹ́hìn tí àwọn darandaran náà ṣọṣẹ́ tán ní ilé ìjọsìn náà, wọ́n tún sọ iná sí ilé bíi àádọ́ta ní ìlú náà, kí wọn tó sa lọ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Odumakin sọrọ lori Fulani darandaran Ẹgbẹ̀rún kan ààbọ̀ ènìyàn ni ó ti kú ní Benue láti 2013 Oṣù kejì ọdún yìí ni kọmíṣọ́nnà fún ìbánisọ̀rọ̀ àti ìlanilọ́yẹ ní Benue, Lawrence Onoja, sọ wí pé bíì ẹgbẹ̀rún kan àbọ̀ ènìyàn ni ó ti kú ní Benue láti 2013 nínú àkọlù àwọn afurasí darandaran agbébọn, tí ogunlọ́gọ̀ sì pàdánù dúkìá, ohun ọ̀gbìn àti ilé wọn. E ó rántí wípé ní oṣù kínní ọdún yìí ni ìjọba ìpínlẹ̀ Benue sin òkú métàléláàdọrin tí àwọn agbébọn pa.",0,yoruba Ẹdìẹ tí ò kú ṣì máa jàgbàdo. #Owe #Yoruba,0,yoruba "asin. Nitori eyi, ara eni lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba "Gbogbo nǹkan tó jẹ́ dúdú ò dára, wọ́n ti gbin ìgbìnkugbìn síwa lọ́kàn. | #TransAtlanticSlaveTrade #OwoEru",0,yoruba "Fidio kan ṣafihan ọkunrin naa to jẹ ẹni ọdun mọkandinlọgbọn nibi to ti n sare laarin igboro Notting Hill, to wa ni iha Iwọ oorun London. Ṣaaju ni awọn eeyan adugbo ti kọkọ pe ileeṣẹ ọlọpaa lẹyin ti wọn ri odidi gende ọhun nihoho, ni kete to foju ganni ọlọpaa tan lo ba ẹsẹ rẹ sọrọ. Ọkọ mi bá àwọn ọmọ wa sọ̀rọ̀ lágo kan kó tó wọ bàálù tó já, àmọ háà! - Ìyàwó Olasunkanmi Olawunmi Ẹnikan ti iṣẹlẹ naa ṣoju rẹ, Pedro Lula, sọ fun awọn akọroyin pe, idi iṣẹ ni oun wa ti oun fi ri ọkunrin naa ti awọn ọlọpaa mẹta n le laarin titi, ti oun si fi ẹrọ ibaraẹnisọrọ oun ka iṣẹlẹ naa silẹ. Fidio ọhun ṣafihan bi ọkunrin ọhun ṣe n salọ, ti ọlọpaa meji n le, ki ọlọpaa kẹta to darapọ mọ wọn. Lẹyin o rẹyin, awọn ọlọpaa le ọkunrin naa ba, ti wọn si fi orukọ rẹ lede gẹgẹ bii Ross Springham. Lẹyin naa ni wọn gbe lọ sile ẹjọ to wa ni Westmisnter, nibi to ti kawọ pọn rojọ niwaju adajọ, to si sọ pe oun gba pe oun jẹbi ẹsun rinrin nita gbangba ni ihoho. Bo tilẹ jẹ pe oṣu to n bo ni wọn yoo ṣe idajọ rẹ, adajọ ti ni ko lọ sinmi latimọle fun igba diẹ titi ti wọn yoo fi ṣe idajọ rẹ. 'Tí mi ò bá rí ògùn rà fún ọmọ mi, á máa gé ara rẹ̀ jẹ tí ẹ̀jẹ̀ yóò máa ṣàn' Ọlọ́pàá Ogun ké pe ẹni tó ni Pavillion Hotel láti wá ṣàlàyé ìdí tí kámẹ́rà fi wà nínú yàrá Nigba to n sọrọ lori iṣẹlẹ ọhun, agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ni London sọ pe ootọ ni iwadii wọn fi han pe ọkunrin naa n rin laarin ilu ni ihoho. O fi kun pe nnkan biii aago mẹjọ aarọ ni wọn gba ipe pajawiri nipa ọkunrin ọhun, nigba ti wọn de agbegbe naa, wọn ba bẹẹ lootọ ki wọn to fi ṣikun ofin mu.",0,yoruba "Ó gbọdọ̀ ṣe é jó sí , síbẹ̀ ó ní láti dùn ún ní etí àwọn ènìyàn tí yóò “ mú wọn gbàgbé ara """""""" ní orí ìtàgé , pẹ̀lú ọ̀rọ̀ orin tí yóò mú ayọ̀ jáde , èyí tí a mọ Ijó ìta - gbangba mọ́ .",0,yoruba gbe ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba "Inu ẹni kii dun, ka pa mọra ni ọrọ awọn ololufẹ Olalekan Agbeleshebioba, ti sps eeyan mọ si Leycon, to gbegba oroke ninu asekagba idije BB Naija fun tọdun 2020. Idi ni pe Senator to n soju ẹkun idibo Ariwa Adamawa, Elisha Ishaku Abbo ti kede pe oun fẹ se apejẹ ati ayẹyẹ idawọ idunnu pẹlu Leycon to jawe olubori naa. Ninu fidio kan to gba ori ayelujara kan bayii, ni Sẹnatọ Abbo ti kede pe, nitori oun se agbatẹru fun Leycon, o di dandan ko jawe olubori ninu idije naa. ""Gbogbo ẹyin ololufẹ Leycon, ẹ sunmọ lonii bi ka dijọ se ariya. Mo ti sọ fun yin pe Lecon n gbe owo ile BB Naija bọ wa sile, o si ti de bayii. Nitori naa, ẹyin ti Naira Marley, nibo lẹ wa? O ya, a n lọ silu Eko lọ se ariya, Naira Marley, o ya sunmọ ibi, jẹ ka ls se ariya fun Lekan ooooo."" Bẹẹ ba si gbagbe, Sẹnatọ Abbo yii ni ẹnu n kun lati ọdun to kọja lori ẹsun pe o lu obinrin kan ninu ile itaja, ti fidio naa si gba ori ayelujara kan. Amọ ọjọ Aje ni iroyin gbalẹ pe, ile ẹjọ giga ilu Abuja ti ni ki Sẹnatọ Abbo yii lọ san miliọnu lọna aadọta naira fun obinrin naa, ti Abbo fiya jẹ. Lẹyin wakati mẹrinlelogun ti idajs naa waye, ni akọtun fidio miran tun lu sori ayelujara ninu eyi ti Sẹnatọ Elisha Abbo ti n kesi Naira Marley pe kawọn lọ silu Eko, ls se ariya fun Lekan. Ibeere ti ọpọ eeyan wa n beere ni pe, ki lo pa Sẹnatọ Elisha Abbo, Naira Marley ati Lekan pọ? Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe, ile ẹjọ giga ilu Abuja, to wa ni Maitama, ti dajọ pe ki sẹnetọ to n ṣoju ẹkun idibo Ariwa Adamawa, Elisha Abbo, san aadọta miliọnu Naira, gẹgẹ bi owo itanran, fun oṣiṣẹ ile itaja kan to fi iya jẹ. Oṣu karun-un, ọdun 2019 ni fidio kan jade sori ayelujra, to si ṣafihan bi Sẹnetọ Abbo ṣe n ko igbaju, igbamu fun obinrin kan ni ṣọọbu ti wọn ti n ta awọn eroja ibalopọ nilu Abuja. Ọpọlọpọ ọmọ Naijiria lo koro oju si ihuwasi sẹnetọ naa. Eyi mu ki ọrọ naa de ileeṣẹ ọlọpaa, ti wọn si kọkọ gbe e lọ si ile ẹjọ majisireti kan ni agbegbe Zuba, nilu abuja. Ṣugbọn, adajọ ile ẹjọ naa, Abdullahi Ilelah, wọgile ẹjọ naa, lẹyin ti Abbo kọwe pe oun ko ni ẹjọ kankan latiu jẹ. Arabinrin naa, Osinibibra Warmate, pẹlu iranlọwọ awọn agbẹjọro rẹ, pe ẹjọ miran si ile ẹjọ giga ilu abuja, ti wọn si fi ẹsun kan Sẹnetọ Abbo pe o tẹ ẹtọ rẹ mọlẹ. Onidajọ ile ẹjọ giga naa, Samira Bature si ti dajọ pe ki Sẹnets Abbo san miliọnu lọna aadọta Naira fun arabinrin Warnate, lati fi tu u ninu.",0,yoruba COVID - 19 ṣe àgbéǹde ìṣẹ̀lẹ̀ - àtẹ̀yìnwá tó burú jáì nípa ìdánwò egbògi ní Ilẹ̀ - Adúláwọ̀,0,yoruba gbe ti o nuni ti o nuni ti o nuni ti o nuni ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó wáyé..,0,yoruba wáyé. ti Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa iṣẹ́: ti o dara.,0,yoruba "A kú ìrọ́jú l‘Osun, ìyà ti pọ̀jú, ojojúmọ́ ní mò ń sunkún – Adeleke",0,yoruba "wáyé. ti Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "ài: ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba World Toilet Day: Onímọ̀ kan ní ìpèsè ilé ìgbọ̀nsẹ̀ nìkan kò lè tàn ipenija yí,0,yoruba In Yorùbá dúkìá is property (dúkìá wa ò ni jó'ná - our property will not get burnt) #Yobamoodua #Yorubaword #LearnYoruba,0,yoruba àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ài: ti o ṣe pataki.,0,yoruba olóótọ fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde sí ara ilẹ̀.,0,yoruba "fi, Nitori eyi, ara eni lo ni iwa rere lojiji.",0,yoruba Pánẹ́ẹ̀lì Igun Òsì Tí A Fẹ̀,0,yoruba RT @user: @user asiri ti tu niyen ooo (afefe ti fe a ti ri furo adiye),0,yoruba ️️ ikira fun egbe agbabolu ti won ma fi igba gbaga pelu egbe agbabolu ni ere papa ni ilu london,0,yoruba Òyó. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..,0,yoruba "Gomina Gboyega Oyetọla ti ke sawọn oludije mejeeji ti wọn jọ dije fun aṣia idibo gomina nibi eto idibo abẹnu to waye lopin ọsẹ to kọja. Gomina Oyetọla pe ipe yii ninu ipe akọkọ to sọ lẹyin ti wọn kede rẹ gẹgẹ bi olubori idibo abẹnu naa. Moshood Adeoti pẹlu Lasun Yusuf lo baa dije fun ipo naa. Ibẹru bojo ti gbalẹ nipinlẹ Osun ṣaaju eto isibo abẹnu gomina ẹgbẹ oṣelu APC ọjọ Abamẹta. Oludije mẹta ni yoo kopa ninu ibo abẹnu yii lati mọ ẹni ti yoo ṣoju APC ninu idibo gomina ọjọ kẹrindinlogun oṣu keje ọdun 2022 yii. Awọn oludije naa ni gomina ipinlẹ Osun lọwọ yii, Gboyega Oyetola, igbakeji adari ile aṣojuiṣofin l'Abuja tẹlẹ ri, Lasun Yusuff. Oludije kẹta ti yoo kopa ninu ibo abẹnu ọhun ni Alhaji Moshood Adeoti to jẹ akọwe ijọba ipinlẹ Osun tẹlẹ. Eto idibo gbangbalaṣanta ni awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC faramọ fun idibo naa. Ki lo fa ibẹru-bojo ṣaaju eto ibo abẹnu gomina ẹgbẹ APC l'Osun? Laipẹ yii ni awọn ọmọlẹyin gomina ipinlẹ Osun tẹlẹ, Rauf Aregbesola atawọn ọmọlẹyin gomina Oyetola kọlu ara wọn l'Osun. Koda awọn kan ti fẹsun kan awọn ẹṣọ alaabo wi pe wọn n ṣegbe lẹyin ẹnikan pẹlu rogbodiyan to n ṣẹlẹ ninu ẹgbẹ APC nipinlẹ Osun. Awọn ọmọlẹyin Aregbesola kan ti ẹ fẹsun kan kọmiṣọnna ọlọpaa Osun pe o n ṣegbe lẹyin gomina ipinlẹ Osun. Oludamọran fun minisita ọrọ abẹnu, Aregbesola, lori ọrọ iroyin, Sola Fasure, sọ pe awọn janduku kan ṣe ikọlu si ọkọ Aregbe lọjọ Aje lẹyin ṣe ipolongo fun oludije rẹ. Ṣugbọn kọmiṣọnna eto iroyin naa, Funke Egbemode, sọ pe awọn eeyan kan ti ya wọ ilu ti wọn si n wọ aṣọ ayederu ajọ abo ara ẹni ni abo ilu, NSCDC ati awọn to n sọ ọgba ẹwọn. Aregbesola sọrọ lori aawọ to n lọ lọwọ ninu ẹgbẹ APC l'Osun Aregbesola ṣalaye pe adari awọn oṣiṣẹ nipinlẹ Osun ni Oyetola nigba ti oun fi jẹ gomina ipinlẹ Osun. ''Mo fi gbogbo agbara mi ṣiṣẹ lati ri pe Oyetola di gomina ipinlẹ Osun. Ṣugbọn o jẹ iyalẹnu fun mi pe lati igba ti Oyetola ti di gomina ni o ti wa ṣọ mi lọwọ ṣọ mi lẹsẹ. Ọdun meji ni mo fi bẹ Oyetola lati dẹkun aawọ to n ṣẹlẹ lọwọ yii ninu ẹgbẹ APC, amọ ko gbọ si mi lẹnu,'' Aregbesola lo sọ bẹẹ. Adeoti ni oludije ti Aregbesola n ti lẹyin fun ipo gomina ninu ibo abẹnu ẹgbẹ APC. Ẹwẹ, ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Osun ti kede pe gbogbo eto lo ti to lati ri pe eto abo to muna doko wa fun eto idibo abẹnu naa lọjọ Abamẹta.",0,yoruba Ìfòfinlíle mú àtakò,0,yoruba Ọdún ti ń sẹ̀dẹ yii ni àwọn ọmọ abinibi a ń ṣaṣa.,0,yoruba "lòdì Ìjẹ̀. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "àkokò, Baàlè ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn.",0,yoruba "Ọkọ ofurufu An-26- bii iru eleyi lo jẹ onipele meji fun kiko awọn ọmọogun ati awọn araalu Ileesẹ ologun Orilẹede Russia lo fidi isẹlẹ yii mulẹ. Ileesẹ iroyin Russia to gbẹnu sọ fun ileesẹ oloogun ilẹ naa, kede pe ọkọ ofurufu An-26 jabọ nigba to n balẹ ni papako awọn ọmọogun ofurufu to wa ni Latakia, lorilẹede Syria. Iroyin naa wipe awọn ọmọogun mọ̀kandinlogoji lo padanu ẹmi wọn, eyi to yatọ si iroyin akọkọ to wipe eniyan mejilelọgbọn lo padanu ẹmi wọn. Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: O fikun pe kii se pe wọn yinbọn mọ ọkọ ofurufu naa, ati wipe akọsilẹ to wa nilẹ saaju isẹlẹ naa fihan wipe o seese ko jẹ wipe baalu naa ni iyọnu lo sokunfa ijamba naa. Ileesẹ ologun orilẹede Russia naa fikun wipe, iwadi si isẹlẹ naa ti bẹrẹ.",0,yoruba "Abbo tọrọ aforojin yii pẹlu ikaanu nla, lasiko ipade akọroyin to se ni olu ile ẹgbẹ PDP to wa nilu Abuja. Asofin ẹgbẹ PDP naa, to tọrọ aforijin pẹlu lọwọ ẹgbẹ oselu rẹ, awọn mọlẹbi, ọrẹ tun mẹnuba pe, iwa bayii se ajeji si oun lati ẹyin wa, ti oun si kabamọ fun iwa toun hu yii, lainaani ohun to bi oun ninu lati se bẹẹ. Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: O wa rawọ ẹbẹ si tọkunrin-tobinrin ọmọ orilẹede yii lati wa aaye ninu ọkan wọn fi fori jin oun nitori eniyan lo n dẹsẹ, Ọlọrun si lo maa n fori jin ni. Abbo, to ni ọmọ kii mọ ẹkọ jẹ ko ma ra lọwọ, tun tọrọ aforijin lọwọ ijọ Ọlọrun lagbaye lori iwa aidaa ti oun hu yii, nitori o ni gẹgẹ bii asoju Kristi, iru iwa yii ko tọ si oun. CAN: Samson ni ọrọ awọn ajinigbe ti gba àpérò ní Naijiria Bakan naa lo fikun pe itọni ti oun gba ninu ile ati ijọ Ọlọrun ko fọwọsi iru iwa yii, nitori idi eyi, oun tọrọ idarijin niwaju Ọlọrun ati awọn eeyan ti iwa oun yii ti jẹ ẹdun ọkan fun.",0,yoruba RT @user: Akure Oloyemekun! RT @user: Ọmọ #Ondo dà? Ibi ìrìn-àjò ìgbafẹ́ t'ó ń kó èrò wọ #Ondo #WTD @user,0,yoruba o ò tíì dáhùn ìbéèrè ọ̀hún tán ó ku ọ̀kan o iṣẹ́ẹ kí lọ́ ńṣe,0,yoruba "Ni bayii awọn obi awọn ọmọ bi ọgọrun ti wọn sọnu ni ile-iwe abule Dapchi ti n sunkun nigba ti awọn alaṣe n sọ awọn ọrọ ti wọn tako arawọn nipa ipọ ti awọn akẹkọbirin naa wa. Lẹyin igba ti wọn ji awọn akẹkọbirin Chibok gbe, ijọba dakẹ lai sọ nkankan. Ṣugbọn ileeṣẹ ologun Naijiria kede wipe oun ti gba awọn ọmọ ile-iwe naa la. Lẹyin naa ni ileeṣẹ na ba sọ wipe ọrọ naa ko ri bẹ mọ. L'akọkọ ijọba Naijiria ti ọdun 2014 ko mọ bi ọrọ naa ti tobi to saaju ki wọn o to ma polongo BringBackOurGirls. L'asiko yi gan ọrọ naa kun fun iruju nibi ti awọn alaṣẹ ti kọkọ daba wipe awọn ti gba awọn ọmọ naa silẹ ki wọn o to wa tọrọ aforijin lẹyin ọrẹyin wipe ọrọ na ko ri bẹ. Titi di isin yii wọn ko ti fi idi ọrọ mulẹ nipa ibi ti awọn akẹkọbirin naa wa ati ounka wọn. Awọn kan n sọ wipe awọn akẹkọbirin naa to adọta nigba ti awọn kan si wipe awọn ọmọ ile iwe naa to ọgorun. Har yanzu akwai ragowar 'yan matan Chibok kusan 100 da ba a gano ba Ko si ti si ẹri kan to muna doko to le fi han wipe awọn ikọ Boko Haram ni wọn gbe awọn ọmọ ile iwe naa lọ. Ṣugbọn nkan ti ko ni tabi-tabi ni ibanujẹ ọkan ati ainidaniloju awọn obi awọn akẹkọbirin naa. Obirin kan to jẹ ọkan lara awọn obi awọn ọmọ naa sọ wipe ""Ti mọ ba ranti wipe ki se l'ọrun lo wa ati wipe n ko mo iru ipo to wa, ti mo ba ronu bi wọn ti maa s'afihan aworan awọn ti wọn ji gbe, ma kan maa sukun ni lai dakẹ. Ki wọn gbe oku rẹ wa ki wọn si gbe sin o ya ju kin ma le ri lọ."" Ọkan lara awọn obi awọn ọmọ naa, Adamu Muhammed, sọ wipe ""Lotitọ ti wọn ba se iru nkan bai si yan inu rẹ ko ni dun, sugbọ gẹgẹ bi Musulumi, gbogbo nkan to ba sẹlẹ si mi, maa kan ti si Ọlọrun mi ni. ""Ṣugbọn nkan ti wọn se fun wa ko dara rara. Ọmọ ọdun mẹdogun l'ọmọ mi. Ipele kinni lowa ni ile-ẹkọ girama agba (SS1). Ẹmi ko mọ ibi ti ọmọ mi wa. Awa (ti ako mọ ibi awọn ọmọ wa wa) pọ gidigan. ""O damiloju wipe ijọba Buhari ni wọn fẹ fi ijinigbe yii koba. Bi kii ba se bẹ, eleyi jẹ nkan to n runi loju ni."" Lootọ awọn obi awọn ọmọ Dapchi wọn ko ni sọ ireti nu sugbọn awọn kan lara awọn obi awọn akẹkọbirin Chibok sin reti awọn ọmọ wọn lẹyin ọdun mẹrin ti wọn ti ji wọn gbe. Nkan ti awọn onwoye n wi ni pe ọwọ yẹpẹrẹ ti wọn fi mu ọrọ ibi ti awọn akẹkọ naa wa lo fa ti ko fi ti ni ojutu bayii. Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹ si:",0,yoruba "Ajọ ti o ri si ere boolu ni Naijiria ko dunnu rara si bi iku ojiji ti n pa awọn ọjẹ wẹwẹ agbaboolu lorilẹede yii. Ninu ọrọ rẹ, akọwe agba fun ere boolu lorilẹede yii, Dokita Mohammed Sanusi banujẹ lori iku Issac Promise. Issac Promise ni adari ojugba rẹ nigba idije awọn ọjẹwẹwẹ ti ọjọ ori wọn ko ju Ogun ọdun ati mẹtalelogun lọ. Akọwe agba lẹka ere bọọlu naa ni pe aipẹ yii ni ọkọ ayọkẹlẹ kan pa meji lara awọn agbabọọlu fun Ọlọpaa meji. Awọn meji naa ni wọn ku lairo tẹlẹ ni ilu Uyo, Olu Ilu Akwa Ibom ni ọjọ meji sẹyin, ki ti Issac Promise to tun ṣẹlẹ. Mohammed Samuel ni ọsẹ ibanujẹ ni ọsẹ naa jẹ fun Ajọ naa. O ṣapejuwe Isaac Promise gẹgẹ bi ẹni ti o ni iwa tutu ti o si mura siṣẹ. O tẹsiwaju pe titi di asiko ti iroyin yii jade, wọn ko i tii mọ orisun iku rẹ. O wa ni manigbagbe ni Promise yoo jẹ fun gbogbo eniyan. Promise ni o jẹ adari ikọ ọmọ Naijiria ninu idije ti ọjẹwẹwẹ ilẹ Afrika ni ọdun 2005 ni Orilẹ ede Benin. Bakan naa ni o tun kopa ninu ere idije ifese wọn sẹ ti FIFA ti ọjọ ori wọ ko ju Ogun kọ Promise ni o tun je adari ninu idije ti awọn ọjẹwẹwẹ ti ọjọ ori wọn ko ju mẹtalelogun lọ ni Beijing 2008. Ninu atẹjade ti ẹgbẹ agbaboolu rẹ Bold FC fi lede wọn ni Promise jade laye lẹyin ti o ti lo Ookanlelọgbọn lori eepẹ.",0,yoruba àkún rẹ́ ni ó di àkúré ẹ̀bá ọ̀dàn ni ó di ìbàdàn oko òdú ni ó di ìkòròdú ni ó di òndó,0,yoruba ìlú tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa aráyé: ti o ní wúlò.,0,yoruba Kà síwájú sí i : Àwọn akọrin lóbìnrin Ìlà - Oòrùn Ilẹ̀ Adúláwọ̀ kọrin tako àìfààyè gba obìnrin àwọn ọkùnrin .,0,yoruba ojú onà. ti Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tobi jù lọ ní Afríkà gúúsù.,0,yoruba RT @user: Ojú á tún'ra rí; òwe àkàlà. #EsinOro🐎 #Yoruba,0,yoruba "O to gee Ajọ Amnesty international ṣalaye pe ọna ati fi ẹtọ Ṣoworẹ dun un ni njọba n yẹ. Amnesty international ni awọn ẹsun ti ko lẹsẹ n lẹ ti wọn fi kan Ṣoworẹ jẹ ara ọgbọn ti ijọba apapọ n da lati fi ẹtọ rẹ dun un. Bakan naa ni wọn ni bi ijọba ṣe tii sinu ahamọ labẹ ikawọ ofin to de iwa igbesunmọmi nitori pe o ṣe amulo ẹtọ rẹ labẹ iwe ofin jẹ ara aṣilo ọna lati fi ofin di ẹnu awọn to ba n tako ijọba ni. Wọn wa ke sawọn alaṣẹ lorilẹ-ede Naijiria, 'lati bọwọ fun ẹtọ ọmọniyan ki wọn maa si lo awọn ofin naa lati tẹ oju ẹto Ṣoworẹ mọlẹ."" Ijọba apapọ ṣi iwe ẹsun fun Ọmọyẹle Ṣoworẹ ti wsn si fi ẹsun kan an pe o gbimọran ati gbimọpọ idtẹ gba ijọba nipa agbekalẹ eto iwọde Revolution now ni ọjọ karun oṣu kẹsan ọdun 2019 lati ys aarẹ orilẹ€de Naijiria nipo. Agbẹjọro agba lorilẹ-ede Naijiria to tun jẹ minisita fun eto idajọ, Abubakar Malami, SAN lo ṣe eto ifisun naa. Kini awọn eniyan Naijiria n sọ lori ọrọ yii? Ero awọn ọmọ Naijiria ṣotọọtọ lori bi ijọba Mohammadu Buhari ṣe ti Omoyẹle Soworẹ mọle lati ọkan le ni adọta ọjọ sẹyin. Awọn kan n yin Arẹ Buhari pe o fẹ tete pẹka iroko sowore ni, ko too maa gbẹbọ lọwọ Naijiria: Bee naa ni awọn miran ni ori bibẹ kọ ni oogun ori fifọ Sowore lasiko yii: Ọpọ ọmọ Naijiria gba pe asiko ti to ki ijọba tu gbogbo awọn to wa ni ahamọ silẹ nitori ominira lati sọrọ to yẹ ko wa ni Naijiria. O to gee Loju awọn miran bii Kayode Ogundamisi, ẹsun meje ti ijọba fi kan Omoyele to dije dupo aarẹ ninu idibo Naijiria to kọja ti pọju: Nigba ti awọn bii Don Jazzy ni ọna lati di awọn to n sọrọ lodi si aṣiṣe ijọba Buhari lẹnu ni atimọle Sowore jẹ lasiko yii Bẹẹ naa dẹ ni awọn miran gba Sowore nimọran lati san sokoto rẹ ko le daadaa nitori ẹsun ifọtẹgbajọba ti ijọba fi kan an Awọn miran gba pe ohun ti Sowore ṣe ko dara rara: Yollywood: Kò sí ẹni ti òbí mi kò lè sọ̀rọ̀ sí -Sisi Quadri",0,yoruba "Òyó. Nitori eyi, ara eni lo ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba yìí ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò.,0,yoruba "Ninu atẹjade ti agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Rivers, SP Nnamdi Omoni fi sita, o ni bi ago mẹjọ abọ alẹ ni iṣẹlẹ ọhun ṣẹlẹ. O ṣalaye ninu atẹjade naa pe ọkọ Hilux lawọn agbebọn naa fi ṣe iṣẹ laabi ti wọn ṣe lọjọ Ẹti. Awọn ọlọpaa to wa lori afara Choba lawọn agbebọn naa kọkọ kọlu nibi ti wọn ti pa ọlọpaa meji ti wọn si tun dana sun ọkọ ọkan lara awọn ọlọpaa ọhun. Awọn agbebọn naa tun gbera lọ si agọ ọlọpaa to wa ni Rumuji nibi ti wọn tun ti pa ọlọpaa meji mi ti wọn si tun dana sun ọkọ awọn ọlọpaa. Nnamdi sọ ninu atẹjade naa pe awọn agbofinro naa kọju ija sawọn agbebọn ọhun nigba ti wọn de eyi to mi ki meji lara wọn gbẹmi mi. Bakan naa ni wọn tun kọlu agọ ọlọpaa to wa ni Elimgbu, bo tilẹ jẹ pe wọn ba awọn ọlọpaa naa nile. Awọn ọlọpaa kọju ija sawọn janduku agbebọn ọhun, ṣugbọn mẹta ninu awọn ọlọpaa lo ba iṣẹlẹ naa lọ. Awọn agbebọn naa ko ri ọkọ Hilux ti wọn gbe wa pada gbe lọ, ọkọ Sienna ti wọn ji gba lọwọ ẹnikan ni wọn gbe lọ. Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe awọn agbebọn naa fara gbọta yana yana eyi to da apa si wọn lara. Wọn tun gbe Sienna naa silẹ nigba tawọn ọlọpaa ko pada lẹyin wọn, bayii ni wọn ṣe na papa bora pẹlu apa ọta ibọn lara wọn. Ẹwẹ, wọn ti gbe oku awọn ọlọpaa to ṣubu loju ogun lọ si mọsuari, nigbati ọga ọlọpaa ipinlẹ Rivers, Eboka Friday sẹleri pe ileeṣẹ ọlọpaa yoo ṣe awari awọn kọlọnbiti ẹda naa. Ileeṣẹ ọlọpaa wa rọ awọn araalu lati fi to awọn ọlọpaa leti ti wọn ba ri ẹnikẹni pẹlu apa ibọn lara wọn.",0,yoruba "Ẹ kú Ọjọ́-Ọ̀sẹ̀ o gbogbo ọmọ #Oodua tòótọ́, ẹ̀yin ọmọ #Yoruba àtàtà, jákèjádò ilẹ̀-aye. Ṣé àlááfíà ni!",0,yoruba "Oludasilẹ ile ijọsin kan nilu Eko, Wolii Adegboyega Ajani lo woye ọrọ yii lasiko ipade akọroyin kan to ṣe lati sami ayajọ gbigbe ogun tiwa ajẹbanu lagbayee. Ojisẹ Ọlọrun naa fikun pe, awọn elesinjesin gan ti kuna ninu gbigbe ogun tiwa ajẹbanu. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ""Ni gbogbo agbaye, tàwọn eeyan ba gbọ nipa iwa ajẹbanu, owo jiji nikan ni wọn maa n ro si eyi to jẹ asise. O dabi igba ti eeyan n wa ojutu si isoro mẹta amọ ti onitọun gbajumọ ẹyọ kanṣoṣo, to si fi awọn isoro yoku silẹ. Idi ree to fi yẹ ka tete san sokoto wa ko le lati gbogun tiwa ajẹbanu naa. Nigba to n sọrọ lori bi ajẹbanu naa ṣe n fẹju si, Wolii Ajani ni yoo nira diẹ kiwa ajẹbanu to kasẹ nilẹ ni Naijiria. ""Bi awọn obi ṣe n ko owo ilu, naa ni wọn n fi iwa àjẹbánu ọhun le awọn ọmọ wọn lọwọ, eyi ti ko ni jẹ ka tete ri ọna abayọ siwa ajẹbanu naa."" Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú Ojisẹ Ọlọrun naa ni gbogbo ẹka awujọ ni iwa ajẹbanu ti gogo pupọ, tàwọn oloselu atawọn gbajumọ si n ko owo ilu, ti wọn si tun n fi le awọn ọmọ wọn lọwọ. Wolii Ajani wa rọ awọn ojisẹ Ọlọrun lati maa waasu tako iwa ibajẹ naa, ko le di ohun itan ni Naijiria Ọ̀pọ̀ nkan tó n ṣẹlẹ̀ kò jẹ́ kí n gbàgbọ́ pé Naijiria wà ní abẹ́ ìdarí ẹnikẹ́ni - Wole Soyinka Agba onkọwe, Ọjọgbọn Wole Soyinka ti sọ pe, oun ko gbagbọ pe Naijiria wa ni abẹ idari ẹnikẹni. O sọ eyi nibi ayẹyẹ ikojade iwe rẹ tuntun, 'Chronicles of the happiest people on earth', nilu Eko. Ọjọgbọn Wole Soyinka ṣapejuwe ọdun 2020 gẹgẹ bi eyi to ti buru julọ ti oun mọ lorilẹ-ede Naijiria. O ni kii ṣe nitori ajakalẹ aarun Covid-19 nikan, ṣugbọn ọpọlọpọ awọn iṣẹlẹ to waye, ati iha ti ijọba kọ si wọn. O to ogoji ọdun ti Soyinka ti n kọ iwe naa, ko to o gbe jade lọdun 2020. 'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan' Soyinka ni bi nkan ṣe ri bayii ni Naijiria, awọn ọmọ Naijiria ko mọ ibi ti wọn n lọ, tabi ibi ti irinajo wọn yoo pari si. ""Nnkan ti de ikorita ti eeyan ko ni idaniloju ibi to n lọ, ati ibi ti yoo pari rẹ si. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ""Bi mo ṣe sọ tẹlẹ, ọpọlọpọ nkan to n ṣẹlẹ ko jẹ kii eeyan o gbagbọ pe ẹnikẹni wa ni iṣakoso."" Soyinka sọ pe ọdun 2020 kii ṣe ọdun to dara rara fun oun, ni gbogbo ọna.",0,yoruba "Balogun tẹlẹ fun ikọ agbabọọlu Super Eagles , Joseph Yobo ti fọwọ sọya pe didun lọ̀san yoo so fun ikọ agbabọọlu ilẹ wa naa. Yobo ni tawọn ikọ asoju Naijiria ni AFCON 2019 ba lee se ara wọn lọkan, ti wọn gba bọọlu pẹlu irẹpọ, ti wọn si ri ara wọn bii ẹbi kansoso, wọn yoo gba ife ẹyẹ naa. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Bakan naa ni Yobo ni inu oun dun lati jẹ agbabọọlu akọkọ ti yoo soju orilẹ́ede Naijiria ninu ere bọọlu fun igba ọgọrun.",0,yoruba Yoruba Nation: Ìjọba Nàìjíríà ló ń dún mọ̀huru mọ́ Benin Republic lati dé Sunday Igboho mọ́ àhámọ́ - Gani Adams,0,yoruba "Láti ìparí ọdún 2016 , a ti fi ìtàn àwọn ènìyàn ṣe ìdánilẹ́kọ̀ọ́ àyíká fún àwọn èwe ní ìgbèríko Laos àti Thailand .",0,yoruba "A ò ní gb'ojú orun d'ójú ikú. Ó di ojúmọ́, kí ẹ jí mi bí ẹ bá jí o. Àjípé o!!!",0,yoruba "Kọmisana fun ajọ INEC nipinlẹ Ọyọ tun kede pe, Ọjọru ni gomina ti wọn dibo yan ati igbakeji rẹ yoo gba iwe mo yege ibo. Agboke lo sọ ọrọ yii lasiko to n gba ami ẹyẹ ‘Akinkanju ninu eto iselu tiwantiwa ti ile isẹ iroyin kan ni ilu Ibadan fun un. O wi pe ati oun ati awọn osisẹ Ajọ INEC ni ijọba ibilẹ mẹtalelọgbọn to wa ni ipinlẹ naa, lo koju isoro ibanilorukọjẹ, ìjínigbé, àti ìdúnkookò mọ́ni lásìkò ìbò, ti wọn si fẹ rẹ salọ kuro lẹnu idibo naa. Mutiu Agboke fi kun wi pe, lasiko ti ọrọ naa gbomi mu fun oun, ni oun pe Alaga apapọ fun Ajọ INEC, Ọjọgbọn Mahmood Yakubu wi pe, ki ni ki oun se, ti o si pasẹ fun un lati ka esi idibo naa, ki oun si se oun lori esi naa Èré Ọṣun: Àtáója ní wọn kò jí ère Ọṣun, ó sì wà níbi tó wà Kọmisọnna fun Ajọ eleto idibo INEC ni ipinlẹ Ọyọ naa wa fikun wi pe, Ọjọru ni gomina ti wọn dibo yan ati igbakeji rẹ yoo gba iwe mo yege ibo.",0,yoruba Lionel Messi: ''Kò sí ohun to lè mú Messi dúró sí Barcelona mọ́'',0,yoruba Píríǹtì,0,yoruba lọ. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀.,0,yoruba "Àwọn onímọ̀ ẹ̀rọ nípa oúnjẹ lórílẹ̀èdè Brazil ti se ìyẹ̀fun búrẹ́dì pẹ̀lú àwọn kòkòrò bíi aáyán tó wọ́pọ̀ ní ilẹ̀ Àfíríkà. Ajọ UN to ni ko to di ọdun 2050, eniyan to le ni billiọnu mẹsan ni yoo ma rin loke eepẹ, fikun wi pe, iyẹfun ti wọn fi kokoro ati aayan se dara fun eniyan, nitori eroja protein to pọ lara rẹ ju ti awọn eranko lọ. Eyi waye lẹyin ti awọn onimọ lati orilẹede Brazil gbe abajade iwadii wọn sita wi pe, isoro si ọwọn gogo ounjẹ lagbaye ni ki eniyan bẹrẹ si ni lo eroja asaraloore protein, lati fi pese ounjẹ to se ara loore. Eroja ti wọn fi se burẹdi yii lo ni iyẹfun eroja asaraloore latinu awọn kokoro Ninu ọrọ ti wọn, Ajọ Isọkan Agbaye ni, kokoro n sara loore, ti ko si wọn lati ri gẹgẹbi wọn ti n se lawọn apa agbeegbe kan ni Guusu-Ila oorun Asia. Amọ, awọn oniwadii imọ ijinlẹ ni Brazil naa fikun wi pe, aayan ti awọn fi se burẹdi yii kii se iru aayan ti wọn n rin kaakiri nilẹ n lẹ, sugbọn eleyii ti wọn didi tọju lati se ara loore ni ayika Ariwa Ilẹ Afirika ni. iwadii ni esunsun ni eroja asaraloore protein ju eran lo Awọn eroja kokoro miran ti awọn eniyan ma n jẹ ni alangba, alantakun, akekee, labalaba ati bẹẹ bẹẹ lọ. Èròjà Búrẹ́dì Brazil ni kokoro to ni protein to dára fún agọ ara ènìyàn",0,yoruba "Nibayi ti eto ipolongo ibo aarẹ ti bẹrẹ nigbaradi feto idibo gbogbo gboo to n bọ ni Naijiria, oniruru awuyewuye lo n lọ kaakiri. Bẹẹ ba gbagbe, laipẹ yii ni asaaju ẹgbẹ Afenifere, Alagba Ayo Adebanjo kede pe ẹyin oludije sipo aarẹ fẹgbẹ oselu Labour, Peter Obi ni oun to si. Bakan naa lo ni oun ko ni se atilẹyin fawọn oludije aarẹ fun ẹgbẹ oselu PDP ati APC, eyiun Atiku Abubakar ati Bola Tinubu. Idi ree ti BBC Yoruba se kan si asaaju ẹgbẹ Afenifere, Alagba Ayo Adebanjo lati se afọmọ ohun to ri, to fi yan oludije aarẹ kan nipọsin. Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, alagba Ayo Adebanjo ni kii se pe oun ko fẹran oludije sipo aarẹ fẹgbẹ oselu APC, Asiwaju Bola Ahmed Tinubu. Amọ o ni kii se ilan aoselu ti oun gbe le Tinubu lọwọ lo n se. “Tinubu ko duro ki mi ri, o maa n tẹ ki mi ni, bẹẹ ni Uncle lo n pe mi. Amọ kii se ilana oselu ti mo gbe le lọwọ lo n se, emi ati Tinubu gan sun mọra ju awọn alatilẹyin rẹ to n bu mi lọ. Bi Tinubu ba si di aarẹ lonii, maa jẹ anfaani rẹ ju awọn alatilẹyin rẹ gan lọ. Amọ ọna eru ni n ko fẹ ko gba di aarẹ.” Alagba Adebanjo tẹsiwaju pe o ti wa ni akọsilẹ ninu ofin Naijiria pe gbogbo ipo to ba da awọn ẹya to wa ni Naijiria papọ, a gbọdọ maa pin dgba-dọgba ni. O ni ofin Naijiria lo ni ipin ti ẹya kan ko gbọdọ ju ti ekeji l eyi to mu ka ni ofin ’Federal Character’, tii se ilana bu u re, la a re, ikan ko gbọdọ ju omii l. Adebanjo tẹsiwaju pe idi ree ta se ni ilana ’Rotation’ eyiun pinpin nnkan kaakiri. Eyi si lo ni o mu ki awọn ologun wa yan Yoruba lati di aarẹ lẹyin ti wọn da ibo aarẹ to gbe MKO Abiola wọle nu lọdun 1993. Adebanjo ni ni awọn ẹya to wa lapa ariwa Naijiria lo ti dari orilẹede yii, bakan naa ni ẹya Yoruba ati awọn eeyan ẹkun aarin gbugbun lati guusu Naijiria ti se aarẹ saaju. O ni kii se awọn ẹya to ti jẹ aarẹ saaju yii lo tun yẹ ka to si lẹyin, to si wa n beere pe ẹya Igbo n kọ? “Ẹyin wọn ni awa Afenifere duro si, a dẹ n fẹ ominira ẹ̀tọ́ ati ètò fun Naijiria. Ẹyin ki ipo aarẹ lọ sọdọ ẹya Igbo ni awa duro si, se ibo ko wa lati South East ni? Nigba to n woye lori ijijagbara fun orilẹede Yoruba ta mọ si Yoruba Nation, Adebanjọ ni ko si ẹnikẹni to le jade pe awọn n ja fun ilẹ Yoruba ju Afenifere lọ. Bakan naa lo ni ko si ẹni kankan to wa ni aye yii, to le ni oun n ja fun ifẹ Yoruba ju oun Ayo Adebanjo lọ. O wa fi ọwọ sọya pe oun ko se ounkohun tako ipe fun Yoruba Nation nitori awọn ọmọ oun lo n lewaju ipe naa. “Awọn ti oju n kan pe ti wọn ko ba se Naijiria ni ẹtọ ati ofin, yoo dara ka kuku yapa lo n pe fun Yoruba Nation. Awọn ologun lo gbe iwe ofin irẹjẹ le wa lọwọ, kii se ofin ti Awolowo, Azikiwe ati Balewa fọwọsi la n lo lasiko yii. Idi ree ta se duro lori sise agbeyẹwo ofin ilẹ wa nibi ta ti se agbekalẹ ilana atunto tun orilẹede yii. Mo si ti sọ fun Buhari pe to ba jẹ pe lootọ lo nif orilẹede Naijiria, yoo gba ka se atunto orilẹede yii. Sunday Igboho ati IPOB yoo dakẹ, bijọba ba se atunto Naijiria’ Alagba Adebanjo tẹsiwaju pe ẹya to wa lapa ariwa nikan lo n gba awọn ipo nla nla to wa ni Naijiria. Bakan naa lo tun koro oju si bi ijọba apapọ se n pariwo pe abẹ akoso awọn gomina ni ipese eto aabo nipinlẹ koowa wọn wa. Amọ o ni o se ni laanu pe awọn ohun ija ti wọn yoo lo lati pese aabo naa wa lọdọ ijọba apapọ, ti ko si fun awọn ipinlẹ lati lo wọn. O ni yoo dara ki Naijiria si wa papọ gẹgẹ bi orilẹede kan amọ ko seese ka wa papọ lori irẹjẹ. Nigba to n sọrọ lori ominira Naijiria, Adebanjo ni kaka ko san lara iya ajẹ ni ọrọ wa, se la kan n fi ọmọ wa bi obinrin, ti ẹyẹ wa n yi lu ẹyẹ. O ni se ni ohun gbogbo kan n buru si ni Naijiria, to si buru jai pupọ labẹ isejọba aarẹ Muhammadu Buhari.",0,yoruba "Ẹ kúu làákàyè @user tiwa ntiwa, á dára ka padà sí tiwa torípé bojúbojú l'òyìnbó lò fún wa. Real. IFÁ is pure truth. #Ephod #yoruba",0,yoruba owo ṣẹlẹ ni Eko ti gbogbo eniyan sọ o ṣe pataki. (2004),0,yoruba ìrìn ìròyìn. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó wáyé..,0,yoruba ǹjẹ́ ìwọ́ mọ̀ wípé àjẹnù ìrèkè a máa fa àkéréke bí ohun aládìńdùn ṣe ń fa kòkòrò,0,yoruba apero obinrin titled igbeaye opo,0,yoruba Agbègbè Ìkéde Pánẹ́ẹ̀lì,0,yoruba "RT @user: Ojúmọ́ ire ó ẹ̀yin olólùfẹ́ Alámọ̀já! How's the weather at your end today? Here, it is òtútù ń mú! Is it the same at yo…",0,yoruba "Isẹlẹ kikọlu awọn ajeji ti di ohun to n waye lemọlemọ ni orilẹede South Africa Nibayii, awọn ọmọ orilẹede Nigeria ti n sọrọ lori afojusun wọn lori ayipada isejọba yii. Jendele Hungbo, ọmọ orilẹede Naijiria kan to n gbe lagbegbe Mafikeng to ba BBC Yoruba sọrọ ni ko si afojusun kan ti awọn ọmọorilẹede Naijiria to n gbe ni orilẹede South Africa ni ju wipe wọn n se agbeyẹwo ijọba orilẹede South Africa ati ti Naijiria ni ifẹgbẹkẹgbẹ. Ipenija nla n bẹ niwaju fun aarẹ tuntun ni South Africa, Cyril Ramaphosa ""Lootọ isejọba yii pada sugbọn ohun ti awa gẹgẹbii ọmọ Naijiria ngbe yẹwo lori ọrọ yii ko ji afiwe ijọba orilẹede tiwa ni Naijiria ati ti South Africa ti a n gbe. Paapaajulọ lori awọn nkan bii ilana isejọba, idagbasoke ọrọ aje, ati igbayegbadun ọtun fun awọn ajeji to n gbe nibẹ."" Ohun kan ti awọn eniyan yoo fẹ mọ nipa ayipada yoowu to lee de eto isejọba ni orilẹede South Africa ni wahala ati ikọlu awọn ọmọ orilẹede ti kii se ọmọ orilẹede South Africa. Ọpọ igba ni wahala yii ti waye ninu eyi ti awọn ọmọ orilẹede South Africa yoo maa kọlu awọn ọmọ ilẹ okeere to n gbe nibẹ ti wọn yoo si ba dukia wọn jẹ. Isẹlẹ kikọlu awọn ajeji ti di ohun to n waye lemọlemọ ni orilẹede South Africa paapaa julọ laaring ọdun mẹsan sẹyin Lara awọn orilẹede ti ọmọ Naijiria pọ si julọ ni South Africa Amọsa, Ọgbẹni Jendele Hungbo ni awọn ọmọ orilẹede Naijiria to wa ni orilẹede South Africa ko ni igbagbọ wipe ikọlu awọn ajeji yoo dinku lasiko isejọba Cyril Ramaphosa. Lori ọrọ yii ohun to jaju nipe, se ijọba yoo gbe ajọ tabi ileesẹ silẹ lati dide si ọrọ yii. Sugbọn ni tiwa, ko si ireti pe yoo dinku. Saaju ko to kan isejọba yii ni ikọlu awọn ajeji ti bẹrẹ ni orilẹede South Africa ko si lee duro lori rẹ bi a se n woo yii."" Ọpọ ajeji ni wọn ti fara kaasa ni orilẹede South Africa Bakanna lo salaye wipe, pẹlu bi nkan se n lọ yii, afaimọ ki awo ẹgbẹ oselu ANC to n se ijọba ni orilẹede naa o maa sun lebi bi wọn ko ba tete fi ori ikoko sọọdun lori atunto to lee fun ẹgbẹ oselu naa lẹnu ọrọ ni ọdun 2019 ti ibo apapọ miran yoo waye. O ni ""alaafo ni wọn fi isejọba Ramaphosa di titi di igba ti ẹgbẹ oselu naa yoo fi ri ojutu si atunto to n gbero lori awọn afojusun rẹ gbogbo.",0,yoruba "lòdì Òyó. Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.",0,yoruba "Ní ní àìlẹ̀, Olùwo ri A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà. ti Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba pataki. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọmọ lo ojú odò.,0,yoruba ìwé orisirisi. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa àwọn ènìyàn: ti o nuni ti o ní wúlò fún.,0,yoruba @user @user @user Nkan ti bàjẹ́ kọjá báyẹn o! iwájú gbangba ni wọ́n ti ngbàá báyìí :),0,yoruba "àkokò, Bàbá lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó.",0,yoruba naa ní ègé olóótọ fún àwọn ìkòkò tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa aráyé: ti o tẹ.,0,yoruba "Arun lassa ni Naijiria Oludari ibudo yii, Chike Ihekweazu sọ eyi di mimọ pe afikun iṣẹlẹ mẹẹdọgbọ́n yii ti sọ gbogbo rẹ laarin oṣu kinni si isisiyii di ọọdunrun o le marun le laadọta ni ipinlẹ mọkandinlogun to fi mọ olu ilu orilẹede yii. 'Àwọn Dókítà fẹ́ kẹ́yin s'awọ̀n alárùn lassa' Kíni ọ̀nà àbáyọ sí àìsàn Lassa Fever? O ni o ti to eniyan marunlelaadọrin to ti gbẹmi mi latari iba Lassa lati igba to ti bẹrẹ. Gẹgẹ bo ṣe sọ ọ, ni bayii, ipinlẹ Edo, Ondo, Bauchi, Nasarawa, Ebonyi, Plateau, Taraba, Adamawa, Gombe, Kaduna, Kwara, Benue, Rivers, Kogi, Enugu, Imo, Delta, Oyo ati Kebbi to fi mọ ilu Abuja ni kọọkan lo ti ni akọsilẹ iṣẹlẹ iba Lassa. O j ko di mimọ pe, oṣiṣẹ eleto ilera kan naa tun ti fara ko o ni ipinlẹ Edo eyi to sọ ọ di mtala oṣiṣẹ eleto ilera to ti fara gba a lati igba to bẹ silẹ.",0,yoruba "Ọ̀tàkìtì pọ́n'wọ́ lá, Ò b'omi 'ẹ́nu fẹ́'ná jó, Ò fìdìí aró ìyá ẹ̀ ṣeléérú, Balúbodè lọ́run, Oólabí ojigan lóògùn, Olówó Gbáròyèé, Ọláàlú o gbére owó kò mí, kí Ajé ó máa jẹ́ mi.",0,yoruba o pataki. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọmọ lo se.,0,yoruba "Igbimọ alaṣẹ maa n ṣe ipade lọsẹ-ọ-ọsẹ Femi Adesina, ti o jẹ oluranlọwọ pataki fun Aarẹ Buhari lori ọrọ iroyin ati ipolongo, kede eyi ninu atẹjade kan to gbe jade ni ọjọ aje. Adesina sọ wi pe bi Aare Muhammadu Buhari ati ọpọlọpọ awọn aṣoju ati Minisita se n lọ fun eto pataki kan ni ile igbafẹ Transcorp Hotẹẹli nilu Abuja lọjọru, eyi ti i ṣe ọjọ ipade naa lo sokunfa wiwọgile ti wọn wọgile ipade naa. Gẹgẹbii atẹjade naa se sọ, ""Ipade awọn igbimọ alaṣẹ orilẹede yii ko nii waye ni ọjọru, ọjọ kejidinlọgbọn oṣu keji ọdun yii"" Aarẹ Buhari maa ndari iade igbimọ alaṣẹ ""Eleyi waye nitori pe ikopa ti Aarẹ Muhammadu Buhari ati awọn minisita pataki ninu ipade giga apero ti o da le lori ọrọ Chad nilu Abuja"". Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹ si:",0,yoruba "Wolii ijọ Kerubu ati Serafu kan, Joseph Ogundeji ti wọ gbaga ọlọpaa nipinlẹ Ogun fun biba awọn ọmọ iya meji kan lo pọ. Awọn ọlọpaa sọ pe, ọkan lara awọn ọmọbinrin naa loyun nipasẹ aṣemaṣe naa. Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ogun, Abimbọla Oyeyẹmi ṣalaye ninu atẹjade kan pe ọmọ ijọ Wolii Ogundeji ni awọn ọmọ iya mejeeji naa jẹ ati pe awọn ọlọpaa lọ fi panpẹ ofin mu wolii naa lẹyin ti wọn fi ẹjọ rẹ sun ni agọ ọlọpaa to wa lagbegbe Ajuwọn. O ni wolii naa jẹwọ nigba ti wọn fi ọrọ waa lẹnu wo pe lootọ loun ṣe aṣemaṣe naa. Iwadii ọlọpaa fihan pe ọkan lara awọn ọmọbinrin naa jẹ ọmọ ọdun mẹrindinlogun ti ikeji si jẹ ọmọ ọdun mẹtala “Awọn ọmọbinrin mejeeji yii fi to ọlọpaa leti pe pe nigbakugba ti wọn ba ti ni iṣọ oru ni ile ijọsin, wolii naa ti ile rẹ ko jina si ile ijọsin naa yoo ni ki awọn lọ sun si ile oun nigbakugba ti iṣọ oru naa baa pari ni nnkan bi agogo mẹta.” Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ogun sọ pe awọn ọmọbinrin naa tun sọ pe nigba kugba ti awọn ba ti wa ni ile wolii na yoo fun awọn ni nnkankan lati la, eleyi ti yoo mu wọn sun lọ ti awọn yoo si taji nigba to ba ya lati rii pe wolii ti ba awọn ni ibalopọ. “Nigba ti a bi wọn pe ki lo de ti wọn ko fi ọrọ naa to awọn obi wọn leti, wọn ni wolii naa leri lati pa awọn bi awọn ba sọ ọrọ naa fun ẹda alaye kankan.”",0,yoruba "Ìpinnu Ọdún Tuntun tó o ṣe ní ọjọ́ kìníní 2014, ǹjẹ́ o pámọ́ bí? »» http://t.co/32oVczPP1g #Yobamoodua #Bilingual #Blog #Yoruba",0,yoruba Chinese Simplified (_HZ),0,yoruba "Aishat Lola Iroyin to tẹ wa leti sọ pe ninu ile rẹ ni agbebe Samaru nipinlẹ Kaduna ni wọn ti ba oku rẹ pẹlu lẹta to kọ silẹ to fi dagbere fun awọn ọrẹ rẹ. Nigba ti BBC Yoruba ba ile iṣẹ Ọlọpaa sọ̀rọ̀, wọn ni lootọ ni Aisha mu majele. Lẹyin naa, wọn gbe e digba digba lọ sile iwosan ko to di pe o gbẹmi mi. Loju opo Twitter ọrẹ rẹ, @Mer_yherm jẹ ko di mimọ pe Aishat n ba oun sọrọ lọwọ lori Watsap lori eyi to ti fi lẹta idagbere to kọ kalẹ sọwọ si i ko to gbe majele jẹ. End of Twitter post, 1 Lati igba naa ni awọn ọmọ Naijiria ti n fi ọrọ ikẹdun ati erongba wọn lori igbesẹ yii ranṣẹ. Ninu lẹta rẹ, o pari rẹ pe ki wọn sin ohun ni kete ti wọn ba ti rii pe oun ku.",0,yoruba "Nígbà tí Ìyá fè joko, Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba "Buhari, ayẹyẹ kí là ń ṣe gan, ṣé ti ìpànìyàn àbí ìjínigbé? - Aráàlú ń bèèrè O mẹnuba oniruuru awọn nnkan to n ba orile-ede yii fira to si pe fun ifaraji, ifẹ ọmọlakeji ati igbara ẹni niyanju láti máa ṣe nkan to tọ. Lẹyin ti aarẹ Muhammadu sọrọ tan, ọpọ awọn ọmọ Naijiria lo ti n fi ero wọn han lawọn oju opo ibaraẹnidọrẹpọ loju opo itakun agbaye. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Odeh ninu atejisẹ rẹ soju opo Twitter ni, ki aarẹ ranti pe ko si nkan iwuri kankan ninu ayẹyẹ ominira ọgọta ọdun ti Naijiria. O ni ko si itẹsiwaju kan bikose pe nkan ń buru sii ni. Ninu ọrọ tirẹ @fingertrickz ni ọna àbáyọ kan ṣoṣo to yẹ, ni kí ijọba din owo awọn ọmọ ile ìgbímọ asofin ku, ti awọn miran si n fẹdun ọkan wọn han lori ọrọ airiṣẹse, lẹyin ọpọ ọdun ti wọn ti jade ile iwe. Lori ọrọ iye ti awọn orile-ede miran to ni epo rọbi n ta epo bẹtiro fun ara ilu aarẹ ni Egypt ₦211 Saudi Arabia ₦168 Chad ₦362 Niger ₦346 Ghana si n ta ni ₦326, ti Naijiria si ti n taa ni ₦161 báyìí. Goitre Patients: Àwọn èèyàn tó ní àrùn gẹ̀gẹ̀ ní ọ̀pọ̀ ìkórira àti ìdẹ́yẹsí ní àwọn ń kojú Ọpọ ọmọ Naijiria lo gbana jẹ lori eyi pe, ko tọ ki aarẹ maa fi owo epo Saudi we tí Naijiria nitori anfani ti Saudi n jẹ lati ọdọ ijọba ko ni afiwe, si iya ti ijọba Naijiria fi n jẹ ara ilu . Ẹlomiran tiẹ n beere pe elo ni owo osu osisẹ ni Naijiria ati ti Saudi, Ghana, Chad, Egypt. Gbajugbaja akoroyin ni Naijiria, Fisayo Soyombo ni ibanujẹ ni ọjọ oni nitori ọrẹ oun ti awọn ajinigbe jigbe ti pe ọjọ meji ni akamọ wọn. O ni o jẹ nkan itiju pe iru iṣẹlẹ yii n waye ni orile-ede to ti pe ọgọta ọdun, ijọba ko le pese nnkan tó ṣe koko lara nnkan ti ara ilu nilo, eyi to jẹ aabo to peye. Ibeere ti Thomas Ibu ni tirẹ ni pe, ajọyọ kini Naijiria n ṣe gan-an? Ṣe ti owo epo to wọn gogo ni? Tabi ti ọrọ ina mọnamọna to lọ soke ni? Ijinigbe gbogbo ati ipaniyan jakejado Naijiria, ṣe ti ainiṣẹ lọwọ awọn ọdọ ni abi kini gan-an.? Ọpọ loju opo twitter lo ń beere ibere yii bakan naa pe, ki ayẹyẹ ti a n se gan-an? Ẹnikan ni orile-ede ti a n ṣe ayẹyẹ rẹ yii, kii se eyi to yẹ wa. Ọgọta ọdun, ikuna isejọba ati ajẹbanu. October 1 Celebrant: Atinuke Oladeru ni kẹ yé ṣépè fún Nàíjíríà mọ́, ẹ pa ohùn dà Ọgọta ọdun eto ọrọ aje to dẹnukọlẹ. Ọgọta ọdun ninu gbigbọkan le epo rọọbi nikan ati aini isokan laarin awọn ẹya rẹ. Buhari, iye owó oṣù tí wọ́n ń san ni Saudi kọ́ ní wọ́n ń san ní Naijiria, má fi wá wé ara - Femi Falana Amofin agba ati ajafẹtọ ọmọniyan, Femi Falana ti sọ fun BBC pe ominira ti Naijiria n ṣajọyọ rẹ kii ṣe ominira rara, bikoṣe omi inira. Falana ni ọrọ ti Aarẹ Buhari sọ nipa owo epo nigba to n ba awọn ọmọ Naijiria sọrọ ko bojumu to, ati pe ko lẹtọọ ki Aarẹ maa ṣafiwe igbe aye awọn ọmọ naijiria si ti awọn eeyan Saudi Arabia. O ni ""Ọrọ aje orilẹ-ede wa ko ṣe dede nitori awọn to n ṣelu ko gbọ eyii ti awọn ara ilu n ṣe bikoṣe eyii ti ajo IMF ati banki agbaye ba sọ."" Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Amofin agba naa sọ pe itan ati afarawe iye ti wọn n ta epo ni Saudi Arabia ati Egypt ko kan awọn ara ilu lasiko yii, bikoṣe pe ki aijọba sọ fun wọn bi igbe aye wọn yoo ṣe gbe pẹẹli ju ti atẹyinwa lọ. Falana ni ti Aarẹ Buhari ba fẹ ṣe afiwe, ni ṣe lo yẹ ko bẹrẹ lati owo oṣu to kere ju ti awọn ọmọ orilẹ-ede Saudi Arabia n gba si ti Naijiria ko to sọrọ nipa iye ti wọn n san fun owo epo. O ni ""Ọfẹ ni owo ile iwe ati eto ilera ni Saudi, bakan naa ni ile iwe Ghana dara ju ti Naijiria lọ, idi ree ti awọn ọmọ ilẹ yii ṣe n kẹkọọ lọhun. Falana pari ọrọ rẹ pe o yẹ ki ijọba wo iru iya to n jẹ awọn ara ilu, ko si wa ọna abayọ sii ko to maa ṣafiwe iye owo epo. Ẹwẹ, nigba to n da si ọrọ naa, akọwe ẹgbẹ Afenifere, Yinka Odumakin ni bo tilẹ jẹ pe o ti pe ọgọta ọdun ti Naijiria gba ominira kuro loko ẹru ijọba ilẹ Gẹẹsi, inu oko ẹru naa ṣi ni awọn ọmọ Naijiria wa sibẹ. O ni bo tilẹ jẹ pe o ti pe ọgọta ọdun ti Naijiria gba ominira lọwọ ijọba amunisin oyinbo alawọ funfun, abẹ ijọba amunisin abẹ ile ni Naijiria wa sibẹ. Odumakin sọ pe Naijiria ti di ilu to n ba aye awọn ọmọ onilu jẹ, eyii to mu ki ọpọ eeyan maa funrere pe ki Naijiria tu ka. Gẹgẹ bo ṣe sọ, o ni Naijiria ko ni ilọsiwaju kankan to lamilaaka lati ọgọta ọdun sẹyin. O tẹsiwaju pe ""Ina Naijiria n jo ajorẹyin ni, nitori ko si olori tuntun kankan to jẹ nilẹ yii ti asiko rẹ ko buru ju ti ẹni to jẹ ṣaaju rẹ lọ."" Bo tilẹ jẹ pe Odumakin sọ pe Afẹnifẹre ko fẹ ki Naijiria tu ka, ṣugbọn o ni erongba ẹgbẹ ọhun ni ki atunto de ba eto ijọba Naijiria. Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin? Buhari Independence Live Broadcast: Wo àwọn kókó tó wà nínú ọ̀rọ̀ tí ààrẹ bá ọmọ Nàíjíríà sọ Aarẹ Muhammadu Buhari ti sọ pe, kii ṣe Naijiria ni epo rọbi ti wọn ju lagbaye nitori epo wọn ni awọn orilẹ-ede kan bii Ghana ati Niger ju Naijiria lọ. Buhari lo kede bẹẹ nigba to n bawọn ọmọ Naijiria sọrọ laarọ ọjọ kinni, oṣu Kẹwaa, ọdun 2020, fun ajọyọ ọgọta ọdun ti Naijiria gba ominira lọwọ oyinbo alawọ funfun. Bakan naa lo fi kun pe, owo epo Naijiria lo si dinwo julọ lẹkun iwọ oorun Afirika nitori N326 ni wọ́n ń ta jáálá epo ní Ghana, N211 ní Egypt, ní ìgbà tó jẹ́ N168 ní Saudi Arabia. Aarẹ wa woye pe, kò mú ọpọlọ lọ́wọ́ kí owó epo bẹntiróòlù ní Nàìjíríà dinwo ju ti orilẹede Saudi Arabia lọ. Awọn koko to wa ninu ọrọ ti aarẹ Buhari bawọn ọmọ Naijiria sọ ree:",0,yoruba Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó ṣe pàtàkì. (Item 132),0,yoruba "ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Nitori eyi, ara eni lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé mú yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba """Davido ń tọpasẹ̀ bí àwa olórin àtijọ́ ṣe máa ń bọ̀wọ́ fáwọn àgbà olórin tó kọ wa níṣẹ́ ni"" Gbajugbaja ati ilumọọka olorin ni Naijiria, Yinka Ayefele ti sọrọ lori gbogbo ohun tawọn eeyan n sọ si igbesẹ gbajumọ ọdọ olori David Adeleke to n jẹ Davido nipa owo gọbọi to ri ko jọ fun ọjọ ibi rẹ amọ to dari si ọdọ awọn ọmọ alailobi ni Naijiria. Ilé alájà tí Ṣọ́ọ̀ṣì Salvation Ministry ń lò dàwó, Ọlọ́pàá ní èèyàn mẹ́ta ní wọ́n rí tó ti kú 'Mo sọ fún Dókítà pé èmi ò lè gé ọyàn mi, pé ṣọ́ọ̀ṣì yóò fi àdúrà ṣẹ́gun àìsàn jẹjẹrẹ ọmú fún mi àmọ́ ...' Wọ́n fún mi ní ""sack letter"" lẹ́yìn tí ìyá mi kúnlẹ̀ bẹ̀ wọ́n láti sọ ìdí tí mi ò fi lè lọ ọ́fíìsì - Raymond Adegoke Yinka Ayefele jẹ́ ko di mimọ pe iwa ire yii latọwọ Davido kii ṣe akọkọ tori o ti ya oun gan lẹ́nu ri lai ṣe pe awọn ti kọkọ pade tabi ni ajọṣepọ. ""Davido ti fi itan ayeraye silẹ̀, kò tíì sí eléré tó ṣe irú ǹkan tó ṣe, àfi táa bá ṣẹ̀ máa ṣe, èèyàn mélò nínú wa ló dẹ̀ lè rí irú àǹfàní yìí tí kò ní kọ́kọ́ rántí ìyá tirẹ̀ tàbí àbúrò. Iwa ọtọọtọ lo wa ninu wa"". Yinka Ayefele ni Davido kò jọ àwọn kan nínú iṣẹ́ orin tá máa tẹ ojú ọ̀gá orin tí wọ́n kọ́kọ́ ń wò bí àwòkọ́ṣe. “Lọjọ ti mo kọkọ maa pade Davido, lai ṣe pe a ti rira ri tabi ni ajọṣepọ kan, o kọkọ wa di mọ mi latẹyin to n ṣe Daddy mi Daddy mi, inu mi dun”. O ni o yatọ si awọn olorin kekeke kan to jẹ pe ọla orin ti agba olorin kọ gan lo fi n jẹun amọ wọn lee yẹyẹ agba olorin yẹn ti wọn ba jọ pade. “Davido tiẹ́ kọkọ bu ọla fun mi, o yọ mọ mi, di mọ mi to tun n pe mi ni Daddy rẹ, inu mi dun”. Lẹyin igba akọkọ ti awọn olorin mejeji yii pade, Ayefele ni awọn tun ti pade to si n bu ọla fun oun, to n fẹ ba oun ya fọto to si jẹ pe irawọ agbaye ni Davido koda titi de Amẹrika lo ni o tun ti n sare bọ wa ki oun. Ayefele ni iwa ire ni iwa ti Davido ni ko si si olorin to ti ṣe iru nkan to ṣe fawọn alailobi yii ri afi ti awọn ba ṣẹ maa tọọ lẹyin.",0,yoruba ìbadandun. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé.,0,yoruba Àfẹ́ẹ̀rí ► to be invisible in Yorùbá. (Ọdẹ lo àfẹ́ẹ̀rí - the hunter became invisible) #InYoruba,0,yoruba "o wo fun ipilẹ̀ ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó tìkẹ́ gbé joko yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú.",0,yoruba wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìwà: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba "ìròyìn. Nitori eyi, ara eni lo ni ìwájú.",0,yoruba nípé ìròhìn nípa pọ̀ tí a lè sọ̀rọ̀ lé lórí ní orí ayélujára tí aráyé fẹ́ mọ̀ ní pa,0,yoruba "a kọ eḳọ nípa ire àti ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìbàdandun, àwọn ẹ̀kọ́ ọmọ aláwọ̀ wà níṣẹ̀.",0,yoruba ni a ní nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o nuni ti o nuni ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ àti ìbi tí wọn wà.,0,yoruba "@user @user @user @user @user @user @user @user @user Ẹ kú iṣẹ́ náà, Olódùmarè yó tì yín lẹ́yìn.",0,yoruba àìkú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ẹkọ́: ti o jare.,0,yoruba fálétí náà ni atọ́kùn ètò àkọ́kọ́ ní yorùbá lórí rédíò àti lórí amóhùn máwòràán fálétí lọ sí yunifásítì dakar ní orílẹ̀ èdè senegal ni tí ó sì gba iwé ẹ̀rí nínú èdè faransé àti ọ̀làjú ní ọdún ó ṣe tán ní yunifásítì ìbàdàn tí ó sì gba ìwé ẹ̀rí nínu,0,yoruba re yóò ri Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "ìbàdandun àtọ́wọ́dá, àwọn oníṣẹ́ ìṣẹ́ ni a ní láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..",0,yoruba eku ife sugbon ni ile yoruba omo eni okin buru titi ka fi fun ekun pa je ọlọrun aláàbò wa ẹni tí ń gbé abẹ́ ààbò ọ̀gá ògotí ó wà lábẹ́ òjì eba wa da ààbò bo,0,yoruba "kọ. Nitori eyi, ara eni yi ojú òní.",0,yoruba wáyé.. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ẹkọ́: ti o dara.,0,yoruba olùparapọ̀ ri pe nilo ayẹwo wey ti o dun.,0,yoruba "Ni nkan bi oṣu melo kan sẹyin ni gbogbo awọn ololufẹ oṣere naa n kọ haa lẹyin ti wọn ri foto oṣere yii lori ayelujara instagram rẹ. Nigba ti awọn kan n ki ku orire ni awọn miiran n sọ pe awo sinima to fẹ gbe jade ni. Kí nìdí tí gbajúgbajà òṣèré Sotayo Gaga ṣègbéyàwó bóńkẹ́lẹ́? Mo ti ní ìyàwó àfẹ́sọ́nà, ayẹyẹ ìgbeyàwó mi ń bọ̀ láìpẹ́ - Lateef Adedimeji Arapa re gangan sọ̀rọ̀ nípa ìrìnàjò ìpè rẹ̀ tuntun Wo àwọn Ọ̀gá Àgbà Ọlọ́pàá tó ti jẹ́ látọdún 1999 Kí ló lè ṣekúpa olùkọ́ fásitì Adekunle Ajasin tẹ́lẹ̀ tó dákẹ́ sínú mọ́tò rẹ̀ yìí? Sugbọn ninu ifọrọwerọ pẹlu iwe iroyin kan ni Sotayo ti fi idi ọrọ naa mulẹ pe lootọ ni oun ṣe igbeyawo ati pe o ti to ọdun meje sẹyin ni oun ti mọ ọ. O ní, ""mo ti ṣe igbeyawo, ọkọ mi kii si ṣe oni tiata. O ti ṣe diẹ ti mo ti ṣe iyawo. Mo ti mọ ọkọ mi fun ọdun meje ki a to ṣe igbeyawo. Ti ẹ ba mọ mi, ẹ mọ pe mi kii gbe ọrọ ara mi sita. Mo ti wa pẹlu ọkọ mi lati ọdun meje sẹyin. Irubọ ni ọrọ igbeyawo. ""Mo n ka nkan miiran lori awọn iwe iroyin ayelujara mo si rẹrin: gbogbo ibi ti wọn ba fẹ ni wọn le tan an ka de, mi o nifẹ lati maa gbe nkan to ba kan mi si aaye ara mi, nitori rẹ ni mo se fi igbeyawo mi ṣe idakọnkọ. Kii ṣe ọdun yii ni mo ṣe igbeyawo, mo kan ṣẹṣẹ fi fọto igbeyawo mi sita ni oṣu diẹ sẹyin ni."" Àwọn nkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa adelé Ọ̀gá Àgbà ọlọ́pàá ti Buhari ṣẹ̀ṣẹ̀ yàn Àrà kìí tán nílé alárà! Aláboyún oṣù mẹ́jọ, Aminat Idris borí nínú ìdíje Taekwondo Asọtẹ́lẹ̀ ikú Yinka Odumakin ti jáde sí wa tẹ́lẹ̀, ẹbí gbàdúrà, àmọ́...- Jacob Odumakin Àwọn òbìnrin tó ń ya fọ́tò ìhòhò ara wọn níwájú ilé kó sí gbaga ọlọ́pàá!Gbajugbaja oṣere naa, to tun jẹ oniṣowo aṣọ fidirẹ mulẹ pe lootọ ni oun ko kopa ninu awọn Sinima pupọ lati bi ọjọ mẹta sẹyin nitori pe oun n di asiko yii moju to ọrọ aṣọ ti mo n ta ni, eyi ti mo ṣẹṣẹ ṣi ẹka kan si Abuja. O ni ""asiko wa dun gbogbo nkan, mo si ni igbagbọ pe gbogbo nkan ri eniyan ba fẹ ṣe eniyan gbọdọ wa asiko fun. Fun emi, ọpọ lo n fi atẹjiṣẹ ranṣẹ pe awọn o ri mi ninu sinima mọ, nigba miiran eeyan a ma fi iṣẹ silẹ lati wa owo. Igba miiran wa ti mo ma n fẹ lati ṣe sinima, gbigbo ẹni to ba si pe mi fun ere lasiko naa, mo n da wọn lohun, mo si le ṣe sinima meji si mẹta. ""Igba miran si wa ti mi o le ṣe sinima, ki n sọ ootọ iṣẹ aṣọ ti mo n ṣe o maa n gba asiko gidi afi ti ko ba si adojusun. Mo ṣi sọọbu tuntun kan ni Abuja, ibẹ naa si ni ile mi wa nitori ibẹ ni awọn alabara mi pọ si. Ni bayii iṣẹ aṣọ ni mo gbajumọ bi mo ṣe n ta ni mo n ra ""Mo ti ni oju ti awọn eniyan n fẹ ninu sinima, ti mo ba di silẹ diẹ lati lọ ṣowo, igbkuugba ti mo ba pada de ko ai eni ti yoo mọ pe mo fi igba kan kuro. Ti mo ba ri ọwọ nilẹ ni mo n ṣe sinima bayii.",0,yoruba "Igba mi owó àkokò, Ìyá ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó wáyé..",0,yoruba Bákan náà ni Omarah gbóríyìn fún iléeṣẹ́ eré orí ìtàgé Nollywood ti Nàìjíríà .,0,yoruba pe jẹ́ pàtàkì wey ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó jáde nìlẹ̀̀ní sáàrí ti nípa ìtànká àti ire ènìyàn.,0,yoruba iṣẹ́ ṣẹlẹ ni Ibadan ti gbogbo eniyan sọ o dara. (1990),0,yoruba "Oju opo ikansiraẹni Twitter gomina naa ni o ti fi lede wi pe oun ti sọ Amọtẹkun di ofin ni ipinlẹ naa. End of Twitter post, 1 Gomina naa fi da awọn eniyan loju wi pe eto aabo fun awọn eniyan ipinlẹ naa lo jẹ oun logun. Atiwipe awọn ti ṣetan lati ri daju pe awọn ṣe oun gbogbo ti awọn nilo lati ri wi pe eto aabo to gbooro wa ni ipinlẹ naa. Awọn eniyan eniyan to fesi si oun ti gomina naa sọ gboriyin fun Akeredolu fun ipa ribiribi to ko nipa ifilọlẹ ikọ amọtẹkun fun eto aabo ipinlẹ naa ati ilẹ Yoruba lapaapọ. Bẹẹ naa ni awọn eniyan lori ẹrọ Twitter naa ki awọn eniyan ipinlẹ Ondo ku oriire fun aṣeyori ofin to rọ mọ ikọ Amọtẹkun. Bakan naa, gbogbo awọn ile igbimọ aṣofin to wa ni ilẹ Yoruba ni wọn ti buwọlu abadofin naa, ti wọn si ti fi ṣọwọ si gomina ipinlẹ naa lati buwọ lu u.",0,yoruba "Ní wéré kí ètò ìdìbò ààrẹ ọdún 2015 ó wá sáyé ni ìṣẹ̀lẹ̀ ìjínigbé àwọn ọmọdébìnrin Chibok ṣẹ̀ , tí èyí sì mú kí àwọn kan ó máa fi ojú ìgbèlẹ́yìn ẹgbẹ́ olóṣèlú kan wo ìgbàwí tí Ezekwesili ń bá ká lórí ayélujára .",0,yoruba Oṣù Kẹfà tún ti ń kan ilẹ̀kùn. Orí bá mi ṣe o,0,yoruba "tí Ìyá fè lọ, Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba Ifipa ba Zainab lọ pọ ati siseku pa ba awọn eeyan lọkan jẹ ni orilẹede Pakistan Wọn ri oku Zainab Ansari l'ori akitan ni igboro Kasur to wa ni guusu Lahore ni ọjọ kẹsan osu kinni ọdun yii. Iṣekupa ọmọbirin naa s'ọkunfa ifẹhonu-han kakiri orilẹede naa pẹlu rogbodiyan lori esun aimọse ọlọpa. Baba ọmọbirin naa lo si ile ẹjọ lati gbọ idajọ naa l'abẹ aabo to peye. Wọn ti fi ẹsun sise asemase si awọn ọmọbirin miran kan Ali Awọn ọlọpa ati ọlọtu ipinlẹ f'ẹsun kan apaniyan naa lori ikọlu ati ipaniyan to sẹlẹ si awọn ọmọbirin l'agbegbe naan. Ogunlọgọ eeyan lo se ẹlẹri ijọba lori ẹjọ Ali nibi ti ẹri ti wọn ti ẹri to peye han.,0,yoruba ilera ṣẹlẹ ni Eko ti gbogbo eniyan sọ o dara. (2025),0,yoruba "RT @user: 9. Ọọ̀ni ti Ifẹ̀, Àkárìgbò ti Rẹ́mọ, Ataọjà Òṣogbo. Aláàfin ti Ọ̀yọ́, ____ ti Èkó. #ibeere #Yoruba",0,yoruba "RT @user: Emi fe moo!""""""""""""""""@user: Àwọn wo ni Yoòbá ń pé ní alábaraméjì? #ibeere #QnA #yoruba""""""""""""""""",0,yoruba RT @user: 'Eni Eegun ba nle ko maa r'oju; Tori b'oti n re ara aiye ni n re ara orun' #Yoruba #Nigeria #AfricanProverb ..Translatio ...,0,yoruba "Awọn ọmọ adugbo ṣe ọṣẹ fun eekan osere tiata Yoruba, Toyin Abraham nibi to ti lọ ya sinima kan, to pe akọle rẹ ni Ige, laipẹ yii. Gẹgẹ bi ohun ti oun funrarẹ sọ ninu fidio kan, awọn ọraisa naa yabo ibi to ti lọ ya sinima naa, ti wọn si n beere owo gọbọi, ki wọn to lee jẹ ki oun atawọn ikọ rẹ fi irọrun ya sinima naa. Amọ gbogbo bi Toyin ṣe n fi ohun irẹlẹ ba awọn eeyan naa sọrọ, lo n ja si pabo, to si n rọ wọn lati gba owo lọ fi ra ọti lile. Lẹyin ti wọn faa sọtun ati sosi, lo fun awọn janduku naa ni ẹgbẹrun mẹwaa Naira lati fi lọ gbadun ara wọn. Amọṣa awọn janduku naa fariga pe owo naa ti kere ju fun wọn, ti wọn si ni ko tubọ gbọn ọwọ si. Toyin Abraham wa ṣalaye fun wọn tirẹlẹ tirẹlẹ pe owo ko fi bẹẹ pọ lọwọ oun. O ni oun ṣẹṣẹ san ẹgbẹrun lọna ọgọfa naira fun awọn ti oun lo gẹgẹ bi ero, ni ibudo ti oun ti n ya sinima naa ni, eyi si lo mu kawọn janduku naa gba owo naa lọwọ rẹ. Bakan naa lo ṣalaye pe, oun ti kọkọ fun wọn ni ẹgbẹ̀run marun naira tẹlẹ lati fi mu ẹlẹrindodo ati pe, ko tun yẹ ki wọn daamu oun mọ lori ọrọ owo. Nigba to n salaye isẹlẹ yii loju opo Instagram rẹ, Toyin Abraham ni awọn yoo fun awọn eeyan yii ni owo, wọn yoo tun maa fapa janu pe o kere, awọn n fẹ si. O ni irufẹ isẹlẹ yii ni awọn maa n la kọja loore koore lasiko ti awọn ba n ya sinima sugbọn awọn si nifẹ awọn eeyan naa sa.",0,yoruba ojumore fun gbogbo wa loni o a o ni kan agbako o,0,yoruba "Iṣẹ́ ìyá lórí ọmọ, gbàngbàgbàngbà ni. #HappyMothersDay",0,yoruba "Wọ́n á ní """"""""""""""""you are old school"""""""""""""""" bí o bá ń fẹ́ ṣe nǹkan ìwáṣẹ̀, tàbí àṣà ilẹ̀ẹ wa. #YorùbáRonu",0,yoruba "ri Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Nitori eyi, ara eni lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun.",0,yoruba pe nilo ayẹwo wey ti o ní wúlò.,0,yoruba ti ipá tipá la fi fẹ́ràn ṣàngó túlàsì ni ti lárúbáwá o gbọdọ̀ ṣe bẹ́ẹ̀ ni àì ṣe bẹ́ẹ̀ ńkọ́,0,yoruba "Dokita Shanna Swan sọ ninu iwe tuntun rẹ to kọ ti akọle rẹ n jẹ ""Count Down"" sọ pe ọmọ eniyan n doju kọ iṣoro iloyun ati ibimọ latari kẹmika kan ti wọn n pe ni ""phthalates"" to n fa ki wọn bi ọmọ ikoko pẹlu nkan kunrin tabi obinrin ti ko ṣara jọ daadaa. Ninu iwe naa, arabinrin Shanna ṣagbeyẹwo bi wọn ṣe n fi ọwọ yẹpẹrẹ mu iye atọ ọmọkunrin to n jade eyi to maa ṣakoba fun idagbasoke ilana ibimọ ọkunrin ati obinrin to si n ko ọjọ iwaju sinu ewu. Latari idọti ayika nkan ọmọkunrin tabi obinrin yii, awọn ọmọ ti wọn n bi ti nkan ọmọkunrin wọn kere ti n pọ sii. 'Èmi àti ìyàwó mi ti ń gbé pọ̀ nínú ìgbéyàwó wa fún 60 years', ẹ wá kọ́ ẹ̀kọ́ lẹ́nu àgbà méjì Bí Oduduwa Republic bá bẹ̀rẹ̀, a ò ní ṣe aburú fún àwọn tó takò wá, ìlànà ààtẹ̀lé rèé - Banji Akintoye Iwadi Dokita Swan fihan gẹgẹ bi wọn ṣe fi awọn ekute ṣe ayẹwo kẹmika phthalate ọhun ti wọn si rii pe nigba ti wọn fi ṣi ara ọmọ oyun inu wọn si kẹmika naa, o da bii pe wọn yoo bi awọn ọmọ naa pẹlu nkan ọmọ ọkunrin konkolo. O wadii pe awọn ikoko ọkunrin ti ara wọn ba ni nkan ṣe pẹlu phthalates ninu oyun maa n ni awọn nkan to rọ mọ nkan ọmọkunrin kukuru. Kẹmika naa ni iṣẹ to n ṣe ni awọn ileeṣẹ ti wọn fi n mu ki ike rọba fẹlẹ sii ṣugbọn Dokita Swan ni awọn kẹmika naa ti n wọ inu awọn nkan iṣere ati ounjẹ to si n ṣakoba fun idagbasoke eeyan. Ki ni itumọ kẹmika Phthalate to n mu nkan ọmọkunrin kere? Phthalates jẹ akojọpọ awọn kẹmika ti wọn fi ṣe nkan elo pupọ bii iṣere ọmọde, nkan ti wọn n lẹ mọlẹ, lẹ m ogiri, ọṣẹ, ọili, nkan iko ounjẹ si, awn nkan ilera, apo ẹjẹ ati bẹẹ bẹẹ lọ. Wọn maa n lo o ninu awọn oun elo aṣaraloge bii kẹmika ti wọn fi n nu eekana, iparun, ipa abiya lẹ́yìn fifa irun ibẹ, ọṣẹ iwẹ, ọṣẹ ifọrun, lọfinda ati bẹẹ lọ. Wọn maa n lo o lati mu polyvinyl chloride, iyẹn ike rọba ti wọn si tun nlo bii amu nkan yọ ninu awọn ipara. Ninu akọsilẹ iwe kan ti awọn onimọ Sayẹnsi tun fi si ori ayelujara Medical news website, wọn ṣalaye awọn idi mii to fi le mu nkan ọmọ ọkunrin kere sii. Báa ṣe lọ́pọlọ tó, ẹnu Yorùbá ò kò, ọgbọ́n táa gbúdọ̀ dá rèé - Ìpàdé àgbààgbà Yorùbá n'Ibadan Ki lawọn nkan mii to le mu ki nkan ọmọkunrin kere sii? Ki nkan ọmọkunrin maa kere wọpọ paapaa bi awọn ọkunrin ba ṣe n dagba si ṣugbọn awọn idi mii naa wa to le fi yoro. Ọjọ ori Bi ọkunrin ba ṣe n dagba sii, awọn nkan ọlọra to wa ninu ara wn a maa ṣa ara jọ ninu awọn nkan to maa n pin ẹjẹ kaakiri ara yoo si mu ki eyi dinku. eleyi maa mu ki awọn sẹẹli iṣan ara to wa nibi ohun to n mu nkan ọmọ ọkunrin le bẹrẹ si ni ṣaarẹ. Awọn tuubu to n mu nkan ọmọkunrin le maa ṣiṣẹ karakara ti ẹjẹ ba n wọ ibẹ daadaa torinaa bi ẹjẹ naa ba ti dinku, o tumọ si pe nkan ọkunrin naa ko ni maa fibẹẹ le ni gbogbo igba. Sisanra Ipa ti sisanra n ko paapaa ni agbegbe ikùn jẹ pabanbari fun ọpọlọpọ awọn ọkunrin bi wọn ba ṣe n dagba. Bo til jẹ pe nkan ọmọkunrin le fara han bii kekere nitori sisanra, amọ o le ma yoro. idi ti yoo fi jọ pe o kere ni pe ara ogiri ikun ni ibẹrẹ nkan ọmọkunrin wa bi ikun ba si ti n tobi sii, yoo fa nkan ọmọkunrin naa sinu. Bi eeyan ba wa jo lara, nkan ọmọkunrin rẹ yoo pada bọ sipo ati bo ṣe tobi si tẹlẹ. Iṣẹ abẹ abẹ́ ọmọkunrin Iwadii kan ninu Journal of Impotence Research fihan pe bi ọkunrin ba ni aisan jẹjẹrẹ abẹ, ti wọn si fẹ ṣe iṣẹ abẹ eyi ti wọn n pe ni radical prostatectomy, o lee ni iriri ki nkan ọmọkunrin rẹ kere Oogun lilo Awọn oogun kan wa to lee fa ki nkan ọmọkunrin kere. Awọn oogun bii Adderall ti wọn maa n lo fun ẹni ti iṣe féfé rẹ ba ti kọja ala, bakan naa awọn oogun to n wo iporuru ọkan san, oogun to n wo arun ọpọlọ san atawọn oogun mii ti dokita ba pe fun itọju abẹ wiwu. Siga Mimu Ni ọdun 1998, fasiti oniṣegun ti Boston ṣe ayẹwo nkan awọn ọkunrin igba to dide duro tandi. Abajade ayẹwo naa fihan pe, awọn to n mu siga, ti nkan ọmọkunrin wọn ba dide, o maa n kuru ju ti ẹni ti ko mu siga lọ. Idi si ni pe kẹmika to n jade lasiko ti wọn ba n fa siga simu lee ṣe ọna ti ẹjọ n gba lọ inu nkan ọmọ ọkunrin leṣe. O si lee dena ki ẹjẹ kun inu nkan ọmọkunrin naa eyi ti yoo fi dide. Lai wo ti miu ara ya ati ipa to n ko ninu ọpọlọ, bi ohun to n pin ẹjẹ kiri ba ti bajẹ, nkan ọmọkunrin ko le duro ko si ni le tandi.",0,yoruba ".@user eba wa se alaye owe Yoruba ti o so wipe """"""""""""""""""""""""""""""""Omo eni ku, o san ju omo eni nu lo"""""""""""""""""""""""""""""""" fun Aare @user ki wan se awon odomobirin #ChibokGirls ati #DapchiGirls ni awa ri. Oro ki ajini gbe pelu ipa ti wa di nkan nla bayi, jake jado Nijeria. Eyin adari eranti ikunle abiyamo o https://t.co/CXJIy7kahO",0,yoruba "Àwọn olórí Adó-Àkúrẹ́, fárígá, wọ́n ní wípé, Àkúrẹ́ gbọ́dọ̀ lọ singbà fún Benin, èyí wá mú rògbòdìyàn ṣẹlẹ̀ láàárín Àkúrẹ́ àti Adó-Àkúrẹ́ Benin ní iná tó ń jó wọn ní abẹ́ aṣọ lọ́wọ́, èyí tí kò fún wọn ní ìfọ̀kànbalẹ̀ láti pàṣẹ lórí àwọn ìlú tó wà ní abẹ́",0,yoruba "Ọwọ́ ni INEC fi kọ èsì ìbò ààrẹ, kò sí lórí ''server''-Okoye Atiku n beere esi idibo ibo aarẹ orilẹ-ede Naijiria to waye ninu oṣu keji, ọdun 2019. Kọmiṣọna ajọ eleto idibo INEC, Festus Okoye lo ṣalaye ọrọ naa nigba to ba BBC sọrọ lọjọ Ẹti. Ọgbẹni Okoye sọ pe esi ibo aarẹ ko si ninu ''server'' INEC tabi ẹrọ kọmputa nibi kankan. O ṣalaye pe ofin eto idibo lorilẹ-ede Naijiria ko sọ pe ki ajọ INEC ko esi idibo aarẹ sinu ''server'' kọmputa INEC. Barister lo bi gbogbo oníṣẹ́ fújì -Oṣupa Okoye ni ọwọ ni wọn fi kọ esi ibo ni gbogbo ibudo idibo kaakiri orilẹ-ede Naijiria, eleyi ti gbogbo awọn aṣoju ẹgbẹ osẹlu to wa nibẹ foju ri ti wọn si ni ẹda rẹ. Ladoja: Àwọn èèyàn Oyo fì ìbò sọ̀rọ̀ pé ìjọba Ajimobi kò dára O sọ pe awọn esi ibo yii ni wọn fi ṣọwọ si ajọ INEC lawọn ipinlẹ to fi de olu ile iṣẹ INEC nilu Abuja. Ẹwẹ, l'Ọjọbọ ni ajọ INEC ṣi aṣọ loju ọrọ yii nigba to sọ fun igbimọ igbẹjọ ibo aarẹ l'Abuja pe oun ko ni ''server'' ti Atiku ati PDP n beere fun. Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele",0,yoruba jare. Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Alàji lo ojú odò.,0,yoruba Toyin Adegbola: Ìdí rèé tí gbajúmọ̀ òṣèré ṣe fa wàhálà nílé ìtajà n‘Ibadan lórí ọ̀rọ̀ ọmọ rẹ̀,0,yoruba "Ileeṣẹ ọlọpaa ti fi ọrọ wa gbajugbaja akọrin takasufe, Augustine Kelechi, ti awọn eniyan mọ si Tekno lẹnu wo, lẹyin to rin kiri igboro ilu Eko ninu ọkọ kan pẹlu awọn obinrin to wa ni ihoho. Fidio kan, to da bi ẹni pe lati inu ọkọ miran ni ẹni to ya a ti ya aworan naa, ṣafihan ọkunrin kan to joko sinu ọkọ akẹru naa, ti wọn fi gilaasi sẹ ara rẹ, to si n nawo fun awọn obinrin to n jo pẹlu awọtẹlẹ wọn nikan. Tekno ti sọ pe fidio naa kii ṣe ipolowo fun ile faaji onihoho kankan. O sọ pe, oun wa ninu apoti oni gilaasi ọhun ti wọn gbe sinu ọkọ akẹru, ti oun si n lọ lati ibikan si ibomiran lati ya fidio awo orin tuntun. Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko, Bala Elkana sọ fun BBC pe, awọn ọlọpaa bẹrẹ iwadii lẹyin ti fidio naa fa awuyewuye lori ayelujara. Iroyin ti kọkọ jade pe, awọn ọlọpaa ti fi panpẹ gbe Tekno, ṣugbọn Ọgbẹni Elkana sọ pe, awọn kan pe e fun ifọrọwanilẹnuwo ni, ati pe fun ra a rẹ lo wa si agọ ọlọpaa lọjọ Iṣẹgun lati sọ tẹnu rẹ lori ọrọ naa. Wayi o, Tekno tọrọ aforiji lori ayelujara Instagram, fun ẹnikẹni ti fidio naa ba bi ninu. O ni ""A n ya fidio awo orin lọwọ ni diẹ lara awọn ọkọ ayọkẹlẹ ti a n lo bajẹ, a si nilo ọkọ lati ko awọn eniyan lọ si ibomiran ti a ti fẹ lọ ṣiṣẹ, lo jẹ ka lo ọkọ to ni apoti oni gilaasi naa."" Ṣugbọn ko ṣalaye idi to fi n ju owo lu awọn obirnin naa lasiko ti wọn n rinrinajo. Awọn ọlọpaa sọ pe, awọn ti yọnda Tekno, ṣugbọn iwadii ṣi n tẹsiwaju.",0,yoruba "àkokò, Bàbá lo ni ìgbà àkerekere ye ka yè.",0,yoruba "Kó dìde kó dìde o Ẹ̀rùgàlè kó dìde Tóò, ire gbogbo ẹ dìde, bí àrọ̀ gìdìgbà ṣe ń sọ lálẹ́ odò, bẹ́ẹ̀ ni kí gbogbo ire ó má sọ láyé èmi kin ní yìí. Kí ire ti ọ̀tún ó tọ̀ mí wá, kí t'òsì ó tọ̀ mí bọ̀, kí ń báre pàdé níwá, kí t'ẹ̀yìn ó bá mi. Ọ̀sẹ̀ yìí, ọ̀sẹ̀ ire",0,yoruba ó pé ọjọ́ mẹ́sànán tí a ti lo ináa mànàmáná ládùúgbò mi ẹ wá ní kí n máà pe lẹ́jọ́ ó lè fọwọ́ sí i,0,yoruba òbí rere ni ìwọ tí o bá mọ rírì ọmọ,0,yoruba "Pochettino ti buwọ luwe adehun lati ṣiṣẹ gẹgẹ akọnimọọgba fun ikọ agbabọọlu PSG fun ọdun meji pẹlu adehun miran lati fi ọdun kan kun un. Oun lo rọpo Thomas Tuchel to padanu iṣẹ rẹ lọjọ kọkandinlọgbọn oṣu kejila ọdun 2020 lẹyin to ti tukọ ẹgbẹ agbabọọlu naa fun ọdun meji ati aabọ. Pochettino ko ti ṣiṣẹ akọnimọọgba lati igba to ti fi ẹgbẹ agbabọọlu Tottenham silẹ ti Jose Mourinho si rọpo rẹ. Akọnimọọgba Pochettino naa ti figba kan ri ṣoju PSG gẹgẹ bi agbabọọlu laarin ọdun 2001 si 2003. Ipo kẹta ni PSG lori tabili idije Lique 1, ati pe Barcelona ni wọn yoo koju ni ipele ẹlẹni mẹrindinlogun(round of 16) ninu idije Champions League loṣu keji ati ikẹta ọdun 2021 yii. Ọjọ Aiku ọjọ kẹta oṣu kinni ọdun 2021 yii ni Pochettino yoo bẹrẹ iṣakuso rẹ ni PSG. ''Idunnu lo jẹ fun mi lati de ipo akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu yii. Gbogbo igba ni mo maa n ṣafẹri ẹgbẹ agbabọọlu yii,'' Pochettino lo sọ bẹẹ. Pochettino ni oun ''ṣetan lati ṣiṣẹ pọ pẹlu awọn agbaọjẹ agbabọọlu to wa ni PSG.'' Ninu ọrọ tirẹ, alaga igbimọ alaṣẹ ẹgbẹ agbabọọlu naa, Nasser Al-Khelaifi sọ pe Pochettino gan an lo to gbangba sun lọyẹ lati tukọ ẹgbẹ agbabọọlu PSG. Ẹgbẹ agbabọọlu Espanyol ni Pochettino ti kọkọ ṣiṣẹ gẹgẹ bi akọnimọọgba. Lẹyin naa lọ si ikọ agbabọọlu Southampton nibi to ti lo ọdun kan ati abọ ki o to darapọ mọ Tottenham lọdun 2014. Amọm ibeere kan tawọn eeyan n beere ni pe bo ya Pochettino le gba ife ẹyẹ UEFA Champions League ti PSG ti n gbiyanju lati gba fun wọn. Lootọọ ni Pochettino gbe Tottenham de ipele aṣekagba Champions League lọdun 2019 ṣugbọn wọn fidi rẹmi, Liverpool lo lu wọn gba ife naa.",0,yoruba "Ile ẹjọ naa sọ pe bi ọgagun Adeniyi ṣe ke gbajare ninu fidio kan to lu sita lori ayelujara tako ilana ileeṣẹ ọmọ ogun Naijiria. Lẹyin naa lo ni ki wọn rẹ ipo rẹ silẹ nile iṣẹ ọmọ ogun ni wọn ọdun mẹta ṣeyin. Ti ẹ ko ba gbagbe, Adeniyi farahan ninu fidio kan lawọn oṣu diẹ sẹyin, nibi to ti ke si awọn lọgalọga nileeṣẹ ọmọ ogun pe ki wọn gba awọn sọja sile nitori bi awọn ẹgbẹ agbesumọmi ṣe n pa wọn ni ipakupa. Ninu fidio ọhun lo ti ba awọn ọga rẹ rẹ sọrọ pe awọn ọmọ ogun ti oun ko sọdi ko jaya, wọn si n doju ija kọ awọn ọmọ ẹgbẹ Boko Haram, bẹẹ ni wọn ko si sa kuro loju ogun. Ile ẹjọ ọhun ṣe ẹjọ Adeniyi pẹlu amugbalẹgbẹ rẹ, Tokunbo Obanla, ti wọn sọ pe o jẹbi ẹsun ti wọn fi kan an, ti wọn si ni ko lọ fi ẹwọn jura fun ọjọ mejidinlọgbọn pẹlu iṣẹ aṣekara. Iroyin ni Adeniyi sọ fun ile ẹjọ naa pe oun gba pe lootọ ni oun jẹbi ẹsun mẹta ti wọn fi kan oun, lara eyii ti aṣilo oju opo ayelujara wa. Ileeṣẹ ologun ṣe idajọ Adeniyi lẹyin oṣu mẹjọ ti fidio naa lu sori ayelujara, nibi to ti sọrọ pe awọn ọmọ ogun to wa lẹyin oun ko ni irinṣẹ to to lati kọju ija si awọn ẹgbẹgun Boko Haram. Bakan naa lo tun sọ ninu fidio ọhun pe oun ija awọn ọmọ ẹgbẹ Boko Haram pọ, o si tun lagbara ju ti awọn ikọ ọmọ ogun Naijiria lọ. Lẹ́yìn ọ̀pọ̀lọ́pọ̀ oṣù tí òjò kò rọ̀ ní orílẹ̀èdè Cuba, Ọba ilẹ̀ Yorùbá ló Fidio naa ko dun mọ ileeṣẹ ologun ninu, ko si pẹ si asiko naa ti wọn fi iwe gbe kuro ni oju ija ọhun. Ṣugbọn Adeniyi sọ pe oun ko ṣe ohun ti ko dara, ati pe oun kọ lo gbe fidio naa jade lori ayelujara bo tilẹ jẹ pe o ti kọkọ sọ pe aṣiṣẹ ni oun fi gbe fidio naa jade si ojukaye. Ẹwẹ, agbẹjọro ọgagun naa ti sọ pe oun yoo pe ẹjọ kotẹmilọrun lodi si idajọ ọhun. Wo ohun tí wọ́n sọ nípa Owa Ale ìlú Ikare, Ọba Samule Kolapo Adegbite Adedoyin tó wàjà",0,yoruba Bọ́tìnì yìí ń sọ ní pàtó iye àwọn ìṣísẹ̀ tí férémù kọ̀ọ̀kan á ṣàfihàn.,0,yoruba pàtàkì wey ti o nuni ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó ṣe pàtàkì.,0,yoruba ayo ni ire owo ir,0,yoruba ilera ṣẹlẹ ni Ibadan ti gbogbo eniyan sọ o dara. (2016),0,yoruba "Oun ni agbabọọlu tẹnisii to ṣẹṣẹ ko aarun covid-19 lẹyin ti Grigor Dimitrov, Borna Coric ati Viktor Troicki sọ pe awọn ni coronavirus lẹyin ti wọn koju Djokovic ninu idije Adria Tour. Troicki ti oun naa jẹ ọmọ orilẹede Serbia ni Djokovic kọkọ koju ki o to koju Dimitrov ati Borna Coric. Ẹwẹ, gbajugbaja agbabọọlu tẹniisi ọmọ ilẹ Gẹẹsi, Andy Murray ni ẹkọ nla ni awọn agbabọọlu tẹniisi to lugbadi coronavirus jẹ fawọn yoku. Ọmọ ilẹ Australia, Nick Kyrgios ni tiẹ sọ pe igbesẹ lati maa kopa ninu idije tẹniisii lasiko ajakalẹ aarun covid-19 yii. Lati oṣu keji ọdun 2020 ni ajọ to n ri si ere idaraya tẹniisii, ATP ti fote le tẹniisii gbigba nitori ajakalẹ aarun coronavirus. Idije Adria Tour wa lara awọn idije tẹniisii to ṣẹṣẹ bẹrẹ laipẹ yii.",0,yoruba "Ẹ jẹ́ k'á gbé ọ̀ràn kan yẹ̀ wò, ọ̀rọ̀ oṣù ni. Ó níbi tí mo fẹ́ lọ, pẹ̀lú aláyé yékéyéké. Ẹ máa bá mi bọ̀! #OsuLe #Yoruba",0,yoruba "Eyi ko ṣẹyin ọkọ agbepo to gbina ni ilu Abeokuta, ti ẹmi eniyan mẹfa si lọ si iṣẹlẹ naa pẹlu ọpọlọpọ ọkọ to jona raurau. Gomina Abiodun lori Twitter rẹ ba awọn ẹbi ati ara to faragba ninu iṣẹlẹ naa kẹdun. Bakan naa ni o fikun wi pe awọn ti ranṣẹ si awọn to dokita to mọ nipa itọju awọn ti ina ba jo lati wa ranwọlọwọ pẹlu itọju awọn to farapa ninu ijamba ọkọ naa. Tirela naa lo ṣubu lẹyin to ti kọkọ kọlu ọkọ Jeep Lexus kan ko to gbina. Wọn ti ra rọ awọn awakọ pe ki wọn gba ọna miiran yatọ si opopona Kuto Road ati banki GTB. Niṣe ni ero lọ biba nibi ti ọkọ agbepo naa ti n jona ti wọn si n ṣe idiwọ fawọn oṣiṣẹ panapana. Tírélà agbépo bẹntírò gbiná nílùú Abeokuta, ọkọ̀ mérin jóná ráúráú Ọkọ tirela agbepo bẹntiro kan ti gbana lopopona Kuto Road si Okemosan niluu Abeokuta nipinlẹ Ogun. Ọpọ eeyan nin a gbọ pe o farapa nibi iṣẹlẹ naa. Awọn panapana si n ja fita fita lati pa ina ọhun. Tirela naa ṣubu lẹyin to ti kọkọ kọlu ọkọ Jeep Lexus kan ko to gbina. Okere tan ọkọ mẹrin ni a gbọ pe o jona raurau nibi iṣẹlẹ naa ti awọn to wa ninu rẹ si sa asala fun ẹmi wọ. Akomolede ati Asa: Alagba Ajibola láti Fakunle ní olùkọ́ wa lórí ètò ìró lónìí Wọn ti ra rọ awọn awakọ pe ki wọn gba ọna miiran yatọ si opopona Kuto Road ati banki GTB. Niṣe ni ero lọ biba nibi ti tanka naa ti n jona ti wọn si n ṣe idiwọ fawọn oṣiṣẹ panapana. Adigunjalè 24 tó ń jí epo rọ̀bì la mú ní Ondo- Ikọ̀ ọmọogun orí omi Sunday Igboho fún Fulani Oyo ní gbèǹdéke, Seriki fulani yarí, ọlọ́pàá dá síi... Wo ìpalára ní ọ̀nà mẹ́fà tó lè bá ènìyàn tí kò bá kí ń mu omi mímu tó ìwọn tó yẹ Ọlọ́pàá mẹ́rin kú, ọ̀kan dàwátì níbí ìkọlù tó wáyé ní Birnin-Gwari ní ìpínlẹ̀ Kaduna- Ọga Ọlọ́pàá Ẹbẹ lawọn oṣiṣẹ ileeṣẹ panapana n bẹ awọn ero wi pe ki wọn sun sẹyin ki awọn le ri ina ọhun pa. BBC findings on lekki shooting: Ẹ wa wo àwọn tó ṣì ń wá ẹbí wọn nínú ìṣẹ̀lẹ̀ End SARS 2020",0,yoruba "ìlú. Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Oludasilẹ ijọ Living Faith ti ọpọ mọ si Winners, ti ke si awọn Musulumi niluu Ilorin lati ko awọn ọmọ wọn lọ sile ẹkọ awọn Musulumi ti wọn ba fẹ ki wọn maa lo ijaabu. Oyedepo lo sọ ọrọ naa ninu iwaasu kan to ṣe lẹyin rogbodiyan ọrọ ijaabu to waye nile ẹkọ Baptist ati ECWA ni Ilorin. Ṣaaju ni Gomina ipinlẹ Kwara, AbdulRahman AbdulRazaq, ti kọkọ paṣẹ pe awọn akẹkọọ to jẹ Musulumi le maa wọ ijaabu nile ẹkọ ti awọn ọmọlẹyin Kristi da silẹ. Ṣugbọn aṣẹ naa ko dun mọ awọn Kristẹni ilu Ilorin ninu, eyii to da rogbodiyan silẹ. Oyedepo ni ""ohun to n ṣẹlẹ ni Kwara jẹ eyii to ba ni ninu jẹ gidi, nibi ti awọn awọn Musulumi ti sọ fun awọn Kristẹni lati gba ijaabu laaye nile ẹkọ ti wọn da silẹ"" ""Mi o tii ri ibikibi laye yii ti ayalegbe yoo ti maa paṣẹ fun onile... eredi rẹ si ni pe a ko tii fi odikeji Ọlọrun han wọn."" Alufaa naa sọ pe o yẹ ki wọn kilọ fun awọn ẹlẹsin miran pe ki wọn ṣọra fun awọn Kristẹni, ki wọn ma baa ri ibinu Ọlọrun. Oyedepo pari ọrọ rẹ pe ki awọn Musulumi ti ohun ti awọn Kristẹni n fẹ ko ba tẹ lọrun ko awọn ọmọ wọn lọ sile ẹkọ to jẹ ti awọn Musulumi. ""Ẹ dẹkun ati maa ki ika si oju ẹlomiran nigba ti wọn kii ṣe afọju,"" Oyedepo lo kilọ bẹẹ. Gomina ipinlẹ Kwara, AbdulRahman AbdulRazaq ti sọ pe ẹnikẹni to ba fa wahala nitori rogbodiyan ọrọ ijaabu to waye niluu Ilorin yoo foju wina ofin. AbdulRazaq lo sọ ọrọ naa lasiko to n ba awọn eeyan ipinlẹ naa sọrọ lọjọ Isẹgun lẹyin rogbodiyan to waye ṣaju nile ẹkọ Batist ati ECWA niluu Ilorin. Wahala ọhun bẹ silẹ lẹyin ti gomina ọhun kede lọjọ kẹrindinlọgbọn, oṣu Keji, ọdun yii pe, awọn akẹkọbinrin to jẹ Musulumi le maa wọ ijaabu lọ sile ẹkọ ti awọn Kristẹni da silẹ. Igbesẹ naa ko dun mọ wọn adari ile ẹkọ Kristẹni ọhun ninu, eyii to da wahala silẹ. O ni oun ti kọkọ ṣe ipade pẹlu awọn ti ọrọ naa kan ṣaaju ki oun to gbe igbẹsẹ ọhun. AbdulRazaq tun sọ pe gẹgẹ bii gomina, oun ti bura lati daabo bo awọn eeyan ilu lọwọ wahala ki irufẹ wahala bẹẹ to bẹ silẹ. O fikun pe oun yoo ṣe atunsẹ si igbimọ to n ri si ọrọ naa ti oun ti gbe kalẹ ṣaaju laarin ọjọ diẹ si asiko yii, ki ọrọ naa patapata. Lẹyin naa lo dupẹ lọwọ awọn adari ẹsin Kristẹni ati Musulumi fun akitiyan wọn ki alaafia le jọba niluu Ilorin ati lọwọ awọn agbofinro naa fun ipa ti wọn sa lati pana rogbodiyan to bẹ silẹ ṣaaju. Gomina naa pari ọrọ rẹ pe, ki awọn eeyan ipinlẹ Kwara gbiyanju lati fi imọ ṣokan fun itẹsiwaju ipinlẹ naa lai fi ti ẹya tabi ẹsin ṣe. Awọn olukọ lawọn ile ẹkọ ti ijọba ti pàṣẹ iwọle pada ni ipinlẹ Kwara lori ọrọ wahala lilo Hijab ti pa aṣẹ naa mọ. Nile ẹkọ Baptisti to wa lagbegbe Surulere ti BBC Yoruba ṣabẹwo si, a ri awọn olukọ naa ti wọn ti n pada sẹnu isẹ wọn. Ninu ifọrọwerọ pẹlu awọn olukọ ọhun, wọn ni awọn ko ni nnkan mii lati ṣe bi ko ṣe pe ki wọn tẹle aṣẹ ijoba to gba awọn ṣiṣe. Wamuwamu ni awọn agbofinro wa ni ẹnu ọna abawọle ile ẹkọ Baptist naa, sugbon akẹkọọ meji pere la ri nigba ti a kan sibẹ. Alakoso ile ẹkọ girama Baptist, arabinrin Bamikole Julianah Adedoyin ti a ba sọrọ ni awọn n reti ki awọn akẹkọ yọjú, paapaa awọn to fẹ kọ idanwo asekagba WAEC. O fi kun pe oun ti gbe igbeṣe lati maa pe awọn obi awọn akọkọọ naa ki wọn ma baa padanu iforukọsilẹ idanwo WAEC ọhun. Ko si wahala kankan nigba ti a de ibẹ sugbon awon alaṣẹ ile ẹkọ naa ni awọn eeyan kan ti ja ferese ọọfisi alakoso ile ẹkọ alakọbẹrẹ, ti wọn si ba awọn irinṣẹ kan jẹ. Ijọba ipinlẹ Kwara ti pasẹ pe ki awọn ileẹkọ mẹwa to jẹ ti ẹlẹsin Kristẹni ti ija ti waye lori ọrọ lilo ibori bẹrẹ to ẹkọ kikọ lọgan. Atẹjade kan ti alaga ajọ to n mojuto eto ẹkọ girama nipinlẹ Kwara, Tescom, Mallam Bello Abubakar fisita lo pasẹ bẹẹ fawọn ọga ile ẹkọ ati olukọ to wa lawọn ile ẹkọ mẹwẹẹwa naa. Atẹjade naa ni igbesẹ pipada si kilaasi ni yoo mu ki eto ẹkọ kikọ bẹrẹ loju ẹsẹ, kawọn akẹkọjade to n mura idanwo WAEC le joko se idanwo naa. Bello wa dunkoko pe olukọ ti ko ba yọju sibi isẹ lawọn ile ẹkọ naa loni ọjọ Ẹti rugi oyin, ti yoo si foju wina ofin ijọba nitori awọn ko ni faaye gba iwa aibọwọ fofin. Bakan naa ni atẹjade ọhun tun fewe ọmọ mọ awọn eeyan ti ọrọ naa kan leti lati mase tapa sofin nitori ipade alaafia laarin wọn ati ijọba yoo tẹsiwaju. Bello ni ijọba kabamọ nipa inira ti titi ilẹkun awọn ile ẹkọ naa mu bawọn akẹkọ pẹlu afikun pe ijọba gbe igbesẹ naa nitori ipese alaafia ni. Ẹgbẹ awọn ọmọlẹyin Kristi (CAN) ni ipinlẹ Kwara ti sọ pe bii eeyan marundinlogun lo ṣeṣe lasiko rogbodiyan to waye niluu Ilorin laarin awọn Kristẹni ati Musulumi. Akọwe ẹgbẹ naa nipinlẹ ọhun, alufaa Reuben Idowu Ibitoye, lo sọ ọrọ naa ninu ifọrọwerọ kan pẹlu BBC Yoruba. Rogbodiyan naa ko ṣẹyin ọrọ ti ijọba ipinlẹ naa sọ pe awọn akẹkọọbinrin to jẹ Musulumi le maa lo ijaabu lawọn ile ẹkọ ti ile ijọsin da silẹ. Ibitoye ni ""awọn eeyan to ṣeṣe lọjọru ti isẹlẹ naa waye le ni marundinlogun, koda wọn ṣiṣẹ abẹ fun awọn miran ninu wọn. Lonii ẹwẹ, wọn tun ṣakọlu si awọn miran lagbegbe ECWA, ti wọn si kan awọn eeyan naa lapa ati ni ẹsẹ."" Alufaa naa fikun pe, awọn gẹgẹ bii Kristẹni ko ni ija kankan pẹlu awọn Musulumi, ijọba ipinlẹ Kwara ni awọn ba ni ọrọ. O pari ọrọ rẹ pe o yẹ ki ijọba ṣe ododo lori ọrọ naa, ki wọn ma si ṣe ojuṣaaju ninu idajọ wọn. Nigba to n da si ọrọ naa, Ọjọgbọn O.Y Abdulhameed, to jẹ akọwe awọn ọmọ bibi ilu Ilorin ati ọjọgbọn ni Fasiti Ilorin sọ pe, o yẹ ki gbogbo eeyan niluu Ilorin bọwọ fun ohun ti ofin sọ. O ni ""orilẹ-ede to ni ofin ni Naijiria jẹ nitori naa o yẹ ki gbogbo awọn ti ọrọ yii kan tẹle ohun ti ofin sọ."" Gẹgẹ bo ṣe sọ, ""ofin Naijiria, ori ọgbọn, ẹsẹ ikẹjọ fi aye fun gbogbo ọmọ Naijiria lati darapọ mọ ẹsin to ba wu wọn, bakan naa lo tun fi aye gba wọn lati mura bi ẹsin naa ṣe fi aye gba wọn."" Ọjọgbọn naa sọ fun BBC Yoruba pe, eeyan le mura bi ẹsin rẹ ṣe fi aye gba ni gbogbo ibi to ba jẹ ti ijọba, ti ile ẹkọ naa jẹ ọkan lara rẹ."" Akọwe ọmọ ilu Ilorin ṣalaye siwaju si pe, lootọ awọn ile ijọsin lo da awọn ile ẹkọ naa silẹ, ṣugbọn ijọba ti gba iṣakoso awọn ile ẹkọ ọhun lọwọ awọn ile ijọsin lọdun 1974. O ni ti to ba jẹ pe ijọba lo n ṣagbatẹru awọn ile ẹkọ naa, ijọba nikan lo ni aṣẹ lati sọ bi awọn akẹkọọ ṣe le maa mura lọ sile iwe. Lẹyin naa lo gba awọn eeyan ilu Ilorin nimọran lati fi suuru yanju ọrọ naa, ati pe ki wọn ma gba ọrọ ẹsin laaye lati ba ibagbepọ wọn jẹ. BBC tun kan si agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Kwara, Ajayi Okasanmi Jeffery, to sọ pe awọn ko fi panpẹ ofin mu ẹnikẹni ninu awọn to da rogbodiyan silẹ niluu Ilorin. Bo tilẹ jẹ pe o ni lootọ ni awọn gbọ pe awọn eeyan kan farapa nitori iṣẹlẹ to waye niwaju ile ẹkọ Baptist to wa ni Surulere, ṣugbọn awọn ko le fidi rẹ mulẹ pe ẹnikẹni farapa. O sọ pe ""a gbọ pe wọn fọ awọn kan lori, ṣugbọn awa ko ri ẹnikẹni ti wọn fọ lori tabi to farapa."" Jeffery pari ọrọ rẹ pe awọn ti bẹrẹ iṣẹ lati pana rogbodiyan to n waye niluu Ilorin nitori ọrọ ijaabu ọhun. Ọrọ ti di boolọ o yago fun mi ni ilu Ilọrin laarin awọn Musulumi ati Kristiẹni. Rogbodiyan naa ko ṣẹyin ọrọ lilo ijaabu fun awọn akẹkọọbinrin to jẹ Musulumi, to n kawe nile ẹkọ ti awọn Kristẹni kọ. Aarọ Ọjọru ni awọn Kristẹni bẹrẹ ifẹhonuhan lodi si igbeṣẹ ijọba ipinlẹ ọhun, eyi to faaye gba awọn akẹkọọbirin Musulumi lati maa lo ijaabu nile ẹkọ awọn Kristẹni. Igbesẹ naa ko dun mọ awọn alaṣẹ ile ẹkọ Kristẹni naa ninu, lẹyin ti wọn ti kọkọ sọ ṣaaju pe akẹkọọ yowu to ba fẹ maa kawe nile iwe awọn ko gbọdọ wọ ijaabu. Lowurọ Ọjọru ni awọn ẹlẹsin mejeeji peju siwaju ileewe Baptist Secondary School to wa ni Suurulere, pẹlu iwe ilewọ to ni oriṣiriṣi akọle. Ka to diju ki a to laa, ija ti bẹrẹ laarin awọn ẹlẹsin mejeji ọhun, ti ọlọpaa si yin afẹfẹ tajutaju soke lati tu wọn ka. Awọn Musulumi ati Kristẹni bẹrẹ si n sọ oko sira wọn, eyii to mu awọn agbofinro yin gaasi tajutaju lọna ati pana rogbodiyan ọhun. Titi di asiko ti a n kọ iroyin yii, awọn kristeni ti sa wọ inu ọgba sọọsi onitẹbọmi kan ni Suurulere, ti awọn Musulumi ṣi wa nita nibẹ. Ti ẹ ko ba gbagbe, ọjọ Iṣẹgun ni ijọba ipinlẹ Kwara kede ṣiṣi awọn ile ẹkọ mẹwaa kan ti ọrọ naa kan pada, eyi ti wọn gbe ti pa ṣaaju.",0,yoruba ní láti ṣe áwọn iṣẹ́ tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ẹkọ́: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò.,0,yoruba rere. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Alàji lo tun se joko.,0,yoruba yii nípa àwẹ ọba lo je ti ibile.,0,yoruba "Ọba lọ. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba ẹkọ́: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò.,0,yoruba "Awọn ọmọ iya mẹta kan ni wọn ti di asínjẹ pọnbele lori ikanni ayelujara instagram. Muiz Sanni to dagba jù ninu wọn jẹ ọmọ ọdun mẹrinla nigba ti Fawas Sanni jẹ ọmọ ọdun méwaa ti Malik Sanni to kere julọ ninu wọn jẹ ọmọ ọdun mẹjọ Ẹgbọn wọn agba lo maa n ba wọn dari fidio ti wọn n ya fi sin awọn agbajugbaja oloṣere jẹ lori ayelujara. Muiz ni pe opin ọsẹ ni awọn maa n ya fidio naa ko ma lè pa ẹkọ awọn lara. Ọpọ oju ninu ere oniṣe Naijiria bii Adesuwa, Genevive ati bẹẹ bẹẹ lọ ni wọn ti sin jẹ ti wọn fi sọ ara wọn di adẹrin-poṣonu. Wọn sọ bi wọn ṣe bẹrẹ niwọnba ko to di nla bayii péki onikaluku bẹrẹ ohun to wuu lati ṣe lọdun 2019. Igbesẹ kan naa lo ni lati kọkọ gbv'é, koda ki igbesẹ naa kere. Ilu Ikorodu, nipinlẹ Eko ni Naijiria ni wọn wa.",0,yoruba Korean (_JOHAB),0,yoruba "tí a kọ eḳọ nípa ire àti ìbàdandun, àwọn aláìì wà ní ìṣẹ́ ọ̀pọ́lọ̀.",0,yoruba Ọjọ́ Ajẹ́ rèé o. Ajé á wọgbá fún gbogbo wa. A ó jèrè iṣẹ́ lọ́sẹ̀ yìí lọ́la Olúwa. A ò ní ṣòwò fún ọmọ ẹlòmíì jẹ.,0,yoruba ilẹ̀ agbègbè tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Ọmọ lo mú.,0,yoruba "Olori ìjọba China nigba kan, Jiang Zemin, ti jáde laye lẹni ọdun mẹrindinlọgọrun. Àwọn ileeṣẹ iroyin ijọba ni China sọ pe ọsan Òjọru lo kú. Ipa kekere kọ ni Zemin ko fún ọpọlọpọ ọdún, ninu idagbasoke orile-ede China. Iku rẹ waye lasiko ti orisirisi iwọde alagbara n waye jakejado China, nitori isede COVID-19. Zemin gba ìṣàkóso China lẹyin ìwọ́de to waye ni gbagede Tiananmen Square n'ilu Beijing, eyi to mu ọpọlọpọ ẹ̀mí lọ lọdun 1989. Àwùjọ agbaye si fi iya jẹ China nitori eyi. Iṣẹlẹ naa fà rògbòdìyàn ninu ẹgbẹ́ oṣelu Communist. Nípasẹ̀ rẹ si ni Zemin fi gba igbega si ipo adari China. Saaju iyansipo rẹ, oju ẹni ti ko ja fafa ni wọn fi má n wo Zemin, nitori pe o fẹ́ràn láti má ṣe nkan ni ilana to tọ. Sugbọn wọn yan sípò nítorí ireti pe yoo da ìṣọ̀kan pada. Labẹ isakoso rẹ, ọ̀rọ̀ ajé China l'agbara si, egbẹ́ oselu Communist di ipo agbara mú ṣinṣin, China sì wa ni ipo to yẹ ko wa lori igbelewọn àwọn orile-ede to ni agbara lagbaye.",0,yoruba Biola Fowosere skit: Ọ̀rọ̀ Biola Fowosere ati olùdarí èré n tako ara wọn lórí pé kó wọ aṣọ oníhòhò,0,yoruba Ọkan tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìṣẹ̀: ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò.,0,yoruba ìṣẹ̀: ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni A tí lọ́kìlọ̀ sí ojú onà..,0,yoruba "@user Dada awuru yale, yagi oko Olowo eyo, gbongbo ni ahoro Asiso o lara Otosi o niyekan Dada ogbegun, irunmangala Eran gbigbe o nijanja Aladeleye, abisu jooko Dada ogbegun Mo rade yo obinrin Gbon ori ade Gbo ori esu siwaju Dada ogbegun Gbo ori oro sodo mi",0,yoruba Gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó ṣe pàtàkì. (Item 94),0,yoruba òun tí a ní nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o nuni ti o nuni ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn.,0,yoruba "Lẹyin wakati diẹ ti gbajugbaja osere tiata nni, Babatunde Omidina, ti ọpọ eeyan mọ si Baba Suwe jade laye, awuye wuye ti n su yọ lori oku rẹ. Ni kete ti oloogbe naa mi kanlẹ, ni fidio orisi meji ti n ja rain-rain lori ayelujara eyi to se afihan oku apanilẹrin naa. Ọjọ Aje ni agba osere tiata naa dagbere faye lasiko aisan ọlọ pipẹ to ti n ba finra. Ninu fidio akọkọ, ni ọkunrin apọnbeporẹ kan to pe oloogbe naa ni baba oun, ti se afihan ara rẹ ati oku Baba Suwe ni kete to ku, ti oku rẹ si la ẹnu silẹ. Obinrin naa to di ori oku Baba Suwe mu lo n fi omije sọrọ pe baba oun ti lọ. Ọkunrin naa ni ""Ko si ẹbi, ko si ara, a pe wọn lootọ amọ ko si ẹbi. Baba mi ti lọ, mo maa n nifẹ ọkunrin yii ni gbogbo igba, ẹyin ẹbi mo dupẹ o, ẹ seun o, amọ n ko ni sọ ju bayii lọ."" Fidio keji naa lo fi ara pẹ ti akọkọ, ninu fidio naa si ni wọn ti se afihan oku Baba Suwe lati ori de isalẹ. Oloogbe naa lo sun sori ibusun, o la ẹnu silẹ, ti oju ibi ti wọn lẹ pilasita si wa ni apa mejeeji rẹ. Baba Suwe lo wọ asọ ankara olomi buluu eyi to wọ titi to fi mi kanlẹ, to si sun silẹ laimira bi o tilẹ jẹ pe fidio naa ko ni ohun. Ninu fido naa si lo ti foju han pe Baba Suwe ti ru pupọ ko to jade laye, to si yatọ si Baba Suwe to ni omi lara, eyi ti gbogbo aye mọ. Ọpọ eeyan lo ti n sọ ero ọkan wọn lori awọn fidio mejeeji naa, eyi to n tabuku oloogbe, ti wn si n bu ẹnu atẹ lu ẹni to wa nidi bi fidio naa se de ori ayelujara. Boya ariwisi awọ̀n araalu yii lo mu ki ẹlomiran, to jẹ ọmọ oloogbe naa, Adesola Omidina se kede loju opo ayelujara rẹ lati tako igbesẹ afihan oku baba rẹ lori ayelujara. Ọmọ Omidina @ omo_omidina loju opo Instagram, lo fi atẹjade kan sita pe oun n fi gbogbo ẹnu tabuku awọn fidio mejeeji naa. O ni awọ̀n fidio to n se afihan oku baba oun lawọn oju opo ayelujara ni ko tọna bi wọn se gbe jade rara. Bakan naa lo sẹ lori ẹsun pe awọn ko ri oluranlọwọ kankan lati se itọju oloogbe naa lasiko to wa lori ibusun aisan. O ni ẹgbẹ awọn osere tiata, TAMPAN, ijọba, awọn wolii, ẹbi ati ololufẹ baba oun ni wọn sugba awọn niwọnba bi agbara wọn ti mọ, ti wọn si se iwọn ti wọn le se. Adesola Omidina wa lo anfaani ikede naa lati tọrọ aforijin lọwọ awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ, awọn eeyan ati ẹbi wọn. Ọmọ Baba Suwe naa wa n rọ awọn araalu lati kọ ẹyin si awọn fidio ti ko tọna naa, eyi to ti lu ori ayelujara pa. Nibayii na, ikede ti jade lori eto isinku Baba Suwe. Atẹjade miran ti ọmọ oloogbe, Adesola Omidina fisita loju opo Instagram rẹ ni aarọ ọjọ Isẹgun kede pe Ọjọbọ ni wọn yoo gbe oku oloogbe naa wọ kaa ilẹ. Atẹjade naa ni ile oloogbe to wa ladupo Elepe nilu Ikorodu ni wọn yoo ti sin Baba Suwe ni deede aago mẹwa owurọ. Adesola Omidina ni awọn mọlẹbi oloogbe yoo kede ayẹyẹ isinku nigba to ba ya. Ọjọ Aje, ọjọ Kejilelogun osu Kọkanla ọdun 2021 ni agba osere tiata naa, tii tun se adẹrinposonu ti ọpọ eeyan mọ si Baba Suwe ki aye pe o digbose. Ọdun mẹtalelọgọta ni alawada naa lo loke eepẹ, ko to dagbere faye lasiko aisan ọlọjọ pipẹ to ba finra.",0,yoruba RT @user: 51. gbogbo ètò náà yóò sì ti parí bí a bá ti n bí ọmọ. @user @user @user,0,yoruba "Nitori eyi, ara eni lo ni àṣà yorubá eyti o gbe lori ọ̀run dídì.",0,yoruba iṣẹ́ tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé lọ yóò ni Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..,0,yoruba "Babawo se siọ̀ awọn eeyan to n bu ẹnu atẹ lu igbesẹ rẹ naa lori itakun agbaye Kii kuku se awọn ohun eelo to pin lo n se awọn araalu ni haa-hin, bi ko se irufẹ awọn ohun eelo naa, eyi to n kọ wọn lominu. Lara awọn ohun eelo naa lati ri apoti sobata, burọọṣi inubata, ori inubata, taa mọ si pọliiṣi ati fukẹ́-fukẹ́ inubata, taa mọ̀ si foam, asọ, mọto ati ẹrọ iransọ. Oniruuru awọn eroja apanilẹrin lawọn oloselu maa n pin bii ohun eelo aroni lagbara Taa ba si wo daada, kii se Babawo ni yoo kọ̀kọ̀ pin awọn ẹbun ironi laagbara ti yoo kọ awọn ọmọ Naijiria ni ominu bayii, nitori a ti gbọ nipa awọn oloselu ati awọn gomina kan ti wọn ti kọkọ pin awọn ohun eelo ironi lagbara bii tii alagbada, taa mọ si Lipton tea, eroja Noodles, ẹyin adiẹ, garawa ipọnmi ati ọmọ-lanke ti wọn n pe ni wheel barrow. Bẹẹ ba si gbagbe, gomina ipinlẹ Benue, Samuel Ortom naa ti pin ọmọlanke ri fawọn eeyan ipinlẹ rẹ bii ohun eelo ironi-lagbara, eyiti okiki rẹ gbalẹ kan nigba naa. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Eyi lo wa mu ki BBC Yoruba kan si araalu kan lati beere pe oju wo lo fi wo igbesẹ yii ? N jẹ iwa ipese idẹrun fun araalu ni eyi abi iwa tita abuku wọn. Lero ti Alagba Olu Israel, apa oke ọya ni iwa pinpin awọn ohun eelo ironi lagbara to jẹ kayeefi yii wa, ọna lati jẹ gaba lori awọn araalu si ni. Ẹ gbọ Alagba israel siwaju sii. Èèlò ìróni-lágbára, fún ìdẹ́rùn ni àbí àbùkù Niwọn igba to jẹ pe a gbọ́ ẹjọ ẹnikan da, agba osika ni. Ọna lati mase role apakan, da apakan si, lo mu ki BBC Yoruba kan si Kọmisana to pin apoti sobata naa ni ipinlẹ Borno, Hon Babawo. Babawo ni ko si ohun to buru ninu apoti sobata ti ohun pin Lero tiẹ́, o ni ko si ohun to buru ninu apoti sobata ti ohun pin yii, nitori ohun ti awọn ọdọ naa n fẹ ni eyi, wọn si mọọmọ beere lọwọ ohun ni. Babawo ni miliọnu mẹta naira ni oun na lori ipese awọn eroja sobata naa, fawọn ọdọ yii, ti wọn jẹ ọmọ orukan, ti ogun Boko Haram ti pa awọn obi wọn. Babawo ni miliọnu mẹta naira ni oun na lori ipese awọn eroja sobata Ko sai wa se siọ̀ awọn eeyan to n bu ẹnu atẹ lu igbesẹ rẹ naa lori itakun agbaye, to si ni ailaju lo n da irufẹ awọn eeyan yii laamu nitori awọn eeyan to n so bata gan wa lawọn orilẹede to ti goke agba bii Amerika, canada, ati Gẹẹsi.",0,yoruba dídì yìí ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn yì í tún ṣe àwọn iṣẹ́ tí ọ̀pọ́lọ̀ àti àlàáfíà.,0,yoruba ìyá ọ̀ṣun kú ọjọ́ mẹ́ta o,0,yoruba "Olùwo fi. Nitori eyi, ara eni lo ni ìgbà mi owó àkokò, Ọba ri Eyii ni àkóbì ti yoò ronú lọ́rọ̀..",0,yoruba ni a ní nípa ire àti ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn ènìyàn ni ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa aráyé: ti o ní wúlò fún gbogbo àwọn aráyé lẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ àti ìbi.,0,yoruba "#AwonAdojutiYoruba 👇Ishola Oyenusi inagijẹ 'Dr. Ishola'. Ogbologbo adigunjale ti ofi oju awon ara ilu eko ri emo ni odun 1970. Oyenusi ko si pampe @user ni odun 1971, leyin ti oti di eni awati fun ololopo odun. ijoba ologun keyin Oyenusi si agba ni, osu kesan ni odun 1971 https://t.co/2kMTROPAGL",0,yoruba "Eyi ni ọrọ to ti ẹnu aarẹ orilẹede yii, Muhammadu Buhari jade lasiko to n gbalejo awọn eekan ọmọbibi ipinlẹ Ogun, to fi mọ gomina wọn, Dapọ Abiọdun ati igbakeji rẹ, Noimot Salakọ, eyi to waye nile ijọba nilu Abuja. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Lara awọn eekan miran lati ipinlẹ Ogun to se abẹwo si aarẹ Buhari ni arẹmọ oloogbe MKO Abiọla, Kọla Abiọla, ọmọ Abiọla obinrin, Hafzat Abiọla, gomina tẹlẹ nipinlẹ Ogun, Oloye Olusẹgun Ọsọba, awọn ọba alaye ati awọn eeyan jankanjankan miran. Buhari, lasiko to n gbalejo awọn eeyan yii ni Abiọla ati igbakeji rẹ ti wọn dijọ dije, ni wọn jẹ Musulumi, bẹẹ ni aawọ ẹsin tabi ti ẹyako ba ti waye, nitori Kanuri ni ẹni to dije bii igbakeji Abiọla, ti oun naa si jẹ ilumọọka yika Naijiria. O fikun pe Abiọla lo awọn ohun alumọsni ti ọba oke fi jinki rẹ ati gbogbo agbara to ni lati fi gba awọn ọmọ Naijiria niyanju pe ohun kan soso ti oun n fẹ ni orilẹede Naijiria ti yoo duro digbi, ko si si ohunkohun miran ti oun n wa. Buhari salaye pe oun mọọmọ fi papa isere idaraya ilẹ wa sọri oloye MKO Abiọla ni, nitori oun nigbagbọ pe awọn ọdọ lọjọ ọla, yoo fẹ mọ idi ti wọn se fi papa isere nla naa sọri MKO Abiọla. Nigba to n ki aarẹ, gomina ipinlẹ Ogun, Dapọ Abiọdun ni awọn eekan ọmọ bibi ipinlẹ Ogun tọ Buhari wa, lati wa dupẹ lọwọ rẹ, fun iyi ati ẹyẹ to fun Abiọla nitori ẹni ta se loore, ti ko dupẹ, bi ọlọsa ko ni lẹru lọ ni.",0,yoruba "ni ó pa Ọba lo ni Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé se yóò ni Nitori eyi, ara eni lo ni ẹ̀ká àwẹ eyti o gbe lori iwa rere.",0,yoruba Àkójú ọ̀rọ̀ yi kún fún àwọn ìṣẹ́ tí ó jáde sí ara ilẹ̀. (Item 123),0,yoruba "Ni kete to le awọn agbofinro naa jinna lo paṣẹ pe kawọn kọngila wa bẹrẹ atunṣe ileegbimọ naa. Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀ Gomina Ọbaseki ṣalaye fun BBC News latẹnu agbẹnusọ rẹ, Crusoe Osagie pe awọn alagbara oloṣelu kan pẹlu gomina ipinlẹ kan lorilẹede Naijiria ni wọn gbimọ pọ lati fẹ fi tipa gba ileegbimọ aṣofin ipinlẹ Edo ki wọn lee da rugudu silẹ ṣaaju idibo gomina to fẹ waye nibẹ lọjọ kọkandinlogun oṣu kẹsan ọdun 2020. Gẹgẹ bi gomina ipinlẹ Edo ṣe sọ, ""Adams Oshiomhole atawọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC kan, pẹlu gomina Hope Uzodinma lo wa nidi iṣẹlẹ naa. Wọn fẹ fi tipatipa gba akoso ile igbimọ aṣofin ipinlẹ naa eleyii ti wọn n tun ṣe lọwọlọwọ. A gbọ pe wọn lọ rọ ayederu ọpa aṣẹ ile naa eyi ti wọn fi fẹ ya bo ile igbimọ aṣofin ti ko si lẹnu iṣẹ bayii nitori atunṣe to n lọ lọwọ nibẹ, lati gbọna ti ko tọ ṣe agbekalẹ ileegbimọ aṣofin miran lowurọ Ọjọbọ. Gomina ipinlẹ Edo, olori ile aṣofin nibẹ, igbakeji olori ile aṣofin ipinlẹ naa wa ni ileegbimọ aṣofin naa lati ba igbesẹ naa jẹ. Kìí ṣe ọmọbìnrin nìkan ni Ọlọ́run pàṣẹ fún láti pa ìbálé mọ́ Fun oṣu meji bayii inu gbọngan ipade nla to wa ni ileegbimọ aṣofin naa lawọn ọmọ ileegbimọ aṣofin ipinlẹ naa ti n ṣe ipade wọn. Agbẹnusọ fun gomina ipinlẹ Edo, ọgbẹni Crusoe Osagie fi ẹsun kan gomina ana ni ipinlẹ naa, Adams Oshiomhole to tun jẹ alaga ana fun ẹgbẹ oselu APC lo n gbiyanju lati fi ipa gba ile aṣofin naa. Gómìnà Obaseki àtàwọn Ọlọ́pàá tó gbàkóso ílé Aṣòfin Edo forígbárí Ohun taa gbọ ni wi pe Gomina ipinlẹ Edo Godwin Obaseki ati igbakeji rẹ ti lọ tu awọn ọlọpaa to duro gbagba si ẹnu ọna ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Edo ti wọn si n gbiyanju ati fi tipa tikuuku wọle. Obitibiti ọlọpaa lo pejọpọ si Ile Igbimọ Aṣofin ipinlẹ Edo to wa ni ilu Benin. Awọn ọlọpaa naa yabo ile igbimọ aṣofin naa pẹlu ọkọ wọn, ti wọn si duro wamuwamu sibẹ. Eleyii n waye lẹyin wakati diẹ ti awọn aṣofin ipinlẹ naa yọ igbakeji abẹnugan ile igbimọ aṣofin ipinlẹ naa. Igbakeji Kọmisọnna ọlọpaa ni ipinlẹ Edo, Ayoola Ajala lo dari awọn ọlọpaa naa. Ẹgbẹ oṣelu PDP loju opo Twitter ni ẹgbẹ oṣelu APC n lọ awọn ọlọpaa naa lati da ẹru ati ipaya silẹ ni ilu naa nitori Gomina Obaseki n gbajumọ si nipinlẹ naa. Bí Ẹ̀ka aláṣẹ́ ti já agbára gbà mọ́ ìgbìmọ̀ olùdarí APC lọ́wọ́ ""Aug 2018 ni ìgbìmọ̀ aláṣẹ APC ti ṣe ìpàdé kẹ́yìn, Oshiomole ti kùnà"" Àwọn gómìnà lábẹ́ àsía ẹgbẹ́ òṣẹ̀lú All Progressive Congress (APC) tí kési alága ẹgbẹ́ òṣèlú APC, Adams Oshiomole lati pe ipade igbimọ alakoso ẹgbẹ́ tàbi kó kọ̀wé fipò sílẹ̀. Awọn gómìnà naa sàlàyé pé, bi alága apapọ ẹgbẹ kò se lee pe àwọn àgbàgbà ẹgbẹ́ sí ìpàdé, ti n mú idàrúdàpọ̀ bá ètò ẹgbẹ́. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Oludari agba fun ẹgbẹ́ àwọn gomina, Salihu Lukman, lo kede bẹẹ nínú àtẹjáde kan to fọwọsí lọjọru nílùú Abuja. Àtẹjáde náà ni "" kò sí ohunkohun miran, to ba ti yàto si ìpàdé ẹlẹgbẹ́jẹgbẹ́ tàbi ìpáde àpérò gbogboogbo, to lee parí ǹkan to ti dàrú nínú ètò ẹgbẹ́"" ""O sàn kí Oshiomhole bìkítà fún ilana ẹgbẹ́ to wa nínú iwe ofin ẹgbẹ́, láti pe ìpade àwọn èèkàn ẹgbẹ ki wọn lee sọ̀rọ̀ lórí gbogbo kùdìẹ̀kudiẹ̀ to n ba ẹgbẹ́ APC fínra, tàbi ko gba pé òun ko kunju òṣùwọ̀n láti tukọ ẹgbẹ̀, ko sì kọ̀wé fipò sílẹ̀."" Lukman sàlàyé pé, o pọ̀ndandan ki Oshiomole kọwe fipo rẹ silẹ, paapaa pẹ̀lú ìròyìn to n jáde láti ìpínlẹ̀ Edo pé, àwọn oloye ẹgbẹ̀ APC ti díbò ""a ò ní ìgbàgbọ́ nínú rẹ̀"" fun Oshiomhole. ""Dipo ka gbajumọ ọna ti APC yoo fi bori ninu awọn eto idibo to wa nilẹ, n se la n foju tẹnbẹlu ara wa. Gbogbo awọn ami buruku yii to waye ni ipinlẹ Zamfara, Rivers, Bauchi ati Adamawa lo tun fẹ suyọ abyi ni Bayelsa."" Lukman fikun pe o se ni laanu pe igbimọ alakoso ẹgbẹ to yẹ ko wa ojutu sawọn isoro yii lo fẹ dabi eyi ti wọn ti so rọ. Osu kẹjọ ọdun 2018 ni wọn ti se ipade kẹyin, ti ẹka alasẹ to yẹ ko maa se amusẹ ipinnu ti igbimọ alakoso ba se, ti wa ja agbara gba mọ igbimọ alakoso ẹgbẹ lọwọ. Edo APC vs Oshiomole: Ẹ̀kà ìpínlẹ̀ tàbí ìjọba ìbílẹ̀ kò láṣẹ láti yọ alága àpapọ̀ ẹgbẹ́ Ọpọ onwoye gbagbọ pe omi n bẹ lamu fun Oshiomole lori iṣọkan ẹgbẹ oṣelu naa Ẹgbẹ oṣelu APC ti bẹnu atẹ lu igbesẹ awọn ọmọ ẹgbẹ naa kan ni ipinlẹ Edo, ti wọn lawọn paṣẹ lo fidimọle fun alaga ẹgbẹ naa lapapọ, Adams Oshiomole. Idahun yii n waye nitori bi ẹka ẹgbẹ naa nilu Benin ṣe ni oun ko ni igbagbọ mọ ninu alaga ẹgbẹ nipinlẹ ati alaga apapọ ẹgbẹ naa. Yakubu Nabena, to jẹ igbakeji akọwe ipolongo ẹgbẹ APC ṣalaye fun ikọ BBC pe, igbesẹ to yẹ kọ ni awọn to paṣẹ lọ gbele rẹ fun Oshiomole tẹle. O ni ''alawada lawọn to gbe iru igbesẹ yii'' nitori pe wọn ko laṣẹ lati paṣẹ lọ fidimọle fun alaga ẹgbẹ lapapọ. Ohun ti wọn ṣe ko mu ọgbọn wa rara. Wọn ni lati mọ nnkan ti ofin ẹgbẹ sọ ki wọn to gbe iru igbesẹ bẹẹ'' O wa ṣalaye pe, awọn igbesẹ kan wa labẹ ofin ẹgbẹ ti eeyan gbọdọ ṣe, ki o to le ni oun fẹ yọ alaga ẹgbẹ lapapọ ''Ni ipele nipele ni ohun gbogbo wa ninu eto. Ki eeyan to le yọ alaga ẹgbẹ lapapọ tabi ki wọn to le kọwe lọ joko sile fun-un, igbimọ alaṣẹ ẹgbẹ lo le se bẹẹ.'' Ohun ta ti jabọ ṣaaju lori ọrọ yii Nkan ko ṣebi ẹni rọgbọ falaga ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress APC, Adams Oshiomole pẹlu bi awọn ọmọ ẹgbẹ naa kan ni ipinlẹ Edo ṣe lawọn jawe lọ rọọkun nile fun un. Lọjọ Iṣẹgun niroyin gbori afẹfẹ kankan lẹyin ti ẹka ẹgbẹ naa ni Benin tii ṣe olu ilu Edo kede pe awọn jawe lọ rọọkun n'le falaga ẹgbẹ naa ni ipinlẹ ohuin, Anselm Ojezua. Ko pẹ si igba naa ni ikede miran wa lati ile ijọba pe wọn ti yọ akọwe ẹgbẹ naa ati pe wọn tun kọwe lọ fidimọlẹ fun alaga ẹgbẹ naa lapapọ Adams Oshiomole. Titi di bi a ti ṣe n ṣe akojọpọ iroyin yii, Adams Oshiomole tabi alaṣẹ ẹgbẹ naa kankan loke ko tii fesi si igbesẹ yi. Lẹnu ọjọ mẹta yii ni fa ki n fa ti n waye laarin Gomina ipinlẹ Edo, Godwin Obaseki ati Adams Oshiomole. Toun ti bi awọn agbagba ẹgbẹ naa ti ṣe gbiyanju lati dẹkun aigbọraẹniye laarin wọn,iṣẹlẹ to ṣẹlẹ yi n ṣafihan pe nnkan ko rọgbọ ni ipinlẹ naa falaga ẹgbẹ APC. Awọn alaga kan ni digbi lawọn wa lẹyin Oshiomole Bi awọn kan ti ṣe ni awọn ko fẹ ri imi Oshiomole lakitan mọ lawọn agbarijọpọ alaga ijọba ibilẹ kan sọ pe gbọingbọin lawọn wa lẹyin rẹ. Gẹgẹ bi ohun ta ri ka ninu iwe iroyin Naijiria kan,atẹjade kan tawọn alaga Etsako West,Etsako Central fi sita sọ pe ''awa ni alaga ijọba ibilẹ mẹrindinlogun a o si mọ nipa ipade to waye nibi ti wọn ti kọwe akoniigbagbọ ninu rẹ mọ fun alaga ẹgbẹ wa Adams Oshiomole'' Wọn tẹsiwaju pe dipo Oshiomole,Gomina Godwin Obaseki lawọn ko ni igbagbọ ninu rẹ ati alaga ẹgbẹ APC ni ipinlẹ Edo,Anselm Ojezua. Wọn wa tẹnumọ pe Oshiomole ṣi ni alaga olori awọn ati pe ''wamuwamu lawọn wa lẹyin rẹ''",0,yoruba "ojú. Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba ìbàdandun ìlú. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tó gbogbo àwọn ènìyàn ni ó pa Bàbá lo ìgbà ọkọ.,0,yoruba "Sugbọn awọn ọrọ ti Alaafin sọ lasiko ayẹyẹ ọdun Sango naa si n ja rain-rain nilẹ. Ọba Adeyẹmi, lasiko to n sọrọ salaye pe awọn alalẹ ati iran to n bọ lọjọ iwaju ko ni forijin oun, ti oun ba kọ lati maa se ajọdun Sango lọdọọdun, gẹgẹ bii ọkan lara awọn ọba to ti jẹ ri nilu Ọyọ. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Alaafin wa kesi awọn ọba alaye yoku nilẹ Yoruba lati maa gbe awọn asa ajogunba wa, ede, ati ise Yoruba larugẹ, ni gbogbo ilu ti wọn ba jọba le lori. Bakan naa ni Ọba Adeyẹmi tun rọ awọn ọmọ Kaarọ Oojire lati maa fi asa ati ise wa kọ awọn ọmọ wa nitori orisa ti a ko ba fi oju ọmọde mọ, ko ni pẹ parun. ""Iyatọ nla wa laarin ẹsin ati asa, ẹ mase jẹ ki oju ti yin lati maa wọ awọn asọ ajogunba Yoruba, koda asa wa gan gbọdọ fara han ninu awọn ounjẹ ta n jẹ"" Oriade naa wa daba pe kawọn eeyan maa kọ awọn ogo wẹkrẹ wa ni ede abinibi ninu ile ati nile iwe.",0,yoruba "Ìyá se. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò lè mọ ohun tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Ní báyìí, iṣẹ́ yi padà si ìlú..",0,yoruba "Kemi Afolabi: kíni lupus?, kí ló le fàá?, àmì àti ìtọ́jú rẹ̀ rèé",0,yoruba wá lẹ̀ẹ̀ní nípa ìròyìn tí ó jáde wá lẹ̀ẹ̀ní nípa aráyé: ti o nuni ti o ṣe pataki.,0,yoruba Wọ́n ti iléèwòsàn pa nítorí àwọn àlùjànú tó n fi ipá bá àwọn nọ́ọ́sì lòpọ̀,0,yoruba "eyi, ara eni lo je gbogbo ise ibile tèmi.",0,yoruba owo ṣẹlẹ ni Lagos ti gbogbo eniyan sọ o ṣe pataki. (1997),0,yoruba "Ọkùnrin náà fi ojú ibi tí yóò ti bẹ̀rẹ̀ ìwalẹ̀ , ó sì tún sọ fún un pé lórí iṣẹ́ ìwalẹ̀ náà ni yóò ti là .",0,yoruba "Ilẹ ti ta si ti aigbọraẹniye ti n waye laarin ẹka alasẹ ati awọn asofin lorilẹede Naijiria Awọn asofin naa, lai naani pe ile ti tẹwọgba abọ igbimọ ọhun ni, awọn yoo ri daju pe ile pa ohunda lori ipinnu rẹ yi. Wọn ni afojusun atunse ofin idibo naa ni wọn se nitori aarẹ Muhammadu Buhari. Aarẹ ile asofin agba, dokita Bukọla Saraki lo kesi awọn asofin lati dibo lori abọ naa, lati mọ boya wọn faramọ tabi wọn ko faramọ, lẹyin ti alaga igbimọ ọhun, Sẹnatọ Sulaiman Nazif, ti gbe abọ igbimọ rẹ kalẹ tan. Ohun ti awọn asofin naa n binu le lori. Awọn asofin to n binu ni atunse ofin idibo ọhun n na ika atako si Aarẹ Muhammadu Buhari. Awọn asofin to dibo pe awọn faramọ abọ naa pọ ju awọn to dibo pe awọn ko faramọ lọ, ti aarẹ ile si fontẹ lu abọ ọhun, eyi to mu ki ariwo sọ. Bakannaa ni Bukọla Saraki tun kọ lati gba awọn asofin to nawọ soke lati sọrọ tako idibo ọhun laaye lati wi tẹnu wọn.",0,yoruba Ìtàn iwájú,0,yoruba "COVID - 19 : Ìyàwó ààrẹ Buhari pín àwọn ohun ilé - ìwòsàn Ìyàwó ààrẹ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà , ìyáàfin Aisha Buhari ti pín àwọn ohun èlò ilé - ìwòsàn fún ìrànwọ́ láti gbógun ti ìtànkálẹ̀ ààrùn Corona ìyẹn COVID - 19 .",0,yoruba ní ilẹ̀ẹ yorùbá a ní oríṣi ọ̀nà tí à ń gbà tọ́jú oúnjẹ di ọjọ́ pípẹ́ a má ń lo iyọ̀ oòrùn a sì tún ń yan oúnjẹ lórí àrò,0,yoruba "ìbàdandun wa dé jáde nípa àwọn ènìyàn: ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí ó tìkẹ́ gbé fi yóò ni Nitori eyi, ara eni yi ojú òní..",0,yoruba ipilẹ̀ ti o ní wúlò fún àwọn ìṣẹ́ tí ó ṣe pàtàkì.,0,yoruba iṣẹ́ tí ó jáde lẹ̀ẹ̀ní nípa ìwà: ti o ní wúlò fún àwọn ìkòkò tí.,0,yoruba