raw_text
stringlengths
2
128k
joseph wayas joseph wayas tí wọ́n bí ní 21 may 1941 tó sì dágbére fáyé ní 30 november 2021 fìgbà kan jẹ́ olórí ilé-ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà tí orílẹ́-èdè nàìjíríà lásìkò tí nàìjíríà gba òmìnira lọ́wọ́ ìjọba ológun19791983 ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ ayé rẹ̀ wọ́n bí wayas ní basang obudu ìpínlẹ̀ cross river ní 21st may 1941 ó sì kẹ́kọ̀ọ́ jáde ní dennis memorial grammar school ní onitsha ó lọ́ sí òkè-òkun níbi tí ó ti kẹ́kọ̀ọ́ gboyè ní higher tottenham technical college london the west bronwich college of commerce science and technology birmingham and aston university birmingham nígbà tí ó padà dé orílẹ́-èdẹ̀ nàìjíríà ó ṣiṣẹ́ gẹ́gé bí i alámòójútó àti olùdarí láàárín ọdún 1960-1969 fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ilé-iṣé ní orílẹ́-èdè nàìjíríà àti òkè-òkun
paul eyefian paul o eyefian je oniwaasu naijiria to n dunnu nigbagbogbo o je oluso-aguntan ogba adari ni idapo jccf fellowship alakoso nifes fellowship ati alaga ti igbimo idibo olominira omo ile-iwe paul eyefian wa labe adari archbishop dr v e arikoro jp ati pe o je oluso-aguntan ti a yan sipo ni ijo pentecostal african church ni warri ipinle delta naijiria ni osu kerin ojo 27 odun 2023 opinion naijiria royin pe paul eyefian ti so pe awon kristiani yo ki o di a mobile ijo ati kristiani yo ki won sin olorun daradara ninu ohun gbogbo ti won awon itokasi yi ni a kukuru article jọwọ mu yi
mc casino lawre osarenkhoe tí orúkọ gbajúgbajà rẹ̀ ń jẹ́ mc casino jẹ́ apanilérìn-ín ọmọ orílẹ̀-èdè nàìjíríà ó di gbajúgbajà látàri pé ó jé aṣojú àṣà tó sì ń gbe lárugẹ apanilẹ́rìn-ín náà kúndùn láti máa fi àwọn fọ́nrán rẹ̀ pa àwọn ènìyàn lẹ́rìn-ín ètò ẹ̀kọ́ rẹ̀ ilé-ẹ̀kọ́ university of benin uniben ni ó ti kékọ̀ọ́ gboyè nínú ẹ̀kọ́ nípa ẹja nígbà náà òun ni wọ́n yàn gẹ́gẹ́ bí i igbá kejì ààrẹ aṣojú àwọn akẹ́kọ̀ó ní uniben iṣẹ́ rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí i igbá kejì ààrẹ aṣojú àwọn akẹ́kọ̀ó ní uniben mc casino bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ìpànìyànlẹ́rìn-ín látàri fífi ìṣẹ̀lẹ̀ tó ń lọ ní ilé-ìwé ṣe eré ní ọdún 2008 ọdún 2022 ni ó ṣe eré àkọ́kọ́ rẹ̀ ní august 2022 ó rin ìrìn-àjò lọ sí europe fún iṣé láti lọ pa àwọn ọmọ orílẹ́-èdè nàìjíríà tó ń gbé ní òkè-òkun lérìn-ín pẹ̀lú àwon àwàdà rẹ̀ ó ṣiṣé pẹ̀lú àwọn apanilérìn-ín mìíràn ní ayẹyẹ kan ní benin crown height pavilion event center
charles okocha charles okocha tí àwọn ènìyàn mọ̀ sí igwe 2pac jẹ́ òṣèrékùnrin orílẹ́-èdè nàìjíríà tó gbajúmọ̀ fún ṣiṣe ẹ̀dá-ìtàn ọmọ burúkú nínú eré charles okocha jé ọ̀kan lára àwọn àwòkọ́ṣe fún 'idea challenge èyí tí nigeria billionaires network gbé kalẹ̀ ó gbégbá orókè nínú ìdíje ti vskit voice ní ọdún 2019 ìgbésí ayé rẹ̀ ní ọdún 2019 ọlọ́pàá kan ṣèṣì yìnbọ fun èyí sì mu kí ó lọ fún iṣé abẹ ní òkè òkun àríyànjiyàn fọ́nrán kan tàn ká lórí ayélujára tó múnú bí àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ wọ́n fẹ̀sùn kan òṣèrékùnrin yìí pé ó ba ọkọ̀ ọ̀rẹ́ rẹ̀ jẹ́ tí ó sì ń fa ọmọ ọ̀rẹ́ náà sínú ọkọ ìmíì charles okocha yanjú ọ̀rọ̀ náà ó sì ṣàlàyé pé fọ́nrán náà jẹ́ àgékúrú fíìmù kan tí ó ṣe
kunle ajayi kunle ajayi june 16 1964 jẹ́ olórin ẹ̀mí ilẹ̀ nàìjíríà ó jẹ́ olòkọrin olùnfọn dùùrú olùwàásù lórí ẹ̀rọ amóhùnmáwọ̀rán àti olùdarí akọrin ti ìjọ oníràpadàredeemed christian church of god
kingsley okonkwo kingsley okonkwo tí wọ́n bí ní ọjọ́ kọkàndínlọ́gbọ̀n oṣù kìíní ọdún 1976 jẹ́ olùṣọ́-àgùntàn olùdámọ̀ràn àti òǹkọ̀wé ọmọ orílẹ̀-èdè nàìjíríà òun ni olùdásílẹ̀ àti olùṣọ́-àgùntàn ti ìjọ david's christian centre ó sì tún jẹ́ olùṣèdásílẹ̀ ìpérò tó jẹ́ mọ́ ọ̀rọ̀ ìfẹ́ ìbáṣepọ̀ àti ìgbéyàwó èyí tó máa ń wáyé ní oṣooṣù
jerry eze jerry uchechukwu eze tí a bí ní ọjó̩ kejìlélógún oṣù kẹjọ ọdun 1982 jẹ́ olùṣọ-àgùntànìjọ kan ní orílẹ̀-èdè nàìjíríà eze jẹ́ olùdásílẹ̀ streams of joy international àti olùdarí new season prophetic prayer and declaration nsppd at̀i ìpàdé orí afẹ́fẹ́
chukwuemeka cyril ohanaemere chukwuemeka cyril ohanaemere tí wọ́n bí 9 september 1982 tí gbogbo ènìyàn mọ̀ sí odùméje jẹ́ àlùfáà ọmọ orílẹ̀-èdè naijiria gẹ́gẹ́ bi i alábòójútó gbogboogbò ti the mountain of holy ghost intervention and deliverance ministryàti olórin ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ àti ìgbésí ayé rẹ̀ odùméje ni a bí ní ìpínlẹ̀ anámbra ní orílẹ̀-èdè nàìjíríà sínú ìdílé ọlọ́mọ mẹ́fà gẹ́gẹ́ bí ọmọ kẹta ti ọ̀gbẹ́ni àti ìyáàfin pius ohanaemere ó dàgbà soke hustling lati ṣe awọn opin pade gẹgẹ bi fere gbogbo eniyan lati rẹ ẹya ṣaájú kí ó tó di òjíṣẹ́ ọlọ́run odùméje ni awọn ọjọ irẹlẹ rẹ gẹgẹ bi oluyaworan alawọ kan ti o tiraka ni opopona ti ilu onitsha ti o kunju ti o si kunju ni ipinlẹ anambra ó lọ sí ile-iwe girama rẹ̀ ní ilé-ìwé secondary providence lẹ́hìn ètò ẹ̀kọ́ alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ rẹ̀ ní nweje ó fẹ́ láti lọ síwájú ṣùgbọ́n ó lọ sínú ìdókòwò alawọ kan nitori awọn idiwọ owo nibiti o ti kọkọ ṣiṣẹ gẹgẹbi oṣiṣẹ iṣẹ́ ìsìn awọn ọna iwosan ti odumeje sọ fun un ni oyè aguntan gídígbò odumeje ni ija pelu alabagbepo obinrin kan tele ti a mo si ada jesu ti o fi esun pe wolii eke ati charlatan ti o n se akoso ise iyanu nigbati a ṣe apejuwe rẹ gẹgẹbi “oluṣe ere ti o ni owo-owo” o sọ pe awọn apanirun rẹ jẹ alariwo ni oṣu kẹta ọdun 2022 ile ijọsin rẹ ni a mọ gẹgẹ bi ọkan ninu awọn ile ti n ṣe idiwọ awọn ikanni idominugere ni okpoko onitsha ati pe apakan kan ti ile ijọsin ti wó lulẹ gomina ti ipinle anambra ojogbon charles chukwuma soludo ti ṣe ileri lati ko awọn ikanni ti o wa ni idominugere lati ṣayẹwo awọn iṣan omi ni agbegbe naa awọn oṣiṣẹ ijọba ti o wa fun adaṣe ikọlu naa ni wọn ṣe lọwọ rẹ bi o ti n gbiyanju lati da wọn duro lati ṣe iṣẹ abẹ naa sugbon sa gomina soludo fesi si isele naa nipa seleri lati ba awon ti won mu odumeje lowo o si tun kilo wipe ki pasito naa setan lati ru owo idalenu niwon igba ti won fun un ni akiyesi to peye ki ere idaraya naa to waye ọrọ aye rẹ odumeje fẹ arabinrin to n jẹ uju ohanaemere
alhaji yahaya madawaki alhaji yahaya madawaki mfr obe dll oloye ti king george vi da lọ́lá ni oṣù kiini 1907 títí di ojo karùn-ún osu kẹfà 1998 jẹ́ gbajúmò òṣèlú orile-ede naijiria o ti fi igbakan je minisita fun ètò ilera madawaki ti ilorin ati atunluse ti erin-ile ni ìpínlẹ̀ kwara
augustine ukattah augustine ukattah tí wọ́n bí ní august 281918 tó sì ṣaláìsí ní january 271996 je oluko ile naijiria ati oloselu ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ ayé rẹ̀ wọ́n bí augustine echewodor ukattah ní ahaba-oloko ní agbègbè ìjọba ìbílẹ̀ ikwuano ní ìpínlẹ̀ ábíá ní august 28 1918 ukattah jẹ́ ọmọkùnrin kẹrin tí ukattah nkor abajuo àti ejighiato nwamgbede ukattah bí àwọn òbí rẹ̀ méjèèjì jẹ́ ahaba-oloko bàbá rè kú nígbà tó ṣì kéré tí ó sì ń gbé lọ́dọ̀ àbúrò bàbá rè ìyẹn chief mathew ugoani ilé-ìwé alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ christ the king ní aba ló lọ àti ilé-ìwé st theresa ní okigwe lẹ́yìn iṣẹ́ rẹ̀ gẹ́gé bí olùkọ́ àwọn akẹ́kọ̀ó ó lọ sí st charles teacher training college ní onitsha ní ọdún 1941 ó yege gẹ́gẹ́ bí i higher elementary teacher ní ọdún 1944 ó sì ṣàṣeyege nínú ìdànwó ti àwọn olùkọ́ àgbà nínú ẹ̀kọ́ ìtà ní ọdún1948
aminu tambuwal aminu waziri tambuwal tí a bí ní ọjó kẹ̀wá ọdún 1966 o jẹ́ amòfin àti olóṣèlú ó ṣojú ẹkùn gúsù sókótó gẹ́gẹ bí asofin ni odun 2023 o sin gege bi gomina ipinle sokoto lati ọdun 2015 si 2023 o je ọmọ egbe oselu peoples democratic party leyin èyí o sin gege bi agbenuso kejila fun ile igbinmo asojusofin nàìjíríà lati odun 2011 si 2015
lazarus muoka lazarus muoka jé òlùsóagutan ní orilede naijiria ajihinrere pelu òǹkọ̀wé o je oludasile ati oludari fun the lord’s chosen charismatic revival movement ìgbésí ayé rẹ̀ àti iṣẹ́ tó yàn láàyò wọ́n bí lazarus muoka sínú ìdílé catholic ní umuhu-okabia tó wà ní orsu lga ti orlu zone ní ìpínlẹ̀ ímò níbi tí ó ti lọ parí ẹ̀kọ́ alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ àti ti girama ní ọdun 1975 ó kó wá sí ìpínlẹ̀ èkó ó sì ṣiṣẹ́ fún ìgbà díẹ̀ ní ilé-iṣẹ́ kan kí ó tó bèrè ìdókòwò rẹ̀ tí ó ṣe títí ó fi fi ayé rẹ̀ fún kristi gẹ́gẹ́ bí i kìrìsìtẹ́ẹ́nì pípé
timothy oluwole obadare timothy oluwole obadare tí wọ́n bí ní oṣù kẹrin 1930 tí ó sì papòdà ní oṣù kẹta 2013je ajinhinrere am ohun mú àwòrán ni ìlù nàìjíríà àti ajinhinrere gbogbogbo ìjọ kristi àpọ́sítélì cac ìgbésí ayé ìbẹ̀rẹ̀ ọbadare ni a bi ni ileṣa báyìí apakan ti ipinle osun guusu iwọ-oorun nàìjíríà david ati felicia ọbadare olùsọ agutan ati oniṣowo kekere lẹsẹsẹ the majority of documents date obadare's birth to 1930 pupọ julọ awọn iwe aṣẹ ni ọjọ ibi ọbadare si ọdun 1930
chris kwakpovwe chris kwakpovwe tí a bí ní ọjọ́ meédoògún oṣù kọkànlá ọdún 1961 jẹ́ ìránṣẹ́ onígbàgbò akọ́ṣẹmọṣẹ́ onìwósán elégbòogi ati onkọwe oun ni oludasile ati oluso-aguntan agba ti manna prayer mountain mpm ministry worldwide ti o wa ni ilu eko o tun jẹ onkọwe ti manna ojoojumọ wa olufọkansin ojoojumọ chris kwakpovwe ni a bi si idile stephen kasoro kwakpovwe olukọ ti fẹyìntì lati ughelli ipinle delta ati theresa kwakpovwe o ni igba ewe ati eto-ẹkọ alakọbẹrẹ rẹ ni ughelli o te siwaju si government college ughelli delta state re ile-iwe giga ni ọdun 1978 o gba iwe-ẹkọ iwe-ẹkọ giga ti ile-ẹkọ giga ti ife eyiti o jẹ obafemi awolowo university lati kọ ẹkọ ile-iwosan ati pe o gba oye akọkọ ni ọdun 1983 ni ọdun 1999 o gba phd rẹ ninu ẹkọ ẹkọ ẹkọ o fun ni alefa oye oye oye oye ni ẹkọ nipa ẹkọ nipa ẹkọ calvary ni ifowosowopo pẹlu ile-ẹkọ giga christian lighthouse brooklyn
augustine ukattah
godman akinlabi godman akinlabi tí wọ́n bí ní 28 december 1974 jẹ́ olùṣọ́-àgùntàn ti orílẹ̀-èdè nàìjíríà ó sì tún jé òǹkọ̀wé asọ̀rọ̀-ní-gbangba àti onímọ̀-ẹ̀rọ òun ni olùdarí ìjọ the elevation church ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ àti ètò ẹ̀kọ́ rẹ̀ wọ́n bí godman akinlabi ní december 28 1974 ìlú igbo-ora ní ìpínlẹ̀ ọ̀yọ́ ló ti wá ìyẹn ní apá ìwọ̀-oòrùn ilẹ̀ nàìjíríà ìlú ìbàdàn ló dàgbà sí ó sì lọ sí ilé-ìwé government college ibadan ní ìpínlẹ̀ ọ̀yọ́ níorílẹ́-èdè nàìjíríà láti ọdún 1985 wọ 1990 ní ọdún 1992 wọ́n gbà á sí federal university of technology akure ní ìpínlẹ̀ òndó láti kẹ́kọ̀ọ́ nípa mining àti mineral engineering ní èyí tó sì gboyè èkọ́ bachelor of technology btech ní ọdún 1997 ó gboyè ẹ̀kó ti master's degree ní international diplomacy ní university of lagos ó jé akẹ́kọ̀ọ́ gboyè láti manchester business school england níbi tó ti gboyè mba
matthew aṣímọlówó
tunde bakare tunde bakare tí wọ́n bí ní november 11 1954 jẹ́ wòlíì àti olùṣọ́-àgùntàn ti orílẹ́-èdè nàìjíríà ó kẹ́kọ̀ọ́ gboyè nípa ìmọ̀-òfin ní university of lagos ó sì fi ṣiṣé látàri ṣíṣí ilé-iṣẹ́ tirẹ̀ sílẹ̀ ó padà fi iṣẹ́ náà sílẹ̀ láti lọ ṣe iṣẹ́ olúwa óṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bí i amòfin àgbà ní deeper life bible church àmọ́ ó padà lọ sí redeemed christian church of god níbi tí ó ti di olùṣọ́-àgùntàn tí ó sì ṣe ìdásílẹ̀ ìjọ ìgbàlódé ìyẹn model parish lẹ́yìn tí ó darapọ̀ mọ́ redeemed christian church of god bakare kúrò láti lo ṣe ìdásílẹ̀ ìjọ tirẹ̀ tí ó sọ ní latter rain assembly church lásìkò tí ó sì jẹ olùṣọ́-àgùntàn ìjọ náà ó díje dupò ààrẹ orílẹ́-èdè nàìjíríà pẹ̀lú muhammadu buhari ní 2011 nigerian presidential election ní ọdún 2019 bakare ṣe ìkéde láti fi èrò rẹ̀ hàn láti díje dupò fún ipò ààrẹ lẹ́yìn ìṣèjọba buhari ẹlẹ́ẹ̀kejì ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ ayé rẹ̀ ìdílé mùsùlùmí ni wọ́n bí bakare sí àmọ́ ó gba ẹ̀sìn kìrìsìtẹ́ẹ́nì ní ọdún 1974 bakare lọ sí ilé-ìwé all saints primary school kemta ní abeokuta àti lisabi grammar school abeokuta lẹ́yìn tí ó lọ kọ́ ẹ̀kọ́ nípa ìmọ̀-òfin ní university of lagos láàrin ọdún 1977 àti 1980 wọ́n pè é sí ẹgbẹ́ àwọn adájọ́ ti ilẹ̀ nàìjíríà ní ọdún 1981 lásìkò tó ń sin orílẹ̀-èdè rẹ̀ ìyẹn national youth service corps nysc ó ṣiṣẹh ní gani fawehinmi chambers rotimi williams co àti burke co solicitors ó ṣe ìdásílẹ̀ ilé-iṣẹ́ tirẹ̀ tó pè ní tunde bakare co el-shaddai chambers ní october 1984
done p dabale done peter dabale tí wọ́n bí ní april 26 1949 tó sì ṣaláìsí ní august 26 2006 jẹ́ olùdásílẹ̀ ìjọ united methodist church ní orílẹ́-èdè nàìjíríà umcn lásìkò tó jẹ́ bíṣọ́ọ̀bù iye àwọn ọmọ-ẹgbẹ́ ìjọ náà lọ láti 10000 sí 400000 ètò ẹ̀kọ́ rẹ̀ àwọn ilé-ẹ̀kọ́ tó lọ ni
jeremiah omoto fufeyin jeremiah omoto fufeyin tí wọ́n bí ní 15 february 1971 sí burutu ní ìpínlẹ̀ dẹ́ltà ní orílẹ̀-èdè nàìjíríà jẹ́ olùdásílẹ̀ àti wòlíì àgbà ti ìjọ christ mercyland deliverance ministry cmdm effurun ìpínlẹ̀ dẹ́ltà nàìjíríà ó ṣe ìdásílẹ̀ ìjọ náà ní 3 april 2010 ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ àti ẹbí rẹ̀ wọ́n bí jeremiah omoto fufeyin sí ìlú burutu ní warri ìpínlẹ̀ delta nàìjíríà ní 15 february 1971 ó ṣe ètò ẹ̀kọ́ alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ rẹ̀ ní zuokumor primary school ní burutu lga ti ìpínlẹ̀ delta láàrin ọdún 1981 sí 1986 ó lọ sí ilé-ìwé girama rẹ̀ ní gbesa grammar school ojobo láàrin ọdún 1986 sí 1992
emmanuel iren nigerian gospel artist and pastoremmanuel aniefiok iren wọ́n bí ní ojo kejidinlogun osu opeodun 1989 tí àwọn ènìyàn mọ̀ sí emmanuel iren jẹ́ oníwàásù àti olórin ẹ̀mí ti orílẹ̀-èdè nàìjíríà òun ni olùdásílẹ̀celebration church international cci èyí tí olú-ìjọ wọn wà ní ìpínlẹ̀ èkó ní nàìjíríà ní ọdún 2018 ó ṣàgbéjáde orin àkọ́kọ́ rẹ̀ tí àkọ́lé rẹ̀ jẹ́ kerygma ní ọdún 2022 ó sì ṣàgbéjáde àwò-orin kejì rẹ̀ tí àkọ́lé rẹ̀ jẹ́ apostolosvoice of transition ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ àti ètò ẹ̀kọ́ rẹ̀ wọ́n bí emmanuel iren ní ojo kejidinlogun osu ope odun 1989 ìpínlẹ̀ akwa íbọm ní orílẹ̀-èdè nàìjíríà ló sì ti wá ó lo si ile ekọ́ alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ rẹ̀ ní saint bernadettes nursery and primary school ní ipaja ní ìpínlẹ̀ èkó láti ibẹ̀ ó lọ sí queen’s choice nursery and primary school college ní ikotun ní ìpínlẹ̀ èkó bákan náà ni o ti lo si ile iwe girama doregos private academy láti kọ ẹ̀kọ́
benjamin kalu benjamin okezie kalu jẹ́ gbajúgbajà olóṣèlú omo orílẹ̀-èdè nàíjírìa tó ń ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bíi igbákejì olórí ilé ìgbimọ̀ aṣòfin àgbà orílẹ̀ èdè naìjíríà láti ọdún 2023 ìdìbò rẹ sí ipò yìí ní awon akegbe re nile igbimo asofin abga fowosi kalu n ṣe aṣojú fun agbègbè àpapò bende tí ó si mu ero ati ohun ti awon eniyanre fe wa si ile asofin agba ni orílẹ̀-èdè naijiiria ìgbésí ayé ẹ̀kọ́ àti iṣẹ́ ìṣèlú ojó karùn-ún osù karùn-ún odún 1971 ni wọ́n bí benjamin okezie kalu ní agbamuzu ní ìjoba ìbílẹ̀ bende ní ìpínlẹ̀ abia ó ṣe aṣojú agbègbè bende federal constituency àti pé ó ti pinnu láti ṣe ìdásí sí ìdàgbàsókè orílẹ̀-èdè nípasẹ̀ àwọn ìlànà ìṣòfin ìmúse iṣẹ́ àkànṣe àti ìdàgbàsókè ènìyàn gẹ́gẹ́ bí aṣòfin àti agbẹnusọ fún àpéjọ kẹsàn-án ti ilé-ìgbìmọ̀ aṣojú ní nàìjíríà ó ti gba ìyìn àgbáyé fún àwọn ìgbìyànjú rẹ̀ nínú ìdàgbàsókè orílẹ̀-èdè àti àwọn ìlànà ṣíṣe òfin
khalil halilu khalil halilu tí a bí ní ọjọ́ 29 oṣù kẹwàá ọdún 1990 jẹ́ ọmọ ilé-iṣẹ́ ìṣòwò àti alámọ̀já ìmọ̀-ẹ̀rọ̀ ọmọ orílẹ̀-èdè nàìjíríà òntàjà àti igbákejì aláṣẹ lọ́wọ́lọ́wọ́ àti olùdarí àgbà ti national agency for science and engineering infrastructure naseni ààrẹ bola tinubu yàn án sí ipò yìí ní ọjọ́ kìíní oṣù kẹsàn-án ọdún 2023 igbesi aye ibẹrẹ ati ẹkọ ìlú kano ní ìpínlẹ̀ kano ni wọ́n bí halilu ó lọ sí ilé-ìwé alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ rainbow ní kano láti ọdún 1996 sí ọdún 2001 ó parí ẹ̀kọ́ girama ní st thomas catholic school ní ọdún 2003 àti prime college ní kano ní ọdún 2006 lẹ́hìn náà ni halilu forúkọ sílẹ̀ ní university of hertfordshire ní united kingdom níbi tí ó ti gba oyè ní ìṣàkóso ìṣòwò ní ọdún 2009 oyè ìṣòwò káríayé sì tẹ̀lẹ ní ọdún 2010 lẹ́hìn tí ó parí ẹ̀kọ́ láti ilé-ẹkọ gíga halilu ṣíṣe akọ̀wé ìṣàkóso ní archimode associates lẹ́yìn náà ló parí iṣẹ́ national youth service corps rẹ̀ ní abuja
mc edo pikin gbadamosi agbonjor jonathan tí gbogbo ènìyàn mọ̀ sí mc edo pikin jẹ́ apanilẹ́rìnín ọmọ orílẹ̀-èdè nàìjíríà ó jẹ́ ọmọ bíbí ìlú ihievbe ìlú tí ó wà ní ìpínlẹ̀ edo ní orílẹ̀-èdè nàìjíríà ní ọdún 2021 mc edo pikin gba àmì-ẹ̀yẹ ti the humor award tha fún ìsọ̀rí ti apanilẹ́rìnín ní ọdún náà iṣẹ́ rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí apanilẹ́rìnín ẹ̀gbọ́n rẹ̀ àgbà tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ gbàdámásí bernard koboko ni ó gbà á níyànjú láti múṣẹ́ apanilẹ́rìnín lọ́kúnkúndùn ní ọdún 2014 edo pickin ni olùdásílẹ̀ every package entertainment lára àwọn àwàdà rẹ̀ tí ó gbajúmọ̀ jùlọ ni edo pikin undiluted ó sì ti ṣe àwàdà ní voltage-of-hype bovi's naughty by nature àti supernova live concert ní ọdún 2020 ó ṣe ìlanilọ́yẹ̀ nípa àjàkálẹ̀ àrùn covid-19 ìgbésí ayé rẹ̀ mc edo pikin ní ìyàwó kan tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ lily tí wọ́n sì bí ọmọ méjì
taiwo odukoya daniel taiwo odukoya 15 june 1956 7 august 2023 jẹ́ àlùfáà tí pentecostal ni nàìjíríà ó jẹ́ ọ̀kan lára àwọn òlùdásílẹ̀ àti àlùfáà àgbà tí the fountain of life church tí ó si wà ní ilupeju lagos àti pẹ̀lú àwọn ọmọ ẹgbẹ tótó egbarin ènìyàn ní ọdún 2010s taiwo odukoya wọn bí ní ọjọ́ kàrúndínlógún oṣù kẹfà ọdún 1956 ní ìlú kaduna colonial nigeria níbi tí o tún ti dàgbà ó kẹko ní ilé ẹ̀kọ́ àlákọ̀bẹ̀rẹ̀ àti gírámà ni baptist primary school kigo road kaduna àti st paul’s college èyí tí a mọ sí kufena college wusasa zaria lẹ́yìn ìgbà tó wá lọ sí fasiti ibadan ní ọdún 1976 níbi to tí gba oyè ní petroleum engineering ní ọdún 1981 gẹgẹbi ẹlẹrọ epo ó bẹrẹ iṣẹ ni ile-iṣẹ epo ilẹ naijiria nnpc ní oṣù kẹrin ọdún 1982 lẹ́hìn ètò kàn ń pá tí national youth service corp nysc fún ọdún kan o si ṣiṣẹ́ níbẹ̀ títí di àkókò ìfẹhìntì atinúwá rẹ̀ ni oṣù kínní ọdún 1994 lẹ́hìn ìpè sí iṣẹ ìránṣẹ́ rẹ
madam koi koi madam koi koi tí a tún mọ̀ sí lady koi koi miss koi koi madam high heel tàbí madam moke ní ghana àti miss konkoko ni tanzania jẹ́ òkú nínú àwọn ìtàn ìgbàanì ti ilẹ̀ nàìjíríà àti áfíríkà tó máa ń ṣẹ̀rùbà wọ́n ní ilé-ìgbé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àti ilé-ìgbọ̀nsẹ̀ ní àwọn ilé-ìwé lálẹ́ africa
de general joshua sunday tí orúkọ gbajúgbajà rẹ̀ ń jẹ́ de general jẹ́ apanilẹ́rìn-ín ọmọ orílẹ̀-èdè nàìjíríà nígbà kan ó díbọ́ bí aṣiwèrè kó ba lè fún àwọn ènìyàn tó bá ràn án lọ́wọ́ lówó iṣẹ́ tó yàn láàyò apanilẹ́rìn-ín náà ń rí owó látara ṣíṣàgbéjáde fọ́nrán lórí facebook àti youtube ó mú jackie chan gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe rẹ̀ nítorí ó jẹ́ jagun-jagun tó máa ń lo àwọn eré ìjagun fi pani lẹ́rìn-ín àríyànjiyàn àwọn àjo-tó -ń-rí-sí-oògùn-olóró ìyẹn national drug law enforcement agency ndlea ti fìgbà kan fipá mú de general fún ẹ̀sùn pé ó ní ìpìn nínú oògùn olóró wọ́n sì tì í mọ́lé fún ọ̀sẹ̀ kan wọ́n dá a lẹ́jọ́ ní ilé-ẹjọ́ gíga ti ìjọba àpapọ̀ adájọ́ tó sì ṣe ẹjọ́ náà ni daniel osiagor adájọ́ náà sọ pé kò jẹ̀ bí wọ́n kọ̀ fà á létí ni wọn ò dá a lẹ́jọ́ tàbí ran lọ sẹ́wọ̀n lẹ́yìn tí wọ́n tú u sílẹ̀ de general ṣe ìkéde pé bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé wọ́n rí àwon oògùn olóró nínú ilé òun òun kò mu oògun olóró rárá pé iṣẹ́ apanilẹ́rìn-ín ni òun ń ṣe àwọn ènìyàn ò fi tayọ̀tayọ̀ gba ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn án yìí ọ̀kan lára àwọn tó sọ̀rọ̀ ni basketmouth tó ní wọ́n kọ̀ ń ṣe owó-orí báṣubàṣu ni bákan náà àwọn àjọ tó ń rí sí ẹ̀tọ̀-ọmọnìyàn ìyẹn human rights writers association of nigeria bu ẹnu àté lu ndlea fún ẹ̀gbin tí wọ́n kó bá apanilẹ́rìn-ín náà nígbà tí wọ́n sì fi abba kyari tó jẹ́ ògbóǹtarìgì a-mu-oògùn-olóró sílẹ̀ mr macaroni náà bu ẹnu àtẹ́ lu bí wọ́n ṣe hùwà sí de general nígbà tí wọ́n mú u
climate action africa climate action africa tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ mọ̀ sí cma jẹ́ àwùjọ tí ó ń jà fún climate resilience ilé iṣẹ́ àwùjọ yìí kalẹ̀ sí ní gra ikeja ìpínlẹ̀ èkó oluchi grace àti chukwuemeka fred agbata ni ó da kalẹ̀ ní ọjọ́ kẹrìnlá oṣù kèje ọdún 2021
hauwa ali hauwa ali o ku ni ọdun 1995 jẹ onkọwe ọmọ orilẹede naijiria ti a mọ si awọn iwe aramada rẹ ti n ṣawari awọn igbesi aye awọn obinrin musulumi ati igbega awọn ibeere nipa awọn idiyele islam ati ominira awọn obinrin iwe aramada ti o mọ julọ julọ destiny gba ẹbun delta fun itan arosọ igbesi aye a bi i ni gusau ni ariwa naijiria o kọ ni yunifasiti ti maiduguri ati pe awọn iwe aramada rẹ ni a gbejade ni ipari awọn ọdun 1980 ni ọdun 1995 o ku fun ọgbẹ igbaya awọn ohun ti o kọ awọn itan arosọ rẹ ti o kọ lati oju wiwo ti ọdọmọde ti ko ni iyawo o si ṣe afihan eto-ẹkọ gẹgẹbi “ọna-ọna si aṣeyọri ọjọ iwaju ti o ni iwuri” ohun kikọ akọkọ ti aramada akọkọ destiny enugu 1988 jẹ farida ọmọ ọdun 16 itan naa ṣeto awọn ariyanjiyan laarin ni apa kan eto-ẹkọ iṣẹ ominira ati ọkọ ti farida fẹ ati ni ida keji ọkọ kan ti o rọ awọn ibatan rẹ pe o funni ni aabo owo ṣugbọn gbiyanju lati fi ipa mu u lati tẹriba ati gba si gbogbo awọn yiyan rẹitọkasi nilo aramada keji rẹ iṣẹgun enugu 1989 tẹsiwaju diẹ ninu awọn akori wọnyi ati tun ṣafihan awọn ibeere nipa igbeyawo laarin aṣa alariwisi kan ṣe awọn asopọ laarin awọn iṣoro farida ati islam ni iyanju pe o ṣe afihan “gbigba ifarabalẹ ti ayanmọ” omiiran jiyan lodi si eyi o si tẹnumọ “aisi ifẹ lati wa ni irẹwẹsi” ati ifaramọ rẹ si adura ri igbagbọ rẹ bi agbara rere a ti sọ pe kadara jẹ ti “aṣa ti isọdọtun islam lakoko ti o ṣakoso lati ṣe ibeere abajade ti ohun elo lile” a ti ṣapejuwe ali gẹgẹbi ọkan ninu awọn onkọwe obinrin ni awọn ọdun 1990 ni ariwa ariwa naijiria “ti nfi ohùn fun awọn talenti iṣẹda wọn” laarin “awọn odi ti ẹsin ati aṣa” ayanmọ gba ẹbun delta fun itan-akọọlẹ
blood sisters fíìmù 2022 blood sisters je ere naijiria ti gbe jade ni odun 2022 ere yii je akoko ere naijiria ti yo wo series awon agba osere ibe ni ini dima-okojie ati peelu ramsey nouah kate henshaw wale ojo kehinde bankole deyemi okanlawon gabriel afolayan tope tedela peelu awon elere miiran awon apa meerin ere na jaade ni ojo kaarun osu kaarun odun 2022 eyi si je ibeere ifowosowopo netflix ati mo abudu nipase ilese ere re ebonylife tv biyi bandele ati kenneth gyang ni oludaari fíìmù blood sisters
arabinrin ẹjẹ jara 2022
jude dibia òǹkọ̀wé orílẹ̀-èdẹ̀ nàìjíríàjude dibia tí wọ́n bí ní 5 january 1975 ní ìpínlẹ̀ èkó ní nàìjíríà jẹ́ òǹkọ̀wé ọmọ orílẹ̀-èdè nàìjíríà ní ọdún 2007 ó gba ẹ̀bù ti ken saro-wiwa fún ìwé ìtàn-àròsọ rẹ̀ tí àkọ́lé rẹ̀ ń jẹ́ unbridled ètò-ẹ̀kọ́ dibia kẹ́kọ̀ọ́ gboyè ní yunifásítì ìlú ìbàdàn ó sì gboyè ba nínú ẹ̀kọ́ modern european languages german iṣẹ́ tó yàn láàyò àwọn ìwé-ìtàn àròsọ jude ni wọ́n ṣàpèjúwe gẹ́gẹ́ bí i èyí tó jẹ mọ́ onígboyànínú àti àríyànjiyàn láti ọẃ àwọn òǹkàwé àti alárìíwísí ìwé náà káàkiri ilẹ̀ africa walking with shadows ni wọ́n sọ pé ó jẹ́ ìwẹ́ ìtàn-àròsọ ilẹ̀ nàìjíríà àkọ́kọ́ tó máa ní ọkùnrin tó jẹ́ géè nínú tí ó sì tún jẹ́ olú-ẹ̀dá-ìtàn unbridled náà ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ àríwísí àti àríyànjiyàn ó jẹ́ ìtàn tó dojú ìkà kọ àwọn tó ń fìyà jẹ obìnrin tí ó ti ní ìrírí mọ̀lẹ́bí tí ń bánilòpọ̀ àti ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìjìyà lọ́wọ́ àwọn ọkùnrin wọ́n ti ṣàfihàn àwọn ìtàn kékeré dibia lórí ẹ̀rọ-ayélujára bí i africanwritercom àti halftribecom ọ̀kan lára àwọn ìtàn kékeré rẹ̀ ni one world tó jẹ́ àkójọpọ̀ ìtàn kékeré bí i ti chimamanda ngozi adichie àti jhumpa lahiri
natasha bowen natasha bowen jẹ́ olùkọ́ àti òǹkọ̀wé ọmọ orílẹ̀-èdè nàìjíríà-tó tan-mọ́-àwọn-ará-wales ó ń kọ àwọn ìwé aláìdálérí-ìtàn-gidi fún àwọn ọ̀dọ́ wọ́n mọ̀ ọ́n fún ìwé ìtàn-àròsọ rẹ̀ skin of the sea tó jẹ́ ìwé ìtàn-àròsọ tó ń tà jù ní new york ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ ayé àti ètò-ẹ̀kọ́ rẹ̀ wọ́n bí natasha bowen sí cambridge ní england sí bàbá tó jẹ́ ọmọ yorùbá àti si ìyá tó jẹ́ ọmọ wales ó dàgbà ní cambridge pẹ̀lú ìṣínilójú sí àṣà yorùbá èyí tó padá̀ lò nínú àwọn àkọsílẹ̀ rẹ̀ ó kẹ́kọ̀ọ́ nípa creative writing ní bath spa university léyìn tó kẹ́kọ̀ọ́ jáde ó kó lọ sí apá ìlà-oòrùn london níbi tí ó ti di olùkọ́ iṣẹ́ tó yàn láàyò ìwé àkọ́kọ́ bowen ni skin of the sea èyí tó jẹ́ ìwé àkọ́kọ́ ti of mermaid and orisa series èyí tó jẹ́ èrò àtinúdá rẹ̀ látara àṣà yorùbá tó ti kọ́ ìyẹn nípa ìtàn-àròsọ ti ilẹ̀ afrika àṣà yorùbá àti ìfẹ́ rẹ̀ fún yemọja ó tẹ ìwé yìí jáde ní 2 november 2021 láti ọwọ́ ilé-iṣẹ́ atẹ̀wétà ti random house ó kọ ìwé náà lásìkò tí ó jẹ́ olùkọ́ ní ilé-ìwé lẹ́yìn náà ló kọ simi tó jẹ́ ìtàn nípa mami wata tó rin ìrìn-àjò lọ sí òkè-òkun láti lọ ṣàwárí ẹlẹ́dàá lẹ́yìn tí ó rú ọ̀fin tó tako ìwàláyé àwọn mami wata ìwé náà wọ orí new york times àti indie bestseller lists ó sì gba ọ̀pọ̀lọpọ̀ àríwísí tó dáa àwọn òǹkàwé náà sì yin òǹkọ̀wé fún ìjọra ìwé náà pẹ̀lú the little mermaid àti ìlò yemọjà ti ilẹ̀ adúláwọ̀ àti àṣà yorùbá láti fi ṣàfihàn transatlantic slave trade soul of the deep ni ìwé tó kọ lẹ́yìn náà ó sì jáde ní september 27 2022 àtòjọ ìwé rẹ̀ of mermaid and orisa series
jhumpa lahiri nilanjana sudeshna jhumpa lahiri tí wọ́n bí ní july 11 1967 jẹ́ òǹkọ̀wé ti indian àti american tí ó gbajúmọ̀ fún àwọn ìtàn kékeré rẹ̀ ìwé ìtàn-àròsọ àti àròkọ rẹ̀ ní èdè gẹ̀ẹ́sì àti ní èdè italy à̀tòjọ ìtàn kékeré rẹ̀ ni interpreter of maladies 1999 tó gba ẹ̀bùn pulitzer prize for fiction àti ẹ̀bùn pen/hemingway award ìwé ìtàn-àròsọ rẹ̀ the namesake 2003 ni ó fàyọ nínú fíìmù àgbéléwò the namesake ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ ayé àti ètò-ẹ̀kọ́ rẹ̀ wọ́n bí lahiri sí ìlú london ó sì jẹ́ ọmọbìnrin ti àwọn ará india tó sí lọ sí west bengal ìdílé rẹ̀ kó lọ sí united states nígbà tó wà ní ọmọ-ọdún mẹ́ra lahiri máa ń rí ara rẹ̀ bí i ará america ó sì máa ń sọ pé wọn ò bí mi síbi àmọ́ ó ṣe é ṣe kó jẹ́ bẹ́ẹ̀ lahiri dàgbà sí kingston ní rhode island níbi tí bàbá rẹ̀ ìyẹn amar lahiri ti ń ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bí i librarian ní university of rhode island ìwé the third and final continent ìtàn tó parí interpreter of maladies jẹ́ èyí tó kọ nípa bàbá rẹ̀ ìyá lahiri fẹ́ kí àwọn ọmọ òun dàgbà sí mímọ àṣà bengali àwọn mọ̀lẹ́bí rẹ̀ sì máa ń wá wò wọ́n dáadáa ní calcutta àtòjọ iṣẹ́ rẹ̀ ìwé ìtàn-àròsọ milan guanda 2018 isbn new york knopf 2021 isbn adálérí-ìtàn-gidi àròkọ ìjábọ̀ ìròyìn àti àwọn àfikún mìíràn december 7 2015 translated from the italian by ann goldstein
oṣù kínní
àtojọ awọn èso
abimbola adelakun abimbola adunni adelakun born 15 september </link> jẹ́ akọ̀wé ọmọ nàìjíríà igbesiaye ọmọ bíbí ní ìbàdàn gúúsù ìwọ̀ oòrùn nàìjíríà ó ti kẹ́kọ̀ọ́ ní fásitì ti ìbàdàn níbi tí ó ti kẹ́kọ̀ọ́ yege pẹ̀lú ìwé ẹ̀rí àti master of arts ní ìbánisọ̀rọ̀ àti iṣẹ́ èdè o gboye gboye gege bi phd dimu ni ijó ati itage ni university of texas austin ó ṣíṣe pẹ̀lú ilé - iṣẹ ìwé ìròyìn the punch ní lagos nàìjíríà gẹ́gẹ́ bí oǹkọ̀wé ó kẹ́kọ̀ọ́ nípa àṣà ìgbà ni tí áfríkà bí ó ṣe ń gbé àti bí wọ́n ṣe kópa gẹ́gẹ́ bí ẹkọ nínú eré ẹ̀dá africana àti ẹ̀kọ́ nípa yorùbá ó kọ́ nípa àwọn ìwé ẹ̀kọ́ tí ó sì tí tẹ jáde ní oríṣiríṣi ìwé àkọsílẹ̀ bí ìwé àkọsílẹ̀ tí obìnrin àti ẹsin àti ìwé àkọsílẹ̀ nípa àsà àti ẹ̀kọ́ nípa obìnrin áfríkà díẹ̀ nínú àwọn ìwé rẹ jẹ́ ‘coming to america race class nationality and mobility in “african” hip hop’ 2013 pentecostal panopticism and the phantasm of “the ultimate power” 2018 ‘the spirit names the child pentecostal names and trans-ethics’ 2020 ‘black lives matter nigerian lives matter language and why black performance matters’ 2019 ‘pastocracy performing pentecostal politics in africa’ 2018 ‘godmentality pentecostalism as performance in nigeria’ 2017 ‘the ghosts of performance past theatre gender religion and cultural memory’ 2017 ‘spectacular prophecies examining pentecostal power in africa’ 2017 ‘remixing religion an interdisciplinary graduate student conference’ 2014 ‘yoruba studies review’ and ‘i am hated therefore i am the enemy in yorùbá imaginary’ </br> ó jẹ́ ònkọ̀wé ìwé ti lábẹ́ brown rusted roofs
jimoh oyewumi ajagungbade iii ọba jimoh oladunni oyewumi ajagungbade iii yoruba jímọ̀ ọládùnní oyèwùmí 27 may 1926 12 december 2021 fìgbà kan jẹ́ sọ̀ún àti olórí ìlú ògbómọ̀ṣọ́ fún ọdún méjìdínláàádọ́ta 48 years títí di ìgbà tó kú ní ọdún 2021 ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ àti ibi tó ti ṣẹ̀ wá oba jimoh oladunni oyewumi ajagungbade iii ni wọ́n bí gẹ́gẹ́ bí i prince jimoh oladunni oyewumi ní 27 may 1926 sínú ìdílé ọlọ́ba ti ilé oluwusi ní ìlú ògbómọ̀ṣọ́ sínú ìdílé oba tó wà lórí oyè nígbà náà ìyẹn oba bello afolabi oyewumi ajagungbade i àti ọ̀kan lára àwọn olorì ìyẹn seliat olatundun oyewumi bàbá rẹ̀ ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìyàwó ó sì ní ọmọ mẹ́tàlélọ́gọ́ta 63 children ìyẹn ọmọbìnrin mọ́kànlélọ́gbọ̀n 31 daughters àti ọmọkùnrin méjìlélọ́gbọ̀n 32 sons òun ni àbígbẹ̀yìn láàrin àwọn ọmọkùnrin mẹ́tẹ̀ẹ̀ta tí ìyá rẹ̀ bí wọ́n bi ní ọdún kẹwàá tí bàbá rẹ̀ ti gun orí oyè bàbá-bàbá rẹ̀ ìyẹn oba gbagungboye ajamasa ajagungbade i tó jọba láàárín ọdún 1869 sí 1871 tàbí 1870 sí 1877 bàbá bàbá-bàbá rẹ̀ ìyẹn oluwusi aremu tó jọba láàárín ọdún 1826 sí 1840 oluwusi jẹ́ ọmọbà toye akanni alebiosu ti ogbomoso tó jẹ́ aare ona kakanfo keje ti ìlú ọ̀yọ́ àti sọ̀ún ògbómọ̀ṣọ́ ètò-ẹ̀kọ́ kí ó tó jọba bàbá oyewumi kú ní 18 february 1940 nígbà tó wà ní ọmọdún mẹ́tàlá lẹ́yìn ikú bàbá rẹ̀ ó ní láti dẹ́kun lílọ sí ìlé-ìwé ti st patrick catholic school ní oke-padre ní ìbàdàn ó sì padà sí ògbómọ̀ṣọ́ níbi tí ó ti gbé pẹ̀lú ìyá rẹ̀ lásìkò ìsìnkú ọlọ́ba náà ó lọ sí ogbomoso people's institute ní paku ní ogbomoso láti lọ tẹ̀síwájú nínú ẹ̀kọ́ alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ rẹ̀ bó tilẹ̀ jẹ́ pé ó í láti kúrò láti lọ kọ́ bí wọ́n ti ń hun aṣọ pẹ̀lú àwọn ẹ̀gbọ́n rẹ̀ ní iléṣà ibẹ̀ ni ó sì tí kọ́ bí wọ́n ti ń hun aso ofi ó padà rin ìrìn-àjò lọ sí ìlú jos ní nàìjíríà ní 17 may 1944 níbi tí ó ti bẹ̀rẹ̀ ìdókòwò rẹ̀ nínú títà àti ríra ọtí òyìnbó láti united kingdom ìmọ̀ rè láti sọ èdè gẹ̀ẹ́sì ṣí ilèkùn owò púpọ̀ fún un ó sì da owò pọ̀ mọ́ ọlpọ̀lọpọ̀ àwọn aláwọ̀ funfun lẹ́yìn náà ló ṣèdásílẹ̀ ilé-iṣẹ́ jooyewumi and company nigeria limited èyí tó jẹ́ ilé-ìgbàlejò ó padà lọ sí ògbómọ̀ṣọ́ láti jos ní ọdún 1973 láti lọ forúkọsílẹ̀ fún ìdíjedupò ọba ti sọ̀un lẹ́yìn ikú oba olajide olayode ii ìgbésí ayé rẹ̀ oyewumi jẹ́ oníyàwópúpọl ó sì fé ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìyàwó ó fẹ́ ìyàwọ́ àkọ́kọ́ rẹ̀ ìyẹn ayaba igbayilola oyewumi tó ti ṣaláìsí báyìí ní ọdún 1950 lára àwọn ìyàwó rẹ̀ ni ayaba olaronke oyewumi b 1949 ó ní ọmọ mẹ́rìndínlógún 24 children àti ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọmọ-ọmọ àti ọmọ ọmọ-ọmọ kunle oyewumi ni ọmọ ẹlẹ́ẹ̀kọkànlélógún rẹ̀ ọ̀kan lára àwọn ọmọ rẹ̀ jẹ́ ọ̀kan láar àwọn gbajúgbajà onímọ̀ ìyẹn oyeronke oyewumi ó jẹ́ mùsùlùmí àmọ́ ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ọmọ àti ìyàwó rẹ̀ jẹ́ kìrìsìtẹ́ẹ́nì ó wàjà ní 12 december 2021 ní ọmọdún márùndínlọ́gọ́run 95
emeka enejere emmanuel nnaemeka enejere 19442016 was a nigerian academic and a political scientist he was the 14th pro-chancellor and chairman of the governing council of the yunifásítì ilẹ̀ nàìjíríà nsukka and a former president of the national union of biafran students in the midst of the nigerian civil war early life and education enejere was born in nsukka into the family of israel aneke idah and obochi enejere on august 8 1944 he obtained his first school leaving certificate from st paul's practicing school awka in 1957 in 1962 he obtained his west african senior school certificate from okongwu memorial grammar school nnewi in 1971 he graduated with a bsc political science from the university of nigeria nsukka he proceeded to new school for social research new york city us where he obtained his ma pol sc in 1975 and passed his phd examination with distinction in 1977 career enejere worked as a clerk of high court registry enugu between 1963 and 1964 after his bsc in 1972 he worked as senior manager hardware division of union trading company utc in lagos at the same time he was a part-time lecturer of daily times of nigeria training school for journalists during his stay in the united states he lectured at westbury college between 1973 and 1974 york college between 1975 and 1979 and adelphi university garden city upon his return to nigeria he secured an appointment with the university of nigeria nsukka on february 5 1980 as a lecturer in the department of political science where he taught for twelve years and earned himself the name 'hobbes’ he was a visiting lecturer to the command staff college jsc nigeria air force kaduna in 1981 he served as a member of the joint governing council of institute of management and technology imt and anambra state university of technology asutech enugu 1986 he also served as chairman governing council of girls secondary school ibagwa-aka 19871988 chairman governing board of vanguard industries anambra state furniture company enugu 19871988 chairman governing board of lotto anambra state lottery company enugu 19881989 member mamser brain trust abuja and a host of other bodies while on sabbatical from unn from 1989 to 1990 enejere served with the nigerian presidency in various capacities these includes as deputy director political education mamser headquarters abuja member mamser study team of 3 on comparative analysis of mobilization strategies in africa covering ethiopia tanzania ghana togo and nigeria he developed with others and edited mamser political education manual and he served as editor mamser publications he led mamser national headquarters political education campaigns in south-east and south-south zones of the country and he made contributions to several transition-to-civil-rule committees of the babangida administration transition programme through mamser in 1993 he voluntarily retired from the university of nigeria nsukka two decades later on april 9 2013 he was appointed the 14th pro-chancellor/chairman governing council of the university of nigeria however in december 2013 he was suddenly relieved of his duty leading to a protest by members of staff and students of the institution against the action
pius n okeke pius nwankwo okeke ti a bi ni 30 oṣu kẹwa ọdun 1941 jẹ awòràwọ ati olukọni ni orilẹ-ede naijiria ti o ṣe alabapin lọpọlọpọ si iwadii aaye afirika igbesi aye ibẹrẹ pius nwankwo okeke ni a bi ni 30 oṣu kẹwa ọdun 1941 ni oraukwu okeke lo si ile iwe alakobere ni oraukwu nibi ti o ti gboye ni math leyin naa lo lo si ile-iwe girama ni washington memorial grammar school lati 1957 titi di 1962 okeke lo si ile eko imo pajawiri ni ilu eko nibi to ti se ipele a ni 1965 o gba wọle si university of lagos lati kọ ẹkọ fisiksi sugbon nitori ogun abele ni won gbe e lo si university of nigeria nibi to ti pari oye oye nipa fisiksi ni odun 1971 o tesiwaju gege bi omo egbe iwadi ni fasiti ko too pari phd ni odun 1975 o si di eni akoko ti o gba ṣe bẹ iwadi ati iṣẹ ni 1979 okeke gbe bi oluwadi postdoctoral si university of cambridge lati ṣiṣẹ labẹ abojuto ti ọjọgbọn martin rees nigbati o pada si naijiria ati ni 1989 o di ọjọgbọn ati olori ile-iṣẹ iwadi space ni university of nigeria ni yunifasiti ti nigeria o jẹ olori ẹka ti fisiksi ati astronomy ati lẹhinna alakoso ti ẹkọ ti imọ-iṣe ti ẹkọ-ara lati 1999 si 2002 ni oṣu kọkanla ọdun 2022 okeke jẹ olukọ ọjọgbọn ni fasiti ti nigeria okeke jẹ onimọ-jinlẹ abẹwo ni university of tuebingen 1995 ati harvard smithsonian centre fun astrophysics 1997 ẹlẹgbẹ iwadii agba ni national astronomical observatory of japan 1993 olukọ abẹwo ni south africa astronomical observatory 1996 ati ọmọ ẹgbẹ igbimọ ita ti national research foundation south africa lati 1994 titi di ọdun 2000 okeke jẹ ààrẹ ẹgbẹ astronomical africa ati oludari ile-iṣẹ fun imọ-jinlẹ alafo ipilẹ nipasẹ awọn eto ile-iwe giga ti o lagbara ati awọn ohun elo iwadii o ti ṣe iranlọwọ lati ṣe aṣáájú-ọnà awọn eto imọ-jinlẹ aaye ni afirika awò awò-awọ̀nàjíjìn rédíò kan tí ó jẹ́ mítà 25 ọ̀kan nínú àwọn tó tóbi jùlọ ní áfíríkà ni a gbé kalẹ̀ sí nsukka lábẹ́ ìdarí okeke àti ní àjọṣepọ̀ pẹ̀lú china okeke ti ṣe agbejade awọn iwe-ẹkọ 15 lori fisiksi ati imọ-jinlẹ okeke ni onkowe ti senior secondary physics okeke ti ṣe ipa ti ko ni iwọn si idagbasoke awọn ọmọ ile-iwe ti o jẹbi lodidi fun iṣelọpọ ni ayika 3/4 ti awọn astronomers ti nigeria okeke ni won pe ni baba ti aworawo ni nigeria okeke jẹ alabaṣepọ ni ile-iwe pan-afirika ti awọn astronomers ti n yọ jade paasea ati ile-iwe igba ooru kariaye ti iwọ-oorun afirika fun awọn awòràwọ ọdọ igbesiaye rẹ “braving the stars” jẹ alajọpọ nipasẹ sam chukwu ati jeff unaegbu ni ọdun 2013 awọn ẹbun okeke jẹ ẹlẹgbẹ ti royal astronomical society fras ẹlẹgbẹ ti ile-ẹkọ giga ti imọ-jinlẹ ti naijiria 1998 ẹlẹgbẹ ti ile-ẹkọ giga ti ile-ẹkọ imọ-jinlẹ ti afirika 2017 ati alamọran ajo agbaye fun imọ-jinlẹ aaye ni afirika ni ọdun 2007 okeke jẹ olugba afirika ti o gba ẹbun un/nasa fun iṣẹ rẹ ni ilọsiwaju astronomy ni afirika igbesi aye ara ẹni okeke ti ni iyawo si francisca okeke olukọ ọjọgbọn ti fisiksi o si ni ọmọ mẹfa francisca okeke jẹ onimọ-jinlẹ ti iṣeto ti o ti ṣẹgun l'oréal-unesco fun awọn obirin ni awọn ẹbun imọ-jinlẹ ni ọdun 2013 awọn atẹjade ti a yan okeke pius n anyakoha m w 1987 senior atẹle fisiksi london macmillan isbn 0-333-37571-8 oclc 17776397 siwaju kika braving the stars the biography of pn okeke famous nigerian space scientist and professor of physics
mahmoud abdel-aty mahmoud abdel-aty jẹ olukọ ọjọgbọn ara egipti ti mathimatiki ati imọ-jinlẹ alaye ni ile-ẹkọ giga sohag ati ẹka iṣiro ni ilu zewail ti imọ imọ-ẹrọ ati innovation o jẹ ẹlẹgbẹ ti a yan ati igbakeji alakoso ariwa afirika tẹlẹ ti ile-ẹkọ giga ti imọ-jinlẹ ti afirika alakoso igbimọ orilẹ-ede egypt fun international mathematical union ati alakoso ile-iṣẹ fun awọn ibatan kariaye ni ile-ẹkọ giga sohag igbesi aye ibẹrẹ ati ẹkọ mahmoud abdel-aty ni a bi ni 6 kọkànlá oṣù 1967 o gba oye akọkọ bsc o tayọ pẹlu ọlá ni ọdun 1990 lati ile-ẹkọ giga assiut egipti o gba oye master of science ni mathimatiki ti a lo lati ile-ẹkọ giga assiut ni ọdun 1995 o gba phd ni mathematics applied ati kuatomu alaye lati max planck institute of quantum optics ni 1999 ati gba dsc rẹ ni mathimatiki ati fisiksi lati national university of uzbekistan ni 2007 iṣẹ-ṣiṣe mahmoud abdel-aty bẹrẹ iṣẹ rẹ gẹgẹbi oluranlọwọ olukọni ni ile-ẹkọ giga assiut 1990-1995 o jẹ olukọni ni ile-ẹkọ giga south valley ni ọdun 1995 titi di ọdun 1997 nigbati o lọ kuro lati lepa doctorate rẹ ni max planck institute of quantum optics munich o di olukọ oluranlọwọ ni ọdun 1999 ni ile-ẹkọ giga south valley lẹhin ipo postdoctoral ni ile-ẹkọ giga flensburg lati 2001 si 2003 o di alamọdaju ẹlẹgbẹ ni ile-ẹkọ giga south valley ni 2004 o di olukọ ni kikun ni ile-ẹkọ giga sohag ni 2009 o jẹ alaga ipilẹ ti ẹka mathematics applied ni zewail city of science ati imọ-ẹrọ 2013-2017 ni ọdun 2017 o di dean ti iwadi imọ-jinlẹ ati awọn ikẹkọ graduate ni ile-ẹkọ imọ-jinlẹ ti applied bahrain ati lati 2018 titi di isisiyi o jẹ alakoso ile-iṣẹ ibaṣepọ kariaye ni ile-ẹkọ giga sohag awards ati iyin ni ọdun 2003 abdel-aty gba aami eye igbaniyanju ti ipinle fun iṣiro ni ọdun 2005 o gba aami eye imọ-jinlẹ ti agbaye kẹta ni iṣiro ni ọdun 2007 o gba aami eye foundation abdul hameed shoman fun awọn oniwadi arab ni iṣiro ati awọn imọ-ẹrọ kọmputa ni ọdun 2009 o fun ni ẹbun fayza al-kharafi ni fisiksi nipasẹ ile-ẹkọ giga ti imọ-jinlẹ ati imọ-ẹrọ ti egypt ni ọdun 2011 o gba aami-ẹri ipinle fun ilọsiwaju ni imọ-jinlẹ ipilẹ nipasẹ ile-ẹkọ giga ti imọ-jinlẹ ati imọ-ẹrọ ti egypt ni ọdun 2018 o gba ẹbun mohamed bin rashed fun ipilẹṣẹ to dara julọ ninu eto imulo ede ati eto ti mohamed bin rashed foundation funni o jẹ nla 5awal
àwọn ará ìbàràpá ethnic groupàwọn ará ibarapa jẹ́ ẹ̀ya yorùbá tí ó wà ní apá gúúsù ìwọ̀-oòrùn ìpínlẹ̀ ọ̀yọ́ orúkọ àwọn ará ìlú yìí jẹ yọ láti ará èso bàrà tí a mọ̀ sí egusi ibara èyí tí ó jẹyọ nínú ìtàn tí àwọn alábàágbé wọn pa bí i àwọn egba ibadan àti àwọn oyo pé wọ́n ń dáko ní agbègbè náa
femi orenuga kenny oluwafemi gbolahan ademola femi orenuga tí wọ́n bí ní 18 march 1993 jẹ́ agbábọ́ọ̀lù orílẹ̀-èdè gẹ́ẹ̀sì tí ó ń gbá a ní ààrin-gbùngbùn iṣẹ́ tó yàn láàyò southend united orenuga tí wọ́n bí ní ìpínlẹ̀ lewisham ní london darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù southend united ní ọdún 2006 lẹ́yìn tí ó wú ẹgbẹ́ náà lórí nígbà tí aṣojú kan fà á kalẹ̀ kò pé tí ó darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ náà ni ó ṣe ìrànwọ́ fún southend láti gba ife ẹ̀yẹ norhanle ní orílẹ̀-èdè denmark eléyìí tí ó mú kí àwọn ikọ̀ fc copenhagen àtibrøndby nífẹ̀ẹ́ sí i ó di agbábọ́ọ̀lù tó kéré jù lọ láti kópa fún ikọ̀ southend united nígbà tí ó wọlé ní ìṣẹ́jú kẹ́tàléláàádọ́rùn-ún 93rd ní ìjáwé-olúborí wọn lórí ikọ̀ luton town pẹ̀lú àmì-ayò mẹ́ta sí oókan nínú ìdíje fa cup abala kejì èyí tí ó wáyé ní keji ni 29 november 2008
òǹkò àwọn ará òǹkò tí a tún mọ̀ sí ará òkè ògùn jẹ́ ẹ̀yà yorùbá jé àwọn tó ń gbé apá kan òkè ògùn ní erékùṣù ìpínlẹ̀ ọ̀yọ́
lawuyi ogunniran láwuyì ògúnníran 5 november 1935 21 september 2020 jẹ́ òǹkọ̀wé eré ní nàìjíríà tó ṣe ọ̀pọ̀lọpọ̀ iṣẹ́ ní èdè yorùbá eré rẹ̀ eégún aláré jẹ́ iṣẹ́ tí gbogbo ayé tẹ́wọ́ gbà ó sì jẹ́ ìwé tí a nílò fún kíláàsì lítíréṣọ̀ yorùbá ní ọ̀pọ̀ ilé ẹ̀kọ́ girama ní nàìjíríà ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ìwé ẹ̀kọ́ ti jẹ́ ìyàsọ́tọ̀ láti ṣe ìtúpalẹ̀ àwọn oríṣiríṣi iṣẹ́ rẹ̀ pẹ̀lú ìwé-ẹ̀kọ́ phd kan láti ọwọ́ saudat adébísí hamzat ní yunifásítì ti ìlọrin tí àkọlé rẹ̀ jẹ́ a new historicist analysis of selected plays of láwuyì ògúnníran ati olú owólabí dúrótoyè adélékè ọ̀jọ̀gbọ́n nínú ẹ̀kọ́ ìmọ̀ ẹ̀dá-édé àti áfíríkà ní yunifásítì ìbàdàn ti tún ṣàyẹ̀wò lórí ‘shakespearean fool’ nínú iṣẹ́ ògúnníran pẹ̀lú eré onítàn mẹ́ta láti ọwọ adébáyọ̀ fálétí ọláńrewájú adépọ̀jù àti afọlábí ọlábímtán àwọn mìíràn ti ṣiṣẹ́ lórí àyẹ̀wò àwọn ewì àti ọ̀nà àsọyé tí òṣèré náà ń lò nínú àwọn iṣẹ́ rẹ̀ àwọn àtẹ̀jáde ààre-àgò aríkùyerì eégún aláré ọmọ alátẹ́ ìlẹ̀kẹ̀ ìbàdàn mesìọ̀gọ̀ kìnnìún ilẹ̀ yorùbá 18291893 ọlọ́run ò màwàda àtàrí àjànàku igi wọ́rọ́kọ́ nibo laye dori ko ọ̀nà kan ò wòjà abínúẹni coauthored with yẹmí ọmọ́táyọ̀ ààrò mèta àtọ̀runwá ìṣe tí àwọn yorùbá ńṣe
richard bamisile richard olufemi bamisile ẹni tí gbogbo ènìyàn mọ̀ sí bafem wọ́n bí i ní 27 september 1965 jẹ́ olóṣèlú nàìjíríà tí ó sì jẹ́ ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin tó ń ṣojú agbègbè gúúsù èkìtì ii ó tún jẹ́ agbẹnusọ ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ èkìtì nígbà kan rí ìjókòó kẹta ó wà lára àwọn olùdíje fún ipò gómìnà nínú ètò ìdìbò abẹ́nú ẹgbẹ́ òṣèlú apc ní 2019
abideen olasupo olasupo abideen opeyemi tí àbí ní october 17 1993 ní ìlú ifọ́n ní ìpínlẹ̀ osun ó jẹ́ oníṣòwò orílè èdè nàìjíríà ó jẹ́ olùdásílè ilé-iṣẹ́ opab gas àti brain buiders youth development initiative bbydi ó sì jẹ́ ìkan lára alágbàwí sdgs un pe olasupo abideen láti sọ̀rọ̀ ní 2023 economic economic and social council ecosoc youth forum tí ó sọ̀rọ̀ lórí kókó ọ̀rọ̀ yìí strengthening the trust of youth in multilateralism exploring intergenerational and peer-to-peer dialogue intergenerational wọ́n tún dárúkọ rẹ̀ lára àwọn ọ̀dọ́ ajàfẹ́tọ̀ọ́ tí ọ́ máa sọ̀rọ̀ ní ungass lórí àwọn ọ̀rọ̀ àti ojútùú fún dídènà àti gbígbógun ti ìwà ìbàjẹ́ àti fífi ìfọwọ́sowọ́pọ̀ kárí ayé
sam aluko samuel àlùkò august 18 1929 february 7 2012 jẹ́ gbajúgbajà ọmọ nàìjíríà onímọ̀ ètò ọrọ̀ ajé àti ọ̀mọ̀wé tó kọ oríṣìíríṣìí àwọn ìwé tí ó yànnàná àwọn àlàkalẹ̀ ìjọba lórí àwùjọ àti ètò ọrọ̀ ajé àlùkò tún kó ipa olùdámọ̀ràn fún àwọn aṣíwájú olóṣèlú bí i obafemi awolowo àti sani abacha ànfàní ìkẹyìn yìí ni wọ́n lè pé ó ṣàjòjì nítorí i bí ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ ayé àlùkò ṣe jẹ́ àtakò ńlá sí àwọn àìṣe déédé ìjọba èròńgbà ètò ọrọ ajé àti ti òṣèlú àlùkò jẹ́ ti bíbu ẹnu àtẹ́ lu bámúbámú la yó láàárin àwọn olóṣèlú àti mímú àlékún bá owó tí ìjọba ń pa wọlé gẹ́gẹ́ bí ọ̀nà láti mú kí ìdàgbàsókè ọrọ̀ ajé wà ó jẹ́ ayànnàná lórí ètò ọrọ̀ ajé ìlú ó sì tún jẹ́ fi ojú lámèétọ́ wo àwọn àlàkalẹ̀ àwọn báńkì onídàgbàsókè ti ìlẹ̀ òkèrè tòun ti àwọn àlàkalẹ̀ nípa ipò tí ètò ọrọ̀ ajé nàìjíríà wà àti àwọn àbà tó lè mú ojútùú sí àwọn ìṣòro à-jẹ-mọ́- ètò-ọrọ̀-ajé wá
david abioye david olatunji abioye je omo naijiria ti a bi ni march 111961o je onigbagbo onkowe ati oniwaasu oun niigbakeji adari ijo fun ijo olorun igbagbo aye kaakiri agbaye iyen living faith church o je bisoobu ati oniwaasu agba ni ijo to wa ni abuja eyi ti a n pe ni ilu goseni ti o ni iwon omo ijo oke meji ati abo ti o n josin nibe ìgbésí ayé rẹ̀ a bi i si ilu idile kan ni ipinle kwara abioye se igbeyawo pelu arabinrin mary abioye won si bi omo meta david jr ruth ati daniel o lo si ile eko giga yunifasiti ti ilu ilorin lati lo ko eko nipa imo ero iyen mechanical engineering o sise olumo ni ile eko gbogbo nise ni auchi iyen open cast polytechnicauchi ni odun 1985 fun odun kan
olusoji fasuba olusoji adetokunbo fasuba ti a bi ni 9 july 1984 je elere ori paapa ologorunibuso o gbe gba oroke laarin awon elere ile adulawo ni iseju aaya 985 titi ti akanni simbine fi gba ipo naa ni july 2021 pelu iseju aaya 984 iberepepe aye re wọ́n bí fasuba sí sapele ní ìpínlẹ̀ dẹ́ltà ní orílẹ̀-èdẹ̀ nàìjíríà òun ni àkọ́bih nínú ọmọ mẹ́ta eré-ìahrayá ti wà nínú ìdílé náà ìyá rẹ̀ tó jẹ́ jamaican máa ń sáré nígbà tó wà ní ṣàngó òde òun sì ni àbúrò don quarrie tó jẹ́ gbajúgbajà eléré ìdárayá àwọn òbí rẹ̀ fun ní àtìlẹ́yìn láti sá́ré lásìkò èwe rẹ̀ ó sì mọ eré sá gan-an débi pé kò sí ẹni tó le là á ní ilé-ìwé alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ rẹ̀ pàápàá jù lọ ó mọ bọ́ọ̀lù àfẹ́sẹ̀gbà football volleyball àti basketball ó sì gba àmì-ẹ̀yẹ láti lọ sí mixed secondary school látàri ìwé ọ̀fé tó fún un ó máa ń gbé igbá orókè ní gbogbo ìdíje tí wọ́n bá ṣe fasuba tẹ̀síwájú nínú ẹ̀kọ́ rẹ̀ ó lọ sí obafemi awolowo university ní ile-ife àmọ́ iṣé náà nira fún un pẹ̀lú ìgbìyànjú láti ọ̀dọ̀ ìyá rẹ̀ ó fi iṣé ilé-ìwé sílẹ̀ ó sì lọ sí inú eré-ìdárayá lójú pálí
tunde adebimpe babatunde omoroga adebimpe listen ⓘ ti wón bí ní february 25 1975 ó je olórin orílè-èdè améríkà olórin-orinrin òsèré adarí àti olorin wiwo ti a mo si gege bi olori olorin ti brooklyn -based band tv lori redio
oyin adejobi oloye oyin adejobi 19262000 jẹ́ òǹṣèré ni orílẹ̀-èdè nàìjíríà orúkọ rẹ̀ oyin tunmọ si honey ni èdè gẹ̀ẹ́sì ó kọ oríṣiríṣi itan o si kópa nínú eré orí ìtàgé yorùbá lori ẹrọ amóhùnmáwòrán ati ninu fíìmù ọ ṣe ìgbéyàwó pẹlu òṣèré grace oyin-adejobi ti wọn sì jọ wà pọ̀ títí di ọjọ́ ikú rẹ̀ pàápàá jùlọ o gbajumo fún eré agbelewo orogun adedigba eyi ti o jẹ ìtàn ìgbésí ayé rẹ̀ o tún ní eré amóhùnmáwòrán ọ̀sẹ̀ẹ̀ṣẹ̀ 'kootu ashipa' eyi tí o ma n nṣe ni adari ilé iṣẹ amóhùnmáwòrán naijiria nigerian television authority ni abala ti ìlú ibadan a sọ gbọ̀gàn iṣèré 'oyin adejobi' ti o gbajúmọ̀ lẹyìn orúkọ rẹ̀
abimbola abolarinwa abímbọ́lá ayọ̀dèjì abọ́lárìnwá tí wọ́n bí ní 1979 jẹ́ oníṣègùn ọmọ nàìjíríà ó jẹ́ urọ́lọ́jístì obìnrin àkọ́kọ́ ní nàìjíríà ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ ayé rẹ̀ a bí abímbọ́lá ní ilẹ̀ gẹ̀ẹ́sì ìlú ọba uk fún ìyà rẹ̀ tí ó jẹ́ agbẹjọ́rò bàbá rẹ̀ sí jẹ́ ọmọ ógun òfuurufú àti dókítà onísẹ́ abẹ abọ́lárìnwá jẹ́ ọmọ bíbí ìlú ìlọfà tí ó jẹ́ ọ̀kan lára agbègbè ìjọba ìbílẹ̀ òkè ẹ̀rọ́ ní ìpínlẹ̀ kwara ó ka ilé ẹ̀kọ́ alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ ni ilé ẹ̀kọ́ ọmọ ógun òfuurufú nàìjíríà alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ ní kaduna ó ṣi parí ilé ẹ̀kọ́ girama rẹ̀ ní ilé ẹ̀kọ́ ọmọ ógun òfuurufú obìnrin tó wà ní ìlú jos kí ó tó tẹ̀síwájú láti kẹ́kọ̀ọ́ gboyè nínú ìmò ìṣègun ní yunifásítì ibadan ni ọdún 2004
lanre buraimoh lanre buraimoh kẹ́kọ̀ọ́ iṣẹ́-onà ìlẹ̀kẹ̀-híhun lọ́wọ́ àwọn òbí rẹ̀ olóyè jimoh buraimoh àti àlàkẹ́ buraimoh tí wọ́n jẹ́ gbajúgbajà onílẹ̀kẹ̀ ní orílẹ̀-èdè nàìjíríà àti òkè òkun ẹ̀ṣọ̀ òun àrà tí àwọn ẹ̀yà yorùbá ilẹ̀ adúnláwọ̀ ń fi ìlàkẹ̀ ìbílẹ̀ dá sí adé bàtà àti ọ̀pá ìtìlẹ̀ àwọn ọba aládé ni ó ṣokùnfà ìfẹ́ tí lanre buraimoh ní sí iṣẹ́ ìlẹ̀kẹ̀ híhun ọgbọ́n àtinúdá alárà titun onílẹ̀kẹ̀ kíkùn ti buraimoh fi kún ìlẹ̀kẹ̀ ìbílẹ̀ mú kí ẹwà ìlẹ̀kẹ̀ àwọn yorùbá yọ síi ìṣelẹ́ṣọ̀ọ́ yìí sì ṣàfihàn àwọn ìgbàgbọ́ yorùba nípa ìfẹ́ ìdánilárayá àti ìṣọ̀kan
chin ce chin ce tí wọ́n bí ní ọdún 1966 jẹ́ ònkọ̀wé ewì ìtàn-àkọ́ọ́lè àti àròsọ àti olóòtú àwòrán ìgbésíayé rẹ̀ o ti kọ ẹ̀kọ́ ní ilé-ìwé ti ìlú calabar ó jẹ́ ònkọ̀wé ti ìtàn-àkọ́ọ́lẹ̀ ìtàn-mẹ́ta tí àkọ́leh rẹ̀ ń jẹ́ children of koloko gamji college àti the visitor àwọn iṣẹ́ rẹ̀ chin ce tún jé ònkọ̀ọ̀wé ti àwọn ipele mẹ́ta tí ewì an african eclipse full moon àti millennial àwọn ipele méjì rẹ̀ tí àwọn àròsọ bards àti àwọn aládé àwọn àròsọ ni ìkọ̀wé áfíríkà tí òde òní àti àwọn àròsọ àti bash iṣẹ́ ìṣe áfíríkà àti àwọn àtúnyẹwò lítírésò ṣe ìṣirò díẹ̀ nínú àwọn ààyé àti àwọn ìran tí kíkọ́ áfíríkà àti ìbáwí ni àwọn iṣẹ́ tí chinua achebe ngugi wa thiong'o wole soyinka nwoga chinweizu ernest emenyonu nnolim àti àwọn ewì tuntun mìíràn ìtàn àròsọ àti àwọn ohun tó ṣe pàtàkì láti kakiri orílẹ̀-èdè òǹkọ̀wé àwọn ohun afòyemọ̀ òǹkọ̀wé ìtàn kékèèké bí i the dreamer àti the oracle tí ó kọ sí chinua achebe ce tún ṣàtúnṣe sí african short stories vol 1 àwọn ìwé ítírésọ̀ ilẹ̀ áfíríkà mìíràn
pius nwankwo okeke pius nwankwo okeke ti a bí ní ọjọ́ ọgbọ́n oṣù kẹwá ọdún 1941 jẹ amọrawo àti olùkọ́ ní orílẹ̀-èdè nàìjíríà tí ó ṣe alábàápín lọpọlọpọ sí ìwádìí ààyè afíríkà à mọ ọ si bàbá tí astronomy ní nàìjíríà ìgbésí aye ibẹrẹ pius nwankwo okeke ni a bí ni ọjọ́ ọgbọ́n oṣù kẹwá ọdún 1941 ni oraukwu okeke lo si ile iwe alakobere ni oraukwu níbi tí o tí gboyè ní math lẹ́yìn naa ló lọ si ilé-ìwé gírámà ni washington memorial grammar school láti 1957 titi di 1962 okeke lọ si ilé ẹ̀kọ́ imọ pajawiri ni ilu èkó níbi tó ti ṣe ipele a ni 1965 wọn gba wọlé si university of lagos lati kọ ẹkọ fisiksi ṣùgbọ́n nítorí ogún abele wọn gbé é lọ si university of nigeria níbi tí o tí pari ẹ̀kọ́ gboyè ninu ẹ̀kọ́ fisiksi ni ọdún 1971 o tesiwaju gẹ́gẹ́ bí ọmọ ilé ìwé gíga junior iwadi ni fasiti naa ki o tó parí phd ni ọdún 1975 ó sì di ẹni àkọ́kọ́ ti ó gba ṣé bẹ
philip begho philip begho tí a bí ní ọjọ́ 11 oṣù kiní ọdún 1956 jẹ́ oǹkọ̀wé ọmọ orílẹ̀ èdè naìjíríà òṣèré oǹkọ̀wé fún àwọn ọmọ oǹkọ̀wé ìtàn kúkurú àti akéwì ó ti kọ ju ìwé ogójì lọ a bí i ní warri ipinle delta itsekiri ni baba rẹ̀ ìyá a rẹ̀ sì jẹ́ ọmọ ẹlẹ́yàmẹyà ó gba ẹ̀kọ́ ilé-ìwé gíga rẹ̀ ní king's college èkó ó sì gba llb láti yunifásitì ìlú èkó àti ll m láti yunifásitì ìlú lọ́ńdọ̀nụ̀ ile-ẹkọ iṣowo ti ilu lọ́ńdọ̀nù bó tilẹ̀ jẹ́ pé ó ń ṣiṣẹ́ lọ́wọ́lọ́wọ́ bí oǹkọ̀wé ó ti ṣiṣẹ́ bí oníròyìn òṣìṣẹ́ báǹkì oníṣòwò amòfin àti olùkọ́ni ilé-ẹ̀kọ́ gíga ó tún ti ṣiṣẹ́ ní fíìmù àti eré orí ìtàgé àwọn ìwé ere oníṣe rẹ̀ fara hàn nínú fíìmù tẹlifísìọ̀nù rédíò àti gbàgede ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn eré orí-ìtàgé rẹ̀ ti gba àwọn àmì-ẹ̀rí ó tún máa ń kọ àwọn orin àti àwọn ìtàn nípa ìrírí ìwé òfin rẹ̀ company formation precedents on objects of incorporation ti lọ sínú ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ìpín ìgbésíayé ìgbésí ayé ìbẹ̀rẹ̀ díẹ̀ lára ètò ẹ̀kọ́ philip begho ni ètò ẹ̀kọ́ alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ ni ó gbà ní grange school ikeja ní èkó ṣùgbón nígbà tí bàbá rẹ̀ tí ó ti fìgbà kan jé olórí adájọ́ ní ikeja gba tiransifa lọ sí benin city ti a sì yàn gẹ́gẹ́ bí adájọ́ ní mid-western region ó tẹ̀síwájú nínu ètò-ẹ̀kọ́ alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ rẹ̀ ní ilé-ìwé aládàáni emotan ní ọdún 1967 ó lọ sí king's college èkó ó sì bẹ̀rẹ̀ ìwé kíkọ ní ọmọ ọdún mọ́kànlá fún àwọn àtẹ̀jáde méjì ilé-ìwé rẹ̀ - the searchlight àti the mermaid
babatunde lawal salako nigerian academic babatunde lawal salako born 23 july 1959 jẹ akọkọ ọgá àgbà dókítà oníṣègùn òyìnbó ni ile-eko gíga university ìbàdàn chief medical director of the university college hospital ibadan ni ọdún 1978 sí ọdún 1984 òjé akọkọ olùdarí college of medicine university ti ibadan láàrin ọdún 2014 sí 2016 òjé physician olukọ oníṣe iwadii ati adari odi ọgá àgbà èka olupo ogun òyìnbó ile-eko ni 2011 ohun ni director-general of the nigerian institute of medical research yaba lagos director-general of the nigerian institute of medical research yaba lagos oje professor nephrology ni college of medicine the university of ibadansalako joined the university college hospital ibadan in april 1990 for residency training in the department of medicine and obtained the fellowship ẹkọ oló ilé-ìwé ansar ud-deen practising school leyin na ansar-ud-deen secondary modern school ota ati ansar-ud-deen college offa fún senior secondary school certificate kìí otò lọ sí kwara state college of technology ilorin ti oti ka iwe gbọye first degree at university of ibadan obere ìrìnàjò olupo ogun òyìnbó medicine ni 1986 lẹyìn ìgbà tio gbà ipò bachelor’s degree in medicine and surgery mbbs ni university of ibadan o tẹsiwaju di fellow of the west african college of physicians ni 1994 òjé ọmọ ẹgbẹ he was a member of different organisations and societies which includes nigerian academy of science international society of hypertension in blacks african society of human genetics international society of nephrology global forum for health research and the world heart federation ibi isẹ oje ọkan lára àwọn oṣiṣẹ university of ibadan gégé bíi professor of nephrology at the college of medicine the university of ibadan pẹlu honorary consultant physician and director-general of nigerian institute of medical research iyansipo wón yan sí ipò director-general of the nigerian institute of medical research yaba lagos of was appointed the editor of the tropical journal of nephrology the official journal of the nigerian association of nephrology 2005-2012 having become a member in 1991 vice-president of the association in 2012 president-elect of the association in 2014 and later president of the nigerian association of nephrology in 2016 he is a visiting professor to the university of arizona university of michigan loyola university all in the usa and visiting nephrologist at machester university teaching hospitals at different times he has been external examiner/reviewer to a number of universities both home and abroad including the university of cape coast university of cape town university of western cape south african research foundation and the welcome trust uk àmí ẹyẹ àwọn board and management of the university college hospital ibadan nigeria ni ọdún 2008 fi àmì ẹyẹ da lola pẹlu award of excellence and commitment to medical practice fun iṣẹ takuntakun lórí akoko ṣiṣe pasiparo kidinrin ni university college hospital ibadan references professor babatunde lawal salako https//nimrgovng/about-us-2/meet-the-dg/ was the pioneer chief medical director of the university college hospital ibadan 1978 to 1984 and foundation provost college of medicine https//wwwnamedorgng/webroot/js/tinymce/js/tinymce/plugins/filemanager/depot/events/induction20programme20websitepdf provost of college of medicine university of ibadan a physician teacher researcher and administrator he is currently the director-general of the nigerian institute of medical research yaba lagos he was a professor of nephrology at the college of medicine the university of ibadan https//wwwimpactafricasummitorg/professor-babatunde-salako/#~text=professor20babatunde20lawal20salakoof20medical20research2c20yaba20lagos salako joined the university college hospital ibadan in april 1990 for residency training in the department of medicine and obtained the fellowship https//nimrgovng/nimr/wp-content/uploads/2016/10/profile-of-prof-babatunde-salakopdf a professor https//nucedung/wp-content/uploads/2019/02/directory-of-full-professors-in-the-nigerian-university-systempdf director general appointed on 02/12/2016 as the new nimr dg the national institute for medical research nimr https//pharmanewsonlinecom/8890-2/ education foray inmedicine began in 1986 when he obtained a bachelor’s degree in medicine and surgery mbbs from the university of ibadan and further went on to become a fellow of the west african college of physicians in 1994 he became the head of the department of medicine in both institutions in 2011 and was the provost of the college of medicine the university of ibadan between 2014 and 2016 when he was appointed the director general nigrian institute of medical research yaba lagos by president mohammadu buhari by dint of hard work and good clinical practice he was elected fellow of the royal college of physicians of edinburgh in 2014 and the royal college of physicians of london in 2016 professor salako was the chairman of the nigerian medical association in oyo state 2002-2004 and assistant editor-in-chief african journal of medicine and medical sciences 2012 to 2014 employer prof babatunde l salako faculty clinical sciences https//wwwcomuiedung/indexphp/prof-babatunde-l-salako appointments salako was invited by the cdc in atlanta usa was appointed the editor of the tropical journal of nephrology the official journal of the nigerian association of nephrology 2005-2012 having become a member in 1991 vice-president of the association in 2012 president-elect of the association in 2014 and later president of the nigerian association of nephrology in 2016 he is a visiting professor to the university of arizona university of michigan loyola university all in the usa and visiting nephrologist at machester university teaching hospitals at different times he has been external examiner/reviewer to a number of universities both home and abroad including the university of cape coast university of cape town university of western cape south african research foundation and the welcome trust uk award he was recognized by the board and management of the university college hospital ibadan nigeria in 2008 with an award of excellence and commitment to medical practice in recognition of his contribution to the first successful kidney transplantation at the university college hospital ibadan award of excellence and commitment to medical practice by the board and management of the university college hospital ibadan https//wwwcomuiedung/indexphp/prof-babatunde-l-salako he was subsequently to be invited by novartis international pharmaceuticals as an opinion leader in an expert panel to discuss kidney transplantation in sub-saharan africa- dakar senegal 2010 he has been invited as a guset lecturer or keynote speaker in over 100 times publications diabetic nephropathy--a review of the natural history burden risk factors and treatment https//scholargooglecom/citationsview_op=view_citationhl=enuser=zrbe8ysaaaajcitation_for_view=zrbe8ysaaaajlsltfrupkqcc a meta-analysis identifies new loci associated with body mass index in individuals of african ancestry https//scholargooglecom/citationsview_op=view_citationhl=enuser=zrbe8ysaaaajcitation_for_view=zrbe8ysaaaajlpzeul_q3pic assessment of global kidney health care status https//scholargooglecom/citationsview_op=view_citationhl=enuser=zrbe8ysaaaajcitation_for_view=zrbe8ysaaaajbrmtiyaxlbuc blood pressure hypertension and correlates in urbanised workers in ibadan nigeria a revisit https//scholargooglecom/citationsview_op=view_citationhl=enuser=zrbe8ysaaaajcitation_for_view=zrbe8ysaaaajhqojcs7dif8c global kidney health atlas gkha design and methods https//scholargooglecom/citationsview_op=view_citationhl=enuser=zrbe8ysaaaajcitation_for_view=zrbe8ysaaaajpr6y55bgfssc
bidemi olaoba abidemi ayodeji ogunmolu tí a tún mọ̀ sí bidemi olaoba jẹ́ olórin ìhìnrere àti akọrin wọ́n mọ̀ ọ́n gẹ́gẹ́ bí òǹkọrin ìhìnrere ní ìlànà fújì ìgbésí ayé ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ wọ́n bí olaoba ní ọjọ́ kẹẹ̀dógún oṣù kẹwàá ọdún 1991 sínú ìdílé kírítẹ́nì mẹ́fà ni wọ́n jẹ nínú ìdílé náà ní ìlú èkó orílẹ̀ èdè nàìjíríà ó wá láti ìlú ìkálẹ̀ okitipupa ni ìlú ondo bidemi kọ́ nípa civil engineering ní ilé ìwé gíga tí yaba college of technology ní ìlú èkó àti ẹ̀kọ́ economics ní ilé ìwé gíga yunifásítì tí èkó unilag orílẹ̀ èdè nàìjíríà ìgbésí ayé àti iṣẹ́ tó yàn láàyò olaoba bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ orin kíkọ gẹ́gẹ́ bíi adarí orin ìyìn nínú ìjọ àpósítélì ti kristi ó sì dárapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ akọrin ìjọ cac àti ti ìjọ àwọn ìràpadà kírítẹ́nì lẹ́yìn tí ó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ yìí olaoba gbé orin àkọ́kọ́ rẹ̀ jáde tí ó pe orúkọ rẹ̀ ní final say ní ọdún 2016 ó lókìkí nípa ọ̀rọ̀ tó máa ń sọ pé the bible says wọ́n pe olaoba sí ibi ìyìn àṣẹ è dánu dúró marathon praise èyí tí ìjọ àwọn ìràpadà kírítẹ́nì rccg ṣágbékalẹ̀ rẹ̀ tí wọ́n sì lókìkí lọ́pọ̀lọpọ̀ ó ní orin àdàkọ mẹ́fà ti orí pápá méjì àti orin àjọkọ pẹ̀lú àwọn olórin ìhìn rere lóríṣiríṣi olaoba lọ sí àwọn ìlú bíi íróòbù amẹ́ríkà àti àwọn ìlú áfíríkà ó gbé ìyìn kalẹ̀ níbẹ̀ òun sì ni agbátẹrù ìyìn orí afẹ́fẹ́ tí ó pè ní unrestricted praise tí ó bẹ̀rẹ̀ ní ọdún 2020 ó sì dàpọ̀ mọ́ àwọn olórin ìhìnrere bíi buchi tope alabi mike abdul adeleke adeboye eben àti samie okposo láti kọ orin olaoba ṣeré ní ibi ìpéjọpọ̀ àwọn kírítẹ́nì tó tóbi jù ní nàìjíríà àti ìyìn mèsáyà àṣe è dánu dúró tì wọ́n pè ní festival of life tí ìjọ àwọn kírítẹ́nì ìràpadà gbé kalẹ̀ dubai dublin italy àti united kingdom mass hi-impact praise àti coza concert by the redeemed christian church of god festival of life
moses bliss akọrin moses bliss uyoh enang tí gbogbo ènìyàn mọ sí moses bliss tí a bí ní oṣù kejì ọjọ́ ogún ọdún 1995 jẹ́ akọrin ìhìnrere nàìjíríà adarí orin àti ònkọ̀wé orin ó tún jẹ́ òlùdásílẹ̀ spotlite nation aami akọọlẹ nàìjíríà moses bliss kọ́kọ́ ṣe ifilọlẹ akọkọ rẹ ní oṣù kìíní ọdún 2017 tí àkọlé jẹ́ “e no dey fall my hand” tí ó sì dìde ní òkìkí pẹ̀lú orin tí o kọlù “tóò faithful” tí o gbé jáde ní oṣù karùn-ún ọdún 2019 ní ọdún 2020 ó gbé gba ó ròkè ní loveworld international music and arts eye lima 2020 nípasẹ̀ chris oyakhilome fún orin rẹ “iwọ mo n gbe fun” iṣẹ́ orin moses bliss bẹ̀rẹ̀ sí nifẹ sí orin nígbà ewé rẹ láti ọmọ ọdún márùn-ún ní o tí kọ́ àti bí ó tí lù àwọn irinse orin lẹ́yìn náà ó darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ akọrin ní ìjọ onígbàgbọ́ loveworld moses bliss bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ orin ní ọdún 2017 pẹ̀lú akọrin àkọ́kọ́ “e no dey fall my hand” ní ọdún 2019 ó ṣe ìfìlọ́lẹ̀ orin 'olododo' àti pé ó si tọọ ní ọdún 2020 pẹ̀lú ọkan 'bigger lojoojumọ' awo-orin akọkọ rẹ “olododo ju” ti tu silẹ ni oṣu karun ọdun 2021 ati pe o ni awọn orin 13 pẹlu “itọju itọju” “pipe” ati “e no dey fall hand mi” ni oṣu keji ọdun 2023 o ṣe ifilọlẹ awo-orin keji rẹ ti akole “die ju orin lọ ijọsin ikọja” pẹlu awọn orin 13 ninu
nikki laoye oyenike laoye tí a mọ iṣẹ rẹ sí agbohùn olórin sílẹ̀ olórin níẹnití o máa ṣe ohun kan fún àwọn ènìyàn o máa n ko orin sí lè oníjó òṣèré ní tí a mọ̀ ipa takuntakun tí òun kò nínú orin atí eré orí ìtàgé gẹ́gẹ́ bí agbohùn olórin sílè ilé iṣé orin laoye o tí gbà ọ̀pọ̀lọpọ̀ àmì ẹ̀yẹ bí obìnrin tó dáńgájiá nínú orin kíkọ ní ọdún 2013 àti all african music awards afrima ní ọdún 2014 fún best female artiste in african inspirational music ó gbajúmọ̀ fún orin tó kọ ní ọdún 2006 tí àkọ́lé rẹ̀ jẹ́ never felt this way before orin oníjó ti ọdún 2013 1-2-3 orin only you èyí tí ó kọ pẹ̀lú seyi shay ní ọdún 2006 àti orin onyeuwaoma pẹ̀lú banky w
moses bliss moses bliss uyoh enangti ọpọlọpọ awọn ẹniyan mọ si moses bliss wọn bi ni ogunjo osu kejiodun 1995o je akọrin ọmọ oriledẹ niajiriaada esin ati oluko orino je oludasile spotlite nation ile ise orin orilede naijiria
sinach osinachi kalu okoro egbu tí a mọ̀ gẹ́gẹ́ bí sinach àbí ní ọjọ́ ọgbọ́n oṣù kẹta ọdún 1972 ó jẹ́ olórin ìlú nàìjíríà akọrin àti olórí olùsìn àgbà tí ó tí ń ṣiṣẹ́ fún bí ọgbọ́n ọdún ó jẹ́ akọrin àkókò tó kọ́kọ́ de ipò billboard christian songwriter chart fún ọ̀sẹ̀ méjìlá ẹ̀mẹ́ta ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ní wọ́n yan orin rẹ̀ ó sì gba orin tó dára jù lọ́dún ní 5i st gma dove awards èyí ni ó jẹ́ kí ó di ọmọ nàìjíríà àkókò tí ó gba àmì-ẹ̀yẹ ní ọdún 2021 ó gba ìdánimọ̀ ní us congress ní ìgbà tí ó wà ní ìrìn-àjò ní united states tí amẹ́ríkà
onos ariyo onoriode ebiere ariyo tí a mọ̀ sí onos ariyo jẹ́ akọrin àti akọrin tí ó da lórílẹ̀ ẹ̀dẹ̀ nàìjíríà a mọ̀ ọ́n jùlọ sí orin ìyìn rẹ̀ “alagbara” tí ó jẹ́ àkórí orin tí ọ kọ tí ọ̀gbẹ́ni wilson joel bá a jẹ́ agbéjáde rẹ̀ ni orílẹ̀ èdè nàìjíríà ni oṣù kẹsàn án ọdún 2018 o jẹ́ ẹni kan tí a dárúkọ lára àwọn tí o jẹ́ gbajúmọ̀ àti àwọn tí ọ jẹ́ ìkíní títí dé ti ọgọ́rùn ún àwọn ènìyàn ti o ní ipa jùlọ ti ilẹ̀ áfíríkà mipad ibẹ̀rẹ̀ pẹ̀pẹ̀ ayé rẹ̀ a bí onos ni ìpínlẹ̀ delta ni gúúsù nàìjíríà níbi tí ó ti gba ẹ̀kọ̀ alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ áti gírámà lẹ́yìn ìgbà tí ó gba ìdàsílẹ̀ si delta state university abraka níbi tí ó ti parí ẹ̀kọ́ gíga àkọ́kọ́ ni èdè faranse onos ti bẹ̀rẹ̀ orin kíkọ rẹ̀ láti ìgbà tí o ti wà ni ilé ẹ̀kọ́ alakọbẹrẹ tí o šì jẹ́ akópa lára àwọn tí wọ́n wà ní onírúurú ẹgbẹ́ akọrin àti àwọn ẹgbẹ ṣáájú ki o to lọ si ìlú èkó ni ọdún 2004 níbi tí o ti bẹ̀rẹ̀ gbígbà sílẹ̀ orin àkọ́kọ́ rẹ “ijó” ti flo ṣe jáde
ayo vincent ayodele enitan vincent tí a bí ọjọ́ kejìdínlógún oṣù kínní ọdún 1980 tí a mọ̀ ní iṣẹ́-ìṣère bi ayo vincent jẹ́ olórin ìhìnrere nàìjíríà kan akọrin-akọrin àti òǹkọ̀wé ó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ orin ní 2012 lọ́dún 2012 pẹ̀lú ìtúsílẹ̀ àwo orin àkọ́kọ́ rẹ̀ ní ìdánilẹ́kọ̀ọ́ èmi ni tìrẹ ìgbésí ayé ibẹrẹ àti ẹ̀kọ́ ayodele ní a bí sí reverend sunmbo quashie àti felicia bajulaiye ní ọjọ́ 18 oṣù kejì ọdún 1980 ó sì dàgbà pẹ̀lú àwọn n arákùnrin rẹ̀ mẹ́fà ní ojúẹlẹ́gba èkó fún ètò-ẹ̀kọ́ gírámà rẹ̀ ó lọ sí queens college yaba lagos ó sì gbòye jáde ní ilé-ẹ̀kọ́ gíga ti ìpínlẹ̀ ekó pẹ̀lú bsc ní economics iṣẹ́ orin ọmọ ọdún mẹ́jo ni ayodele bẹ̀rẹ̀ orin kíkọ nígbà tó fi dí ọmọ ọdún méjìlá ló ti darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ akorin ilé ìwé rẹ̀ queens college yaba ní ilé-ẹ̀kọ́ gíga ó darapọ̀ mọ́ àwọn onígbàgbọ love world campus fellowship àti lẹ́yìn náà ṣiṣẹ́ bí olùdarí orin lẹ́yìn náà ó darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ akọrin embassy christ ó sì dìde láti di olùdarí orin zonal ó bẹ̀rẹ̀ ní ifowosi iṣẹ́ orin rẹ̀ ní oṣù kọkànlá ọdún 2012 pẹlú àwo-orin àkọkọ “èmi ni tìrẹ” àwo-orin náà ni àwọn orin 10 ayti ìfihàn àwọn òṣèré ìhìnrere mìíràn bí joe praize àti florocka ní ọdún kànnà ô ṣe ìfilọ́lẹ̀ àkọrin àkọkọ́ rẹ̀ “you are great” ní ọdún 2014 ó ṣé ìfilọ́lẹ̀ ẹyọ̀kan mìíràn ti àkọlé “sin olúwa” tí ó nfihàn don jazzy ní ọdún 2019 ó ṣe ìfilọ́lẹ̀ ẹ́yọ̀ kan “your presence is here èyítí ó gbà aàmì-ẹyẹ́ lima fún orin tí ó dára jùlọ tí ọdún ó ti ṣeré pap pẹ̀lú àwọn olórin ìhìnrere bíi todd dulaney sinach lecrae onyeka onwenu nathaniel bassey ada ehi mercy chinwo àti òmíràn ní ọjọ́ 30 oṣù kẹfà ọdún 2023 ayodele ṣé ìfilọ́lẹ̀ àwo-orin kàn tí àkọlé rẹ̀ “supernatural ep” ìgbésí ayé ará ẹni ayodele ṣe ìgbéyàwó ní 25 june 2005 pẹ̀lú hilary vincent tí wọn sì bí ọmọ mẹ́rin
minisita guc gift ugochukwu christopher tí a bí ní october 8 1993 ó jẹ́ akọrin ni orílẹ̀ èdè nàìjíríà olórin àti àwọn tí ó máa ń kọ orin àwọn onigbagbọ ti a mọ sì minister guc ó jẹ́ olùdámọ̀ nígbà tí ó ṣe álúbọ́ọ̀mù rẹ̀ ni oṣù kejìlá ọdún 2020 with the hit tracks all that matters desperate and yours he officially began his music career in 2019 after he was signed by a record label eezee conceptz a bí guc ní oṣù kẹwàá ọjọ́ 8 ọdún 1993 ní port harcourt àti pé ó wá láti ìjọba ìbílẹ̀ emuoha ìpínlẹ̀ rivers lẹ́yìn ẹ̀kọ́ alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ àti girama ó tẹ̀síwájú láti kẹ́kọ̀ọ́ ní university of port harcourt nigeria ní ọdún 2013 ó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ orin rẹ̀ ní port harcourt gẹ́gẹ́ bí i ọ̀kan láàrin ẹgbẹ́ olórin pẹ̀lú àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀ ní oṣù kọkànlá ni ọdún 2019 guc ti fọwọ́ sí àmì ìgbàsílẹ̀ eezee conceptz láti daràpó mọ́ mercy chinwo judikay àti àwọn òṣèré ìhìnrere mìíràn ó gbé orin àkọ́kọ́ rẹ̀ jáde ní ọdún 2020 tí àkọlé rẹ̀ ń jẹ́ “ìfiránṣẹ́ náà” tí ó ní àwọn orin 12 pẹ̀lú gbogbo nǹkan tí ó ṣe pàtàkì desperate tìrẹ àti ọlọ́run ti olùgbèsan ní oṣù kẹwàá ọdún 2020 guc ṣe àfikún ńlá tí àwọn akorin ìhìnrere ní nàìjíríà láti dé ìwọ̀n tó ga jùlọ ní ọdún kan náà ní youtube
loyola college ibadan
abdin mohamed ali salih abdin mohamed ali salih faas ftwas fiwra larubawa عابدين محمد علي صالح ti a bi ni 1944 ọjọgbọn imọ-iṣe ilu ilu sudan kan ni yunifasiti ti khartoum ati amoye unesco kan ni awọn orisun omi igbesi aye ibẹrẹ ati ẹkọl a bi salih ni wad madani sudan ni 1944salih darapo mo university of khartoum ni 1963 o si gba bachelor of science pelu oye kilaasi first ni civil engineering ni 1969 lẹhinna o gba diploma ti imperial college o si tesiwaju lati pari dokita kan ti philosophy ni hydraulics ni 1972 lati imperial college london lẹhinna o gba diploma ni hydrology lati university of padua italy ni ọdun 1974 iwadi ati iṣẹ lẹhin phd rẹ salih pada si sudan ni ọdun 1973 o si darapọ mọ oluko ti imọ-ẹrọ ti ile-ẹkọ giga ti khartoum gẹgẹbi olukọni ṣaaju ki o to di alamọdaju ẹlẹgbẹ ni ọdun 1977 ori ti ẹka ti imọ-iṣe ilu ni 1979 ati olukọ ni kikun ni ọdun 1982 o di igbakeji alakoso yunifasiti ti khartoum laarin 1990 ati 1991 ni oṣu kọkanla ọdun 2022 o jẹ olukọ ọjọgbọn ni ẹka ti imọ-iṣe ilu ile-ẹkọ giga ti khartoum ati ọmọ ẹgbẹ ti awọn igbimọ alakoso ti ile-ẹkọ giga ti khartoum ati ile-ẹkọ giga sudan ti imọ ati imọ-ẹrọ o tun jẹ olukọ ọjọgbọn ni college of engineering king saud university lati 1982 titi di iwadi salih ati iṣẹ ijumọsọrọ dojukọ aabo omi ati iṣakoso awọn orisun omi o ṣiṣẹ ni unesco lati 1993 titi o fi di oludari ti pipin ti imọ-jinlẹ omi ni ọdun 2011 o si jẹ ọmọ ẹgbẹ igbimọ alase ti unesco lati ọdun 2015 titi di ọdun 2019 o tun jẹ gomina miiran ti igbimọ omi agbaye laarin ọdun 1999 ati 2003 salih ṣiṣẹ bi oludamoran fun igbimọ giga fun idagbasoke riyadh saudi arabia o jẹ ọmọ ẹgbẹ ti ọpọlọpọ awọn awujọ omi agbaye ati pe o jẹ ọmọ ẹgbẹ igbimọ ti ọpọlọpọ awọn ẹbun omi agbaye awards ati iyin a yan salih gẹgẹbi ẹlẹgbẹ ti international water resources association fiwra ni ọdun 1983 ẹlẹgbẹ ti ile-ẹkọ giga ti ile-ẹkọ giga ti afirika faas ni ọdun 1993 ati ẹlẹgbẹ ti ile-ẹkọ giga ọrọ ti awọn sáyẹnsì ftwas ni ọdun 2002 o jẹ ẹbun islam world educational scientific and cultural organisation isesco's eye fun didara ni iwadi imọ-jinlẹ igbesi aye ara ẹni salih ti ni iyawo pẹlu ọmọ mẹta awọn atẹjade ti a yan botilẹjẹpe ọjọ ibi jẹ akiyesi bi 1st ti oṣu kini eyi le ma jẹ otitọ ni akoko ibimọ rẹ 1st ti january ni a yàn fun awọn ti a bi ni ita khartoum fun apẹẹrẹ abdalla hamdok ati omar al-bashir
segun awolowo nigerian lawyer born 1963olúṣẹ́gun awólọ́wọ̀ jr wọ́n bí i ní 27 september 1963 jẹ́ agbẹjọ́rò ọmọ nàìjíríà ó jẹ́ alákòóso àgbà fún nigerian export promotion council láti ọdún 2013 dé ọdún 2021 ó jẹ́ ọmọ-ọmọ àgbà olóṣèlù nàìjíríà nnì olóyè obafemi awolowo ní oṣù keje ọdún 2021 wọ́n panupọ̀ dìbò yàn-án gẹ́gẹ́ bí i ààrẹ àwọn àjọ tóń ṣe ìgbélárugẹ fún òwò ní orílẹ̀ èdè yìí tpos láti ara ecowas member states ìbẹ̀rẹ̀ ayé rẹ̀ wọ́n bí awólọ́wọ̀ ní 27 september 1963 bàbá rẹ̀ ṣẹ́gun awólọ́wọ̀ sr kú ní 1965 ní ẹni ọdún mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n láti ara ìjàm̀bá ọkọ̀ ní òpópó márosẹ̀ ìbàdàn sí èkó àtijọ́ ẹ̀yìn oṣù méjì tí bàbá rẹ̀ kú ni wọ́n bí i ọ̀dọ̀ ẹ̀gbọ́n bàbá rẹ̀ ni ó gbé ka ilé ẹ̀kọ́ alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ abilékọ tola oyediran nee awolowo àti ọkọ rẹ̀ ọ̀jọ̀gbọ́n kayode oyediran kí ó tó dìgbà náà ó gbé lọ́dọ̀ ìyá rẹ̀ àti àwọn tòun ti àwọn ẹ̀gbọ́n àti àbúrò rẹ̀ ẹ̀kọ́ awólọ́wọ̀ bẹ̀rẹ̀ ẹ̀kọ́ rẹ̀ ní mayhill convent school tòun ti dolapo osinbajo ìyàwó igbákejì ààrẹ yemi osinbajolábẹ̀ àmójútó ọ̀jọ̀gbọ́n àti mrs oyediran láti ibẹ̀ ó tẹ̀ síwájú lọ sí igbobi college yaba ìpínlẹ̀ èkó lagos state fún ẹ̀kọ́ sẹ́kọ́ńdírì tí ó sì parí ẹ̀kọ́ sẹ́kọ́ńdírí rẹ̀ ní government college ibadan lọ́gán tí ó parí ẹ̀kọ́ sẹ́kọ́ńdírì rẹ̀ ni ó tẹ̀síwájú lọ sí ogun state university now olabisi onabanjo university ago iwoye tí ó sì kẹ́kọ̀ọ́ jáde pẹ̀lú oyè ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ llb iṣẹ́ awolowo ṣiṣẹ́ pẹ̀lú ilé iṣẹ́ amòfin abayomi sogbesan co àti ilé iṣẹ́ amòfin ti gok ajayi co lẹ́yìn ìgbà tí ó wọ àwùjọ àwọn agbẹjọ́rò ní oṣù kejìlá ọdún 1989 ó ṣiṣẹ́ pẹ̀lú ìjọba president olusegun obasanjo's gẹ́gẹ́ bí olùrànlọ́wọ́ pàtàkì lórí àwọn ohun tó jẹ mọ́ àbàláyé ètò àti ọ̀rọ̀ òfin ó ṣiṣẹ́ pẹ̀lú ìjọba umaru musa yar'adua gẹ́gẹ́ bí olùrànlọ́wọ́ pàtàkì tí ó sì ṣiṣẹ́ ní agbègbè ìjọba àpapọ̀ gẹ́gẹ́ bí i akọ̀wé fún ètò ìdàgbàsókè àwùjọ àti akọ̀wé fún ètò ìrìnà ọkọ̀ láti 2007 di 2011 ó padà sí ìdí iṣẹ́ òfin rẹ̀ lẹ́yìn ètò ìdìbò ọdún 2011 títí di 2013 tí ààrẹ t goodluck jonathan yàn-án sí ipò alákòóso àgbà fún ilé iṣẹ́ nigerian export promotion council tí iṣẹ́ rẹ̀ sì tẹnubodò ní ọdún 2017 oṣù kọkànlá ṣùgbọ́n ààrẹ muhammadu buhari tún tún-un yàn sí ipò yìí kan náà ní oṣù kejì 2018 fún sáà ọdún mẹ́rin mìíràn ìgbésí ayé awólọ́wọ̀ ní ìyàwó pẹ̀lú àwọn ọmọ ọmọbìnrin rẹ̀ ṣeun jẹ́ ọlọ́rọ̀ ìyànjú tí ó sì ń darí ilé iṣẹ́ kan tí kìí ṣe ti ìjọba tí à ń pè ní teach-a-girl nigeria èyí tí ó gbájú mọ́ ẹ̀kọ́ àwọn ọmọbìnrin ní nigeria òun yìí kan náà ni òlùdásílẹ̀ leads africa àti 3d living moments
tina fey elizabeth stamatina tina fey tí a bí ní ọjọ́ kejìdínlógún oṣù karùn-ún ọdún 1970 jẹ́ òṣerébìnrin aláwàdà ọmọ orílẹ̀ èdè amẹ́ríkà fey wà lára àwọn tí ó ko eré nbc sketch comedy tí àkọlé rẹ̀ jẹ́ saturday night live láti ọdún 1997 títí di 2006 òun ni ó sagbátẹ̀rù sitcom 30 rock 20062013 2020 àti erénetflix tí àkọlé rẹ̀ jẹ́ unbreakable kimmy schmidt 20152020 fey tún gbajúmò fún ipa rẹ̀ nínú àwọn eré bi mean girls 2004 baby mama 2008 date night 2010 megamind 2010 muppets most wanted 2014 sisters 2015 whiskey tango foxtrot 2016 wine country 2019 soul 2020 àti a haunting in venice 2023 fey tí gba ọ̀pọ̀lọpọ̀ àmì-ẹyẹ bi àmì ẹyẹ primetime emmy mẹ́sàn-án golden globe awards mẹ́ta àmì ẹyẹ screen actors guild márùn-ún àti àmì ẹyẹ writers guild of america méje ní ọdún 2008 associated press fún fey ní àmì ẹyẹ ap entertainer fún ọdún náà fún ipa rẹ̀ gẹ́gẹ́ bi sarah palin ní snl ní ọdún 2010 fey tún gbà àmì ẹyẹ mark twain prize for american humor ìpìlẹ̀ rẹ̀ a bí elizabeth stamatina fey ní ọjọ́ kejìdínlógún oṣù kàrún ọdún 1970 ní upper darby township delaware county pennsylvania bàbá rẹ̀ donald henry fey wà lára àwọn tí ó fìgbà kan ja ogun ní orílẹ̀ èdè korea ó fìgbà kan jẹ́ adarí yunifásítì ti pennsylvania àti yunifásítì thomas jefferson
ahmed gomaa ahmed radwan ahmed gomaa ahmed radwan jẹ olùkọ́ ọjọgbọn ara egipti ti imọ-ẹrọ imọ-ẹrọ àti àwọn imọ-iṣe imọ-iṣe ní olùkó ti imọ-ẹrọ ilé-ẹ̀kọ́ gíga cairo egypt o jẹ ẹlẹgbẹ ti a yan ti ilé-ẹ̀kọ́ gíga tí imọ-jinlẹ afirika ọmọ ẹgbẹ agba ti institute of electrical and electronics engineers o jẹ olùdarí ile-iṣẹ ìṣáájú ti nanoelectronics integrated systems centre tí ilé-ẹ̀kọ́ gíga nile àti olùdarí ile-iṣẹ imọ-ẹrọ fún ìdàgbàsókè iṣẹ tccd ilé-ẹ̀kọ́ gíga cairo lọwọlọwọ ó jẹ alákóso alákóso ti iwadi àti àwọn iṣẹ àkànṣe onigbọwọ ilé-ẹ̀kọ́ gíga nile egypt ẹkọ ahmed gomaa ahmed radwan lọ sí yunifásítì ti cairo lati bsc si ipele phd o gbà oye bsc ni electronics communications ni 1997 ọdún méjì lẹ́yìn ó fí iwe ẹ̀rí diploma ni engineering mathematics 1999 o si parí msc ni engineering mathematics ni 2002 o gbà oye oye oye oye ni engineering mathematics ni 2006 ẹ̀bùn ati ẹgbẹ ní ọdún 2003 ó gba ẹbun masters ti o dára jùlọ 2001-2004 ni oluko ti ilé-ẹ̀kọ́ gíga tí imọ-iṣe-cairo egypt ní ọdún 2011 ó gba ẹbun iwe 2 ti o dára jùlọ ni àpéjọ káríayé ti microelectronics icm ni tunis ní ọdún 2012 wọn fún ni ọmọ ẹgbẹ ieee agba ní ọdún kanna o tún gba ami ẹyẹ àṣeyọrí ìpínlẹ̀ ní ọdún 2013 ó gba ẹbun imọ-iṣe ti ara ni ìdíje itẹjade káríayé 2013 nípasẹ̀ misr el-khair institution ni ọdun kanna o gba ẹbun awọn aṣeyọri ile-ẹkọ giga cairo ní ọdún 2014 ó yan bí ọmọ ẹgbẹ ninu igbimọ imọ-jinlẹ akọkọ ti ara egipti ile-iṣẹ fún ìlọsíwájú ti imọ-ẹrọ imọ-ẹrọ àti innovation ecasti ní ọdún 2016 ó gba ẹbun ọjọgbọn mohamed amin lotfy ní ọdún 2018 ó gba àmì ẹri kilasi akọkọ ti ìpínlẹ̀ ti imọ-jinlẹ àti iṣẹ ọnà àti ní ọdún 2019 ó gba ẹbun dídára jùlọ ti ìpínlẹ̀ àti tún gba ẹbun scopus ní imọ-ẹrọ àti imọ-ẹrọ
mose bìlísì 0 moses bliss uyoh enang tí gbogbo ènìyàn mọ sí moses bliss tí a bí ní oṣù kejì ọjọ́ ogún ọdún 1995 jẹ́ akọrin ìhìnrere nàìjíríà adarí orin àti ònkọ̀wé orin ó tún jẹ́ òlùdásílẹ̀ spotlite nation aami akọọlẹ nàìjíríà moses bliss kọ́kọ́ ṣe ifilọlẹ akọkọ rẹ ní oṣù kìíní ọdún 2017 tí àkọlé jẹ́ “e no dey fall my hand” tí ó sì dìde ní òkìkí pẹ̀lú orin tí o kọlù “tóò faithful” tí o gbé jáde ní oṣù karùn-ún ọdún 2019 ní ọdún 2020 ó gbé gba ó ròkè ní loveworld international music and arts eye lima 2020 nípasẹ̀ chris oyakhilome fún orin rẹ “iwọ mo n gbe fun” iṣẹ́ orin moses bliss bẹ̀rẹ̀ sí nifẹ sí orin nígbà ewé rẹ láti ọmọ ọdún márùn-ún ní o tí kọ́ àti bí ó tí lù àwọn irinse orin lẹ́yìn náà ó darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ akọrin ní ìjọ onígbàgbọ́ loveworld moses bliss bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ orin ní ọdún 2017 pẹ̀lú akọrin àkọ́kọ́ “e no dey fall my hand” ní ọdún 2019 ó ṣe ìfìlọ́lẹ̀ orin 'olododo' àti pé ó si tọọ ní ọdún 2020 pẹ̀lú ọkan 'bigger lojoojumọ' awo-orin akọkọ rẹ “olododo ju” ti tu silẹ ni oṣu karun ọdun 2021 ati pe o ni awọn orin 13 pẹlu “itọju itọju” “pipe” ati “e no dey fall hand mi” ni oṣu keji ọdun 2023 o ṣe ifilọlẹ awo-orin keji rẹ ti akole “die ju orin lọ ijọsin ikọja” pẹlu awọn orin 13 ninu ní oṣù kẹ̀wá ọdún 2021 ó fowó si nípasẹ̀ “ pínpín symphonic ” ilé-iṣẹ́ pínpín orin ní florida ní oṣù kejì ọdún 2023 ó ṣe àfihàn aami ìgbà silẹ rẹ̀ “spotlite nation” o si fowó sí àwọn òṣeré mẹ́rin chizie festizie doris joseph ati grace lokwa
láwuyì ògúnníran
richard bamisile
olusoji fasuba
abímbọ́lá abọ́lárìnwá
lanre buraimoh
damilola sunday olawuyi damilola sunday olawuyi san fciarb jẹ́ agbani-nímọ̀ràn káàkiri àgbáyé ọ̀jọ̀gbọ́n nínú ìmọ̀ òfin òǹkọ̀wé àti agbaniníyànjú lórí ọ̀rọ̀ epo-rọ̀bì iná ìwa-ohun-àlùmọ́nì àti òfin òun ni igbá kejì adarí yunifasiti afe babalola ado ekiti nigeria wọ́n fún ọ̀jọ̀gbọ́n ọjọgbọn ọlawuyi ní ìgbéga sí ipò ọ̀jọ̀gbọ́n kíkún nígbà tó wà ní ọmọdún méjìlélọ́gbọ̀n 32 ó di ọkàn lára àwọn ọ̀jọ̀gbọ́n tó kéré jù lọ nínú ìtàn ìmọ̀ òfin ní orílẹ̀-èdè nàìjíríà ó di alágbàwí àgbà ti orílẹ̀-èdè nàìjíríà ìyẹn senior advocate of nigeria queen's counsel eqv ní ọdún 2020 ẹni ọdún mẹ́tàdínlógójì ó di ọmọ ilé ẹ̀kọ́ àbíkẹ́yìn tí wọ́n gbéga sí ipò àgbà agbẹjọ́rò lórílẹ̀-èdè nàìjíríà ó jẹ́ igbá kejì alága tíinternational law association ó ti ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bíi ti ṣe iranṣẹ bi bok visiting international professor vip ní university of pennsylvania law school ọ̀jọ̀gbọ́n tó ṣe àbẹwò sícolumbia law school new york china university of political science àti law ias vanguard fellow ní university of birmingham àti olùṣèwádìí àgbà ní oxford institute fún ẹ̀kọ́ energy ní ọdún 2019 ó jẹ́ ọ̀jọ̀gbọ́n tó ṣe àbẹ̀wò sí herbert smith freehills at cambridge university ó ti ṣe ìdánilẹ́kọ̀ọ́ lórí òfin tó dá lórí ọ̀rọ̀ iná ní orílẹ̀-èdè ogójì ní ọdún 2020 wọ́n yàn án gẹ́gẹ́ bíi amòye olómìnira lórí african union's working group lórí àwọn ilé-iṣẹ́ kan àyíká àti ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn ní ọdún 2021 ààrẹ muhammadu buhari yàn án gẹ́gẹ́ bíi ọmọ-ẹgbẹ́ igbìmọ̀ ìṣàkóso ti nigeria extractive industries transparency initiative ní ọdún 2022 ààrẹ united nations human rights council yàn án láti jẹ́ aṣojú ilẹ̀ afirika gẹ́gẹ́ bíi amòye olómìnira lórí ìdókòwò àti ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn ó jẹ́ alága unesco lórí òfin agbègbè àti sustainable development ní hamad bin khalifa university doha qatar ètò ẹ̀kọ́ rẹ̀ ó jẹ́ ọmọ ìlú igbajo ní agbègbè ìjọba ìbílẹ̀ boluwaduro ní ìpínlẹ̀ ọ̀ṣun ní orílẹ̀-èdè nàìjíríà ìlú ibadan ní wọ́n bí i sí ó gba ẹ̀kọ́ alákòóbẹ̀rẹ̀ rẹ̀ ní inri nursery and primary school ní ìbàdàn ó sì lọ sí igbinedion secondary school benin city láti lọ parí ẹ̀kọ́ girama rẹ̀ ibẹ̀ sì ni ó ti jókòó láti kọ ìdánwò àṣekágbá láti gba ìwé-ẹ̀rí waec ní ọdún 2000 lákòókò tí ó wà ní ilé-ìwé wọ́n mọ̀ ọ́ sí “authority” nítorí ìfẹ́ tó ní sí ọ̀rọ̀ ìṣèlú òfin àti orílẹ̀-èdè ó máa ń fi ìtara ka ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìwé-ìròyìn tó gbajúmọ̀ ní orílẹ̀-èdè nàìjíríà nígbà náà
rajaona andriamananjara rajaona andriamananjara faas ftwas 1 oṣù kejìlá ọdún 194330 oṣù kẹsán 2016 jẹ olùkọ́ malagasy ti àwọn imọ-jinlẹ àwùjọ àti ti ọrọ ajé o jẹ oludasile àti olùdarí gbogbogbo ti malagasy institute of planning techniques àti alága ti ilé-ẹ̀kọ́ gíga ti orílẹ̀ èdè madagascar ti arts àwọn lẹta àti àwọn sáyẹnsì acnals ẹkọ a bí andriamananjara ni ọjọ àkọ́kọ́ ninu oṣù kejìlá ọdún 1943 ni ambatomena madagascar lẹhìn alefa ilé-ìwé gíga rẹ lati ilé-ẹ̀kọ́ gíga princeton ní ọdún 1966 andriamananjara gba àwọn iwọn masters méjì ní international affairs àti economics lati ilé-ẹ̀kọ́ gíga george washington àti university of michigan ní 1967 àti 1969 ní atele o gba oye dókítà rẹ ní university of michigan ni ọdun 1971 iṣẹ ṣíṣe andriamananjara ṣiṣẹ gẹgẹbi onimọ-ọrọ-ọrọ pẹlú international monetary fund o tún ṣiṣẹ pẹlú ìjọba madagascar gẹgẹbi oludamọran ní olùdarí ètò eto olùdarí gbogbogbo ti ètò ni ile-iṣẹ ti isuna àti ètò àti oludari gbogbogbo ti institute of madagascar fún àwọn ìlànà ìlànà o jẹ ọmọ ẹgbẹ ti malagasy ethics committee for science and technology cmest àti alákóso ilé-ẹ̀kọ́ gíga ti orílẹ̀ èdè madagascar ti arts àwọn lẹta àti àwọn sáyẹnsì ikú andriamananjara ku látara akàn pancreatic ní ọjọ 30 oṣu kẹsán ọdún 2016 awọn ẹbun àti ìyìn wọn yàn andriamananjara gẹgẹbi ẹlẹgbẹ ti ilé-ẹ̀kọ́ gíga ti àwọn sáyẹnsì ti afirika ní ọdún 2006 ati ilé-ẹ̀kọ́ gíga ti àgbáyé ti imọ-jinlẹ ní ọdún 2010 o jẹ ọmọ ẹgbẹ ti malagasy ethics committee for science and technology cmest àti pé ó jẹ alága ti ilé-ẹ̀kọ́ gíga ti orílẹ̀ èdè madagascar ti arts àwọn lẹta àti àwọn sáyẹnsì 2002 2016 wọn fún andriamananjara ní ẹbùn knight ti madagascar ti àṣẹ ti oye àti afgrad alumni awards ti amẹrika institute of usa gbekalẹ
bayo ojo christopher adebayo ojo san fìgbà kan jẹ́ attorney general ti orílẹ̀-èdè nàìjíríà ó sì tún fìgbà kan jẹ́ olórí nigerian federal ministry of justice ó jẹ́ amòfin ó sì láṣẹ láti ṣiṣẹ́ ní nigeria england àti wales ó tún jẹ́ senior advocate of nigeria ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ ayé àti ẹ̀kọ́ rẹ̀ ojo wá láti ife-ijumu kogi state ní nigeria ó kẹ́kọ̀ọ́ alákòóbẹ̀rẹ̀ rẹ̀ ní maiduguri àti kaduna àti àwọn ẹ̀kọ́ ìyókù ní zaria àti kaduna state ó ṣiṣẹ́ fún ìgbà díẹ̀ ní ilorin kwara state kí ó tó lọ sí university of lagos in lagos níbi tí ó ti gboyè ẹ̀kọ́ nínú ìmọ̀ òfin ní june 1977 ó fẹ́ he is hon justice folashade bayo-ojo wọ́n sì jọ ní ọmọ méjì babatomiwa àti olubusola ó ní àbúrò ọkùnrin méjì daniel oluwasegun ojo àti victor olanrewaju ojo iṣẹ́ rẹ̀ ojo di agbẹjọ́rò ní july 1978 ó ní ìṣàfihàn àkọ́kọ́ rẹ̀ ní ilé-ẹjọ́ lórí ọ̀rọ̀ ìfipábálòpọ̀ kan níwájú hon justice anthony iguh ti high court of justice enugu ní ọdún 1978 lásìkò náà ó jẹ́ agùnbánirọ̀ ó ṣiṣẹ́ ní ministry of justice ní ìpínlẹ̀ kwara gẹ́gẹ́ bíi agbẹjọ́rò fún ìpínlẹ̀ náà fún ọdún mẹ́rin lásìkò yìí ó gba ìwé-ẹ̀rí ní royal institute of public administration ní london ní september 1981 lẹ́yìn náà ó lọ sí london school of economics and political science university of london láti gboyè llm ní september 1982 ní march 1983 ó fi iṣẹ́ ìjọba sílẹ̀ láti darapọ̀ mọ́ oniyangi co gẹ́gẹ́ bíi olórí ilé-iṣẹ́ náà ní ọdún 1986 ó ṣèdásílẹ̀ ilé-iṣẹ́ tirẹ̀ tó pè ní bayo ojo co wọ́n yàn án gẹ́gẹ́ bíi nigeria bar association nba ní ọdún 2004 nígbà kan náà ni wọ́n yàn án sípò attorney general àti minister of justice láti ọwọ́ president olusegun obasanjo ní ọdún 2007 ó di ọmọ-ẹgbẹ́ united nations international law commission títí di òní ó ń ṣiṣẹ́ pọ̀ pẹ̀lú nasir el-rufai àti nuhu ribadu
neymar neymar da silva santos júnior ti a bi 5 kínní 1992 ti a mọ si neymar júnior tabi mononymous bi neymar jẹ agbabọọlu alamọdaju ara ilu brazil kan ti o ṣere bii iwaju fun ẹgbẹ agbabọọlu pro league saudi pro al hilal ati ẹgbẹ orilẹ-ede brazil olukọni ibi-afẹde ati elere-iṣere olokiki fun aṣa iṣere rẹ ti o wuyi o jẹ ọkan ninu awọn oṣere ti o dara julọ ni agbaye ati oṣere brazil ti o dara julọ ti iran rẹ neymar ti gba o kere ju awọn ibi-afẹde 100 fun awọn ẹgbẹ oriṣiriṣi mẹta ti o jẹ ki o jẹ ọkan ninu awọn oṣere diẹ lati ṣaṣeyọri iṣẹ yii neymar wa si olokiki ni santos nibiti o ti ṣe akọrin akọkọ rẹ ti o jẹ ọmọ ọdun 17 laipẹ o di oṣere irawọ liigi brazil o bori 2011 copa libertadores pẹlu santos jẹ akọkọ wọn lati ọdun 1963 o jẹ orukọ rẹ ni bọọlu afẹsẹgba south america ti odun ni ọdun 2011 ati 2012 o tun gbe lọ si yuroopu lati darapọ mọ ilu barcelona ni ọdun 2013 ni akoko keji rẹ gẹgẹ bi apakan ti ikọlu mẹta ti barcelona pẹlu lionel messi ati luis suárez ti a pe ni msn o gba idije continental ti la liga copa del rey ati ajumọṣe aṣaju-ija uefa ti o ni itara lati jẹ ẹrọ orin idojukọ ni ipele ẹgbẹ neymar lairotele kuro ni ilu barcelona fun paris saint-germain psg ni ọdun 2017 ni gbigbe miliọnu 222 € eyiti o jẹ ki o jẹ oṣere gbowolori julọ lailai in paris neymar was voted ligue 1 player of the year in his debut season was integral to psg reaching its first ever champions league final in 201920 and became the highest scoring brazilian player in champions league history awọn ipalara jẹ akoko ere neymar ni psg ati ni ọdun 2023 lẹhin awọn akoko mẹfa ati awọn bori akọle ligue 1 marun o forukọsilẹ fun al hilal ni adehun ti o wuyi ifọrọwanilẹnuwo fun brazil ti o jẹ ọmọ ọdun 18 neymar jẹ agbaboolu giga julọ ni gbogbo igba fun ẹgbẹ orilẹ-ede rẹ pẹlu awọn ibi-afẹde 79 ni awọn ere 128 o gba 2013 fifa confederations cup ti o gba boolu goolu ni akọkọ fifa world cup awọn 2014 àtúnse o ti a npè ni ni dream team ikopa rẹ ni 2015 copa américa ni a ge kuru nipasẹ idaduro ṣaaju ki o to di olori brazil si idije goolu olympic akọkọ wọn ni bọọlu awọn ọkunrin ni 2016 summer olimpiiki nini tẹlẹ iyọrisi ami fadaka kan ni ẹda 2012 lehin ti o ti kọ olori-ogun silẹ o ṣe ifihan ni 2018 world cup ati lẹhin ti o padanu 2019 copa américa nipasẹ ipalara ṣe iranlọwọ fun brazil lati pari ipari-ije ni idije 2021 ninu eyiti o gba aami-eye ti o dara julọ ti o dara julọ pẹlu messi ni 2022 world cup o darapọ mọ pelé ati ronaldo gẹgẹbi awọn ara ilu brazil nikan ti o gba wọle ni awọn idije agbaye mẹta neymar ti gba ami-ẹri samba gold mẹfa kan ti o fun oṣere brazil ti o dara julọ ni yuroopu neymar pari kẹta fun fifa ballon d'or ni 2015 ati 2017 ti a ti fun un ni fifa puskás award ti a ti daruko ninu awọn fifa fifpro world11 ati awọn uefa team ti odun lemeji ati awọn uefa champions league squad ti awọn akoko mẹta igba pa ipolowo o wa ni ipo laarin awọn elere idaraya olokiki julọ ni agbaye sportspro sọ ọ ni elere idaraya ti o ni ọja julọ ni agbaye ni ọdun 2012 ati 2013 ati espn tọka si bi elere-ije olokiki kẹrin-julọ ni agbaye ni ọdun 2016 ni ọdun 2017 akoko pẹlu rẹ ninu atokọ ọdọọdun ti awọn eniyan 100 ti o ni ipa julọ ni agbaye ni ọdun 2018 bọọlu afẹsẹgba france ṣe ipo neymar ni agbabọọlu afẹsẹgba kẹta ti o sanwo julọ julọ ni agbaye ni ọdun to nbọ forbes ṣe ipo rẹ ni elere idaraya-kẹta ti o sanwo julọ julọ sisọ aaye kan silẹ si kẹrin ni ọdun 2020
kamal shaddad kamal shaddad larubawa كمال شداد ti wọn bi ni ọdún 1935 jẹ olùkọ́ ọjọgbọn ara ilu sudan pelu imọ-jinlẹ oniroyin àti olùdarí ere ìdárayá o jẹ alága ẹgbẹ bọọlu afẹsẹgba sudan ju ogun ọdún lọ laarin ọdún 1988 ati 2021 ibẹrẹ ìgbésí aye àti ẹkọ kamal hamid shaddad ní wọn bí ni el-obeid north kurdufan sudan ní ọdún 1935 shaddad kẹ́kọ̀ọ́ yege pẹ̀lú ẹ̀kọ́ ọlá nínú lítíréṣọ̀ ṣáájú láti yunifásítì ti khartoum lẹ́yìn náà ó sì gba ìwé ẹ̀rí kan náà ní yunifásítì kan náà lẹhìn ìyẹn shaddad gba phd lati university of london ni ọdún 1970 ó jẹ́ ọ̀jọ̀gbọ́n nípa ìmọ̀ ọgbọ́n orí ní yunifásítì ti khartoum àti olórí ẹ̀ka náà bọọlu afẹsẹgba ìròyìn shaddad bẹrẹ̀ iṣẹ bọọlu afẹsẹgba rẹ gẹgẹbi òṣeré fún ẹgbẹ abu anja omdurman ní aarin àwọn aadọta kò lè tẹsiwaju iṣẹ bọọlu afẹsẹgba rẹ fún àwọn ìdí ìlera nitorinaa ó gbé lọ ṣé iṣẹ ní ààyè ti akọọlẹ ere ìdárayá shaddad ṣiṣẹ ní ààyè ti akọọlẹ ere ìdárayá ní oríṣiríṣi àwọn ìwé ìròyìn pẹlú al-ayyam àti àwọn ìwé ìròyìn al-zaman times o ṣé olori apakan ere ìdárayá ti àwọn ìwé ìròyìn al-sahafa àti al-rai al-aam ar ero awujọ o tun gbe iwe iroyin al-motafari the spectator jade sudan olympic committee shaddad jẹ igbakeji akọwe ti igbimọ olympic ti sudan 1981 àti 1982 o si di alága ti igbimọ olympic ti sudan laarin 1988 ati 1997 o tún jẹ ọmọ ẹgbẹ ti igbimọ alase ti association of national olympic committees of africa laarin 1989 àti 1993 gẹgẹbi aṣojú ti àwọn igbimọ olympic ni zone 5 èyítí ó pẹlú sudan egypt ethiopia kenya uganda somalia ati tanzania a yan shaddad gẹgẹbi ọmọ ẹgbẹ ti igbimọ bọọlu fún àwọn ere olimpiiki ìgbà ooru 2012 ní ìlú lọndọnu ati pe ó yan gẹgẹbi ọmọ ẹgbẹ ti ẹjọ ti arbitration fún ere ìdárayá ní switzerland ní ọdún 2003 sudan football association wọ́n tún yan shaddad gẹ́gẹ́ bí akọ̀wé lẹ́yìn náà òdì olórí ìgbìmọ̀ ìdánilẹ́kọ̀ọ́ àárín ti ẹgbẹ́ bọ́ọ̀lù sudanese laarin 1962 ati 1967 lẹhinna o di olukọni o si ṣé olórí ọpọlọpọ àwọn ẹgbẹ agbabọọlu sudan ó si di olukọni ẹgbẹ agbabọọlu orilẹ èdè sudan laarin ọdún 1964 si 1967 ní akoko yẹn sudan gba ami ẹyẹ fàdákà ni 1965 arab games ni cairo lẹhin ti o padanu ami ẹyẹ goolu sì egypt o si gba àmì ẹyẹ goolu ni ifè ọrẹ ti agbegbe ìlà-oòrùn afirika ni khartoum 1967 o tún ni ànfàní lati darí ẹgbẹ al-hilal club láti dé òpin 1987 african cup of champions clubs fun igba akọkọ ninu itan rẹ shaddad bẹrẹ̀ iṣẹ ìṣàkóso rẹ ní ẹgbẹ bọọlu sudan ní oṣù kọkànlá ọdún 1979 nígbàtí ó dibo yan akọ̀wé fún ẹgbẹ bọọlu sudan sfa títí di oṣù keje ọdún 1982 ní àsìkò yii sudan borí fún ìgbà akọkọ idije cecafa ni ọdún 1980 shaddad di ààrẹ sfa fún ìgbà akọkọ lati 1988 si 1992 ó sì tẹsiwaju fún ìgbà kejì titi di ọdún 1995 o padà si ààrẹ ti sudanese federation lẹhìn ìsáǹsá ti o dúró fún ọdún mẹ́fà ní àkókò tí omar al-bakri abu haraz ti gba ipò ààrẹ ti sfa shaddad parí iṣẹ rẹ ní didari bọọlu orílẹ̀ èdè sudan nípasẹ̀ ipadabọ lẹẹkansi àti ṣiṣakoso sfa ní àwọn àkókò itẹlera mẹta titi dì ọdún 2010 lẹhìn ti o borí àwọn idibo ti ẹgbẹ bọọlu sudan ní ọdún 2001 nígbà àkókò rẹ al-merrikh sc gba 1989 african cup winners' cup o si ṣẹda ẹgbẹ agbabọọlu orílẹ̀ èdè sudan lábẹ́-17 ni ọdún 1991 o tún ṣiṣẹ gẹgẹbi olukọni ní international federation of bọọlu afẹsẹgba àti confederation afirika ni àkókò yẹn pẹlú àti gẹgẹ́ bí akọroyin bọọlu afẹsẹgba sudan muzammil abu al-qasim nítorí àwọn àríyànjiyàn ti o wa laarin shaddad àti abdel halim mohamed 19102009 ọkàn ninu àwọn oludasilẹ ti confederation ti bọọlu afẹsẹgba afirika àti olùdarí ìpilẹ̀ṣẹ̀ sfa shaddad yàn lati má bu ọla fún ú lákòókò ìgbésí aye rẹ tabi lẹhìn ikú botilẹjẹpe ó yan lati bu ọla fún ìbátan rẹ mubarak shaddad ni 25 july 2010 shaddad kéde pe òun yoo ja fún ẹtọ rẹ lati ṣiṣẹ fún atundi ìbò pàápàá ti o jẹ idiwọ nípasẹ̀ ẹgbẹ bọọlu agbegbe àti igbimọ federal igbimọ naa tọka òfin kan ti o sọ pé shaddad ko le ṣiṣẹ fún ìgbà kẹta láìsí idaduro ipò bọọlu káríayé ti ile-iṣẹ ere ìdárayá mọ shaddad kọ ìpinnu naa ó halẹ lati kan fifa ó si ṣofintoto owó yíyàn yíyàn fifa kilọ pé sudan le dojukọ idaduro tabi yọ kúrò ti kikọlu ìjọba ba tẹsiwaju igbimọ ere ìdárayá sudan gbeja ìpinnu rẹ ní ẹtọ ibamu pẹlú àwọn ìlànà sudan ati fifa idalọwọduro òṣèlú ní bọọlu ti yọrí si ijẹniniya ní ìṣáájú pẹlú nigeria kenya àti guinea ti nkọju si àwọn àbájáde fifa kọ àwọn àbájáde ti 26 july 2010 èyítí ko pẹlú shaddad nítorí kikọlu ìjọba sibẹsibẹ ní oṣù kẹjọ ọdún 2010 shaddad yọkuro yíyàn rẹ àti igbakeji rẹ mutasim jaafar sarkhatm ní ọjọ 29 oṣù kẹwá ọdún 2017 shaddad ní a yan gẹgẹ́ bí adari ẹgbẹ bọọlu afẹsẹgba sudan sfa fún ọdún 2017-2021 lẹhìn ti o ní ààbò 33 ninu àwọn ibo 62 ti ṣẹgun alága alága mutasim jaafar ẹniti ó gba àwọn ibo 28 ilana idibo naa ní àmójútó ní pẹkipẹki nipasẹ caf confederation of african football ọmọ ẹgbẹ igbimọ aláṣẹ suleiman hassan waberi àti alákóso ìdàgbàsókè agbegbe fifa david fani àwọn ọmọ ẹgbẹ sfa ti di didi tẹlẹ̀ nítorí kikọlu ìjọba nígbàtí minisita fún ìdájọ́ ti sudan jẹri idibo ti fifa ko fọwọsi fifa dáhùn nípa fifun sfa ní ipari lati yí ìpinnu naa padà nígbàtí ìpinnu wọn ko yipada fifa da àwọn iṣẹ sfa duro sibẹsibẹ lẹ́hìn oṣù kan fifa gbé òfin de kúrò ní atẹle àṣẹ lati ọdọ prime minister bakri hassan saleh lati fagilee ìpinnu ile-iṣẹ ti ìdájọ́ ìdúró ìjọba gba àtakò lati ọdọ àwọn ẹgbẹ alátakò sudan àti pé ìjọba fi òfin de àwọn media lati ṣé ijabọ shaddad ṣàkóso lati di ipò rẹ múlẹ̀ laibikita pe akoko rẹ ti parí o dojúkọ ọpọ àwọn ẹdun fifa ethics láti igbimọ sfa tirẹ fifa ti gba tẹlẹ̀ lori maapu ọnà fun àwọn ìdìbò pẹlú sfa ati al-merrikh sc al-merrikh ti a da ni ọdún 1908 di ipò pataki kan ninu ìṣèlú bọọlu afẹsẹgba sudan ti o ti gba ọpọlọpọ àwọn àkọlé liigi àti àwọn ife ààrẹ ẹgbẹ́ náà adam sudacal alájọṣepọ̀ ti shaddad ń wá ìdìbò lẹ́ẹ̀kan sí i ó sì ti gba àtìlẹ́yìn láti ọ̀dọ̀ shaddad wọ́n ṣètò àwọn ọjọ́ ìdìbò tí wọ́n sì fòpin sí nígbà tí ìpàdé pápá ìṣeré kan sì ti kún fọ́fọ́ wàhálà tún pọ̀ sí i ní ipari àpéjọ gbogbogbo ẹgbẹ agbabọọlu naa wáyé ní ibi isere miiran pẹlú àwọn onijakidijagan ti o takò ìta lòdì si shaddad àti beere fún ìyípadà àwọn ọlọpa pajawiri ti ilu ṣé idasi ní lilo gaasi omijé àti àwọn opa lòdì si ogunlọgọ naa nikẹhin wọn yọ shaddad kuro ni ọfiisi ati pe mutasim jaafar sarkhatm ni a yan ni ọjọ 13 oṣu kọkanla ọdun 2021 igbesi aye ara ẹni shaddad ni iyawo tí orúkọ rẹ njẹ ibtisam hassab al-rasoul wọn si bí ọmọbinrin kan tí orúkọ rẹ njẹ amna al-rayyan
muhammad mustapha olaroungbe akanbi muhammad mustapha olaroungbe akanbi san tí wọ́n bí ní 24 january 1971 tó sì ṣaláìsí ní 20 november 2022 jẹ́ ọ̀jọ̀gbọ́n nínú ẹ̀kọ́ òfin ní orílẹ̀-èdè nàìjíríà àti igbá kejì olùarí kwara state university ó fìgbà kan jẹ́ ọmọ-ẹgbẹ́ senior advocate of nigeria àti nigeria bar association ìbẹ̀rèpẹ̀pẹ̀ ayé àti ètò ẹ̀kọ́ rẹ̀ wọ́n bí mustapha akanbi ní ọdún 1971 ní ile magaji kemberi awodi gambari quarters ilorin east ní ìpínlẹ̀ kwara ti orílẹ̀-èdè nàìjíríà sí ìdílé mustapha akanbi tó jẹ́ òṣìṣẹ́ ìjọba ó gba ìé-ẹ̀rí west african school certificate láti federal government college okigwe ní ọdún 1989 ó kẹ́kọ̀ọ́ gboyè nínú ìmọ̀ òfin ní obafemi awolowo university ní ọdún 1993 ó gboyè ẹ̀kọ́ ní nigerian law school ní ọdún 1995 wọ́n sì pè é sí iṣẹ́ sí ilé-ẹjọ́ ní ọdún kan náà ní ọdún 1998 ó gboyè masters degree nínú ìmọ̀ òfin ní university of lagos ní ọdún 1998 ó gboyè phd ní university of london's king's college london ní united kingdom ní ọdún 2006 iṣẹ́ tó yàn láàyò iṣẹ́ ní ìlànà ẹ̀kọ́ mustapha akanbi bẹ́rẹ́ iṣé rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí i olùkọ ní faculty of law ní university of ilorin ó sì di ọ̀jọ̀gbọ́n ní ọdún 2012 akanbi fìgbà kan jẹ́ olórí ẹ̀ka department of business law àti dean of faculty of law ní university of ilorin ó sì jẹ́ igbá kejì olùdarí kwara state university malete títí tí ó fi kú iṣẹ́ rẹ̀ gẹ́gé ní onímọ̀ òfin mustapha akanbi ṣiṣẹ́ fún orílẹ̀-èdè rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí i legal assistant ní legal department ti central bank of nigeria ní èkó láti ọdún 1995 wọ ọdún 1996 ní legal firms gafar co ilorin àti wole bamgbala co lagos olawoyin àti olawoyin lagos àti ayodele bákan náà ló ti ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bí i òṣìṣé kékeré láti march 1996 títí wọ 1998 àwọn ẹgbẹ́ tó darapọ̀ mọ́ ó di ọmọ-ẹgbẹ́ nigerian bar association ní ọdún 1995 àti ọmọ-ẹgbẹ́ senior advocate of nigeria ní ọdún 2018
fadwa taha fadwa abd al-rahman ali taha tí orúkọ rẹ̀ ní èdè lárúbáwá jẹ́ فدوى عبد الرحمن علي طه ti a bi 23 ni wọ́n bí ní ọjọ́ kẹtàlélógún oṣù kẹwàá ọdún 1955 agbègbè arbaji ní ìpínlẹ̀ gezira ní orílẹ̀-èdè sudan ó jẹ́ olùkọ́ ọ̀jọ̀gbọ́n nínú ìtàn sakaani ní ilé-ẹ̀kọ́ university of khartoum igbesiaye igbesi aye ibẹrẹ ati ẹkọ fadwa abd al-rahman ali taha ni a bi ni arbaji ipinle gezira ni ọjọ 23 oṣu kẹwa ọdun 1955 o si dagba nibẹ arabinrin naa jẹ akoitan ti o kọ ẹkọ ti o gba apon ti arts ni ọdun 1979 master of arts ni ọdun 1982 phd ni ọdun 1987 gbogbo rẹ lati ile-ẹkọ giga ti khartoum lẹhinna o gba titunto si ti aworan ni itumọ ni ọdun 2002 ni afikun si oye oye oye lati ile-ẹkọ giga ti bergen ni norway ni ọdun 2004 iṣẹ-ṣiṣe fadwa darapọ mọ yunifasiti ti khartoum gẹgẹbi oluranlọwọ ikọni ni ọdun 1979 o di olukọni ni 1997 olukọ oluranlọwọ ni 1992 olukọ ẹlẹgbẹ ni ọdun 2000 ati olukọ ni kikun ni ọdun 2012 ni ọdun 2010 o di olootu iwe iroyin ti olukọni ti arts ni university of khartoum ati awọn ti a yàn bi awọn ori ti awọn itan ẹka ni ọdun 2007 o di igbakeji dean ti oluko ti awọn ikẹkọ graduate lẹhinna o gbe lọ si saudi arabia ati nipasẹ 2010 lati di iduro fun didara iwadii ati awọn ẹkọ imọ-jinlẹ ni ile-ẹkọ giga ti ẹkọ ni hafr al-batin o jẹ alakoso ti ile-ẹkọ giga ti khartoum ni oṣu kẹwa ọdun 2019 fadwa kopa ninu iyika sudan ni ọdun 2019 eyiti o mu ijọba omar al-bashir silẹ o tun ṣe ipa ninu awọn ijiroro laarin awọn ologun ti ominira ati iyipada ati igbimọ ologun eyiti o rọpo ijọba al-bashir ni kete lẹhin igbimọ naa igbimọ alakoso iyipada ti orilẹ-ede ṣe itọsọna orilẹ-ede naa ni akoko iyipada titi ti awọn idibo tuntun yoo fi ṣeto ti ijọba ti o dibo yoo jẹ idasile lẹhin ti awọn ẹgbẹ mejeeji ti de ojutu ti o wọpọ ni 5 keje 2019 o pe lati darapọ mọ igbimọ ṣugbọn o kọ o fi ipo silẹ ni oṣu kọkanla ọdun 2021 ni ilodi si adehun lati da abdalla hamdok pada sipo gẹgẹbi prime minister lẹhin igbimọ ijọba sudan 2021 igbesi aye ara ẹni fadwa ti ni iyawo si al-miqdad ahmed ali ati pe wọn ni ọmọ meji hatem ẹniti o kọ ẹkọ ni ile-iwe ti awọn imọ-iṣe isakoso ile-ẹkọ giga ti khartoum ati ezzat ti o jade ni sakaani ti ina lati ile-ẹkọ giga kanna
abdellatif berbich abdellatif berbich faas larubawa عبد اللطيف بربيش may 17 19421 january 2015 jẹ olùkọ́ ọjọgbọn ti oogun inu o jẹ alága idasile ti nephrology ile-iṣẹ moroccan akowe yẹ ti ilé-ẹ̀kọ́ gíga ti ìjọba ilu morocco àti aṣojú ilu morocco si algiers ẹkọ berbich ní a bí ní fez morocco ní 17 may 1934 o lọ si àwọn ilé-ìwé gíga moulay youssef àti gouraud fún ẹkọ ilé-ẹ̀kọ́ gíga rẹ o gbà oye dókítà ninu oogun ní ọdún 1961 lati ilé-ẹ̀kọ́ gíga tí montpellier láàrin 1962 àti 1964 ó lépa pataki kan ní nephrology àti isọdọtun iṣoogun ní ile-iṣẹ ile-iwosan tí ilé-ẹ̀kọ́ gíga tí paris hospital necker iṣẹ ní ọdún 1967 berbich jẹ olùkọ́ ọjọgbọn ti oogun ní university of rabat àti ni ọdún 1968 ó dì dókítà agba ti ile-iwosan ibn sina-avicenne ní ọdún kanna ó yan gẹgẹbi dean ti olùkó ti isegun ti ilé-ẹ̀kọ́ gíga tí rabat titi di ọdún 1974 ní ọdún 1982 ó dì akọwe ayérayé ti ìjọba ilu morocco àti ní 1988 ó dì aṣojú ilu morocco ní algiers ní oṣù kẹwá ọdún 1968 ó dì olùdarí akọkọ ti asopo kíndìnrín ni ilu morocco àti ni ọdún 1973 ó ṣẹda hemodialysis onibaje akọkọ ni ilu morocco idapọ ati ẹgbẹ berbich jẹ ẹlẹgbẹ ti ilé-ẹ̀kọ́ gíga tí imọ-jinlẹ afirika ní ọdún 1986 ó jẹ ọmọ ẹgbẹ olupilẹṣẹ ti àwọn ẹgbẹ moroccan ti àwọn imọ-jinlẹ iṣoogun àti nephrology ọmọ ẹgbẹ ti faransé àti àwọn ẹgbẹ nephrology káríayé ẹgbẹ ti orílẹ̀ èdè faransé ti oògùn inu àti ilé-ẹ̀kọ́ gíga tí orílẹ̀ èdè faransé ti oogun àwọn ẹbùn àti ìyìn berbich ni a fún ni medal hassi beida àti ẹbùn star tí ogun ni ọdún 1963 alákóso royal victorian ni ọdún 1987 alákóso faransé ti iṣẹ ọnà àti àwọn lẹta ni ọdún 1989 alákóso àṣẹ ti itẹ ti morocco ni ọdún 1989 àti alákóso ti legion of honor 2000 wọn tún fún ni àṣẹ alákóso ti àṣẹ ti merit ni spain germany denmark italy portugal àti senegal o gba àmì ẹri lẹhìn ikú ni medal itẹ òṣìṣẹ́ nla ti ilu morocco ni ọdún 2015 ikú berbich ku ní rabat morocco ní ọjọ 1 oṣù kini ọdún 2015 ẹni ọdún 80 wọn si sin i si ibi iteku martyrs
mubarak shaddad mubarak al-fadil shaddad larubawa مبارك الفاضل شداد 19151980 je alamọdaju iṣoogun ti ara ilu sudan ati oloselu ó ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bí akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ nínú iṣẹ́ ìkọ́bí àti gynecology nígbẹ̀yìngbẹ́yín ó di olùdarí ilé ìwòsàn ìkọ́ni omdurman o kopa takuntakun ninu ẹgbẹ iṣoogun ti sudan ati pe o ṣe ipa ninu iyika oṣu kẹwa ọdun 1964 olokiki ti n ṣagbero fun iyipada iṣelu ni sudan shaddad ṣiṣẹ ni igbimọ alakoso ijọba ti sudan keji o si di ipo olori orilẹ-ede ni ṣoki o tun ṣe olori ile-igbimọ aṣofin ti o jẹ alaṣẹ ṣugbọn ti ijọba gba ijọba ni 1969 igbesi aye ibẹrẹ ati ẹkọ mubarak al-fadil shaddad ni a bi ni ọdun 1915 ni barah sudan o pari iwe-ẹkọ diploma lati ile-ẹkọ isegun kitchener ni 1934 ati lẹhinna ṣiṣẹ ni omdurman khartoum juba yei sinja sennar ad-damazin gedaref ati el-obeid iṣẹ iṣoogun shaddad sise ni omdurman teaching hospital 1961-1964 nibiti o ti di alamọja agba ni obstetrics ati gynecology ati lẹhinna oludari awọn ifunni rẹ gbooro si igbimọ ti ẹgbẹ iṣoogun ti sudanese nibiti o ti ṣe alabapin taratara fun awọn akoko pupọ lati 1961 si 1964 oselu ọmọ ni ikọja awọn igbiyanju iṣoogun ati ẹkọ rẹ o di awọn ipo pataki gẹgẹbi akowe ti ile-igbimọ gbogbogbo ti graduates ni juba lati 1939 si 1940 ati aare lati 1943 si 1945 ile-igbimọ gbogbogbo ti graduates ṣe iwe-iranti akọkọ ni 1942 nbeere ominira lati ọdọ 1942 ojúṣe anglo-egypti o ṣiṣẹ bi adari ilu el-obeid ati pe o di ipo alaga ti ẹgbẹ bọọlu agbegbe rẹ nigbakanna lati 1951 si 1956 shaddad jẹ ọkan ninu awọn aṣoju ti ẹgbẹ onisegun lakoko iyika oṣu kẹwa ọdun 1964 olokiki ti o duro ni iwaju ti ronu ti o yori si awọn iyipada iṣelu pataki ni sudan wọ́n fún un ní ipò aṣáájú-ọ̀nà ṣùgbọ́n ó kọ ànfàní náà sílẹ̀ nítorí ipò ààrẹ lieutenant general abboud ni akoko yẹn ni atẹle lati yiyọ abboud kuro o gba awọn ipa ni igbimọ alakoso ijọba ti sudan keji ti n ṣiṣẹ gẹgẹbi ọmọ ẹgbẹ ati nigbamii bi aarẹ iyipo lati 3 oṣu kejila ọdun 196410 okudu 1965 oun ni alakoso igbimọ ati nitoribẹẹ naa olori ẹgbẹ naa ipinle laarin 131 jan 1965 ati 110 june 1965 shaddad di ààrẹ apejọ apejọ fun igba 19661968 eyiti o jẹ tituka lẹyin naa nipasẹ ifipabalẹ ilẹ sudan 1969
medlar mespilus germanica ti a mọ si medlar tabi medlar ti o wọpọ jẹ igbo nla kan tabi igi kekere ninu idile rosaceae awọn eso igi yii ti a tun pe ni medlar ni a ti gbin lati awọn akoko romu nigbagbogbo wa ni igba otutu ati jẹun nigbati o ba jẹ o le jẹ ni aise ati ni ọpọlọpọ awọn ounjẹ ti a ti jinna nigbati iwin mespilus wa ninu iwin crataegus orukọ ti o pe fun eya yii jẹ crataegus germanica kuntze ni guusu iwọ-oorun ti england ni itan-akọọlẹ o ni nọmba awọn orukọ apeso aibikita gẹgẹbi ṣiṣi-arse ati isalẹ ọbọ nitori irisi calyx nla rẹ
farida fassi farida fassi faas larubawa فريدة الفاسي jẹ ọjọgbọn moroccan tí ẹkọ fisiksi ní ilé-ẹ̀kọ́ gíga mohammed v ní rabat o jẹ oludasilẹ ti ìlànà afirika fún fisiksi ìpìlẹ̀ ìpìlẹ̀ àti ọmọ ẹgbẹ ti ilé-ẹ̀kọ́ gíga ti imọ-jinlẹ afirika igbesi aye ati ẹkọ fassi ni à bi ní larache nibiti ó ti lọ si ilé-ìwé arin àti gíga ṣáájú kí o tó ko lọ tetouan lati parí àwọn ẹkọ ilé-ẹ̀kọ́ gíga rẹ ó gba bachelor of science ni fisiksi lati ilé-ẹ̀kọ́ gíga abdelmalek essâd ni ọdún 1996 lẹhìn ìyẹn ó lọ si ilu sipania ilé-ẹ̀kọ́ gíga ti valencia nibiti ó ti gba titunto si imọ-jinlẹ ní ọdún 1999 ni ọdún 2003 o gba ipò dókítà ti imọye ni fisiksi patiku nítorí iṣẹ rẹ lórí ìdánwò atlas ni cern iṣẹ ati iwadi titi di ọdun 2003 fassi wa lára àwọn atlas ati compact muon solenoid cms ẹgbẹ àdánwò àpapọ̀ èyítí ó padà ṣé àwárí higgs boson ní ọdún 2012 lẹhinna ó ṣiṣẹ ní grid computing àti pínpín data analysis ní ọdún 2007 wọn yan fassi fún idapo ni cern pàápàá fún ọdún mẹtala ó ti n ṣiṣẹ ni oríṣiríṣi àwọn ipò lẹhìn-doctoral àti iwadi gẹgẹbi igbimọ iwadi orílẹ̀ èdè ilu sipeeni ile-iṣẹ orílẹ̀ èdè faransé fún iwadi imọ-jinlẹ àti ile-iṣẹ ilu sipeeni fún patiku astroparticle àti fisiksi nuclear o jẹ olùkọ́ ọjọgbọn ti fisiksi ní ilé-ẹ̀kọ́ gíga mohammed v ni rabat fassi tún jẹ ìfihàn ninu atokọ ti àwọn onímọ̀ ìjìnlẹ̀ sayensi 50 ti o ga jùlọ ní àgbáyé ní ìbámu si atọka imọ-jinlẹ ad tí káríayé 2021 won tí tọka sii ju àwọn àkókò 250000 àti pe ó ni itọka h-219 o wa ni ipo mejidinlogoji ni agbaye ati ipò kejì ni continent afirika àti aarin ìlà-oòrùn fassi jẹ akọwe gbogbogbo ti àwùjọ ti ara arab àti olupilẹṣẹ ti strategy afirika fún ìpìlẹ̀ àti fisiksi ti á ló ẹ̀bùn àti ìyìn fassi jẹ àwọn ẹlẹgbẹ ti ilé-ẹ̀kọ́ gíga ti imọ-jinlẹ afirika ní ọdún 2020
ladoke akintola university of technology
nosa olórin nosa omoregie tí a mọ̀ sí nosa jẹ olórin naijiria akọrin àti òṣẹ̀ré o ti wa ni lọwọlọwọ wole si warner music group african alabaṣepọ chocolate city igbesi aye ibẹrẹ nosa omoregie tí a mọ̀ sí nosa a bi ní ọjọ́ mẹ́rin ẹ́rìndìnlọ́gbọ̀n oṣù kejì 1981 ó jẹ́ ọmọ ìlú benin ìpínlẹ̀ edo ó kọ́ ẹ́kọ́ imò-ẹ̀ro ni yunifásítì benin uniben ìpínlẹ̀ edo orísun ayọ̀ ti nosa bí ọmọdé tí ń dàgbà ni orin àti ilé ìjọsìn níbi tí ó ti bẹ̀rẹ̀ sí ṣàwárí àwọn tálẹ́ńtì ìdàgbàsókè rẹ̀ ó bẹ̀rẹ̀ ní akọrin àwọn ọmọdé ní ilé ìjọsìn àti pé ó ní ipa nípasẹ̀ àwọn akọrin ìhìn rere bí fred hammond àti kim burrell àti àwọn ọkùnrin r n b ẹgbẹ́ àwọn ọkùnrin ii tí ó ṣe àkíyèsí ó padà nífẹ̀ẹ́ jazz àti orin ọkàn àti rọọkì fún ayédero rẹ èrò nosa pẹ̀lú orin rẹ̀ ni láti ṣẹ̀dá afárá láàrín àwọn oríṣi orin lákòókò tí ó ríi dájú pé abala ìhìn rere tí ó wà lórí pẹpẹ iwájú gẹ́gẹ́ bi àwọn irú mìíràn bíi ìdápapọ̀ aláìlẹ́gbẹ́ tí irú tí ìpilẹ̀ṣẹ̀ tí ó borí ohùn orin ẹ̀mí lórí ìgbésí ayé gíga kan pẹ̀lú orin ègbè rọ́kì tàbí orin ' pidgin ' gẹ̀ẹ́sì pẹ̀lú adùn r n b nígbà àwo orin ilé -ìṣeré àkọ́kọ́ rẹ̀ ṣí ìlẹ̀kùn tí tú sílẹ̀ ní ọjọ́ mẹ́rìnlá oṣù kẹrin ọdun 2014 àti àtìlẹ́yìn nípasẹ̀ àwọn ọrin “gbàdúrà fún ọ nígbà gbogbo always pray for you ” “kílódé tí o nífẹ̀ẹ́ mi why you love me ” àti “nígbà gbogbo lórí ọkàn malways on my mind ” ní oṣù kàrún ọdún 2014 ó ṣe àjọṣepọ̀ pẹ̀lú nokia fún orin rẹ̀ “ìfẹ́ ń pè ” ní ọjọ́ mẹ́rin dínlógún oṣù kẹrin ọdun 2014 ìwé ìròyìn punch ròyìn pé nosa fowó sí ìwé àdéhùn kan pẹ̀lú unilever ní ọjọ́ ẹ́rìndìnlọ́gbọ̀n oṣù kínní 2020 èyí tí ó tún jẹ́ ọjọ́ ìbí rẹ̀ nosa tẹ̀síwájú láti ṣí ilé orin rẹ̀ orin ìyọ̀ iṣẹ́ orin àti àṣeyọrí rè nosa fọwọ́ sí ìwé ìdáhùn chocolate city ní ọdún 2012 ní ọjọ́ kọkànlá oṣù kọkànlá ọdún 2009 nosa ṣe ìfilọ́lẹ̀ orin rẹ̀ “gbàdúrà fún ọ nígbà gbogbo” lábẹ́ chocolate city gbàdúrà fún o nígbà gbogbo
muhammad al-mahdi al-majdhub muhammad al-mahdi al-majdhub 1919 - 3 march 1982ti a tún le pe ní al-maghut tabi al-majzoub jẹ́ olókìkí akéwì ara ilu sudan ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn eniyan mọ bi ọkan ninu awọn aṣáájú-ni sudanese ewì àti kí ó ti wa ní ka fún jíjẹ ọkan ninu àwọn akọkọ ewi ti sudanese arabic oríkì àti sudanism àwọn í lọ́wọ́ sí rẹ si àwọn iwe-kikọ sudan ti fi ipa pipẹ silẹ lori ala-ilẹ ewi ti orílẹ̀ èdè naa ibẹrẹ ìgbésí aye àti ẹkọ muhammad al-mahdi al-majdhub ní a bí ni ọdún 1919 ní al-damar olú-ìlú ìpínlẹ̀ odò nile ni àríwá sudan bàbá rẹ ní sheikh sufi ti a mọ ní sudan si muhammad al-majdhub ti ó jẹ ti ẹyà ja'aliyin ti àwọn ẹyà ariwa-aringbungbun sudan khalwa ló ti kọ ẹkọ níbi tí o ti kọ ẹkọ kíkà kikọ àti kuran ní ìbámu si babkier hassan omer iná khalwa ti á mọ ní al-toqaba ṣé atilẹyin al-majdhub lati pe akopọ akọkọ rẹ ní ina majdhib o kọ̀wé ninu ìfihàn si ikojọpọ “àwọn knights àwọn onidajọ àti àwọn eniyan paranormal tí ń wo ni ayika rẹ tí ń ṣe ògo àti orin ọla rẹ laarin àwọn eniyan àti ìtùnú ààbò fún àwọn ọgọrun ọdún” onkọwe ara ìlú sudan àti ọmọ ilé-ẹ̀kọ́ abdullah al-tayyib 1921-2003 dàgbà ní ile al-majdhub lẹhìn ikú baba rẹ àwọn méjèèjì dàgbà ní ọrẹ timọtimọ àti akéwì al-majdhub rin ìrìn àjò lọ sí khartoum fún ilé-ìwé ó sì darapọ mọ gordon memorial college ó sì gboyè gboyè oniṣiro al-majdhub ṣiṣẹ gẹgẹbi oniṣiro ní ìjọba sudan ó sì lọ laarin àríwá gúúsù ìlà-oòrùn àti ìwọ oòrùn eyiti ó ṣé ànfàní fún u ni ṣiṣẹda ẹda ti o ni imọran ti pẹlú ìgbáradì ti ara rẹ ṣé ọnà fún ìdàgbàsókè iṣẹ-ọnà ewì rẹ àwọn iṣẹ litireso ní àkókò yii àwọn atẹjade wa bí al-sudan al-nahda àti al-fajr laarin àwọn oju-iwe al-fajr àwọn onkọwe bíi al-tijani yusuf bashir àti muhammad ahmad mahjub ṣé akọbẹrẹ wọn gẹ́gẹ́ bí òpìtàn huda fakhreddine ṣe sọ àwọn ọmọ ẹgbẹ́ fajr ní òye nípa àjogúnbá àṣà ìṣẹ̀dálẹ̀ sudan àti àwọn ìṣàn omi ìtàn tí ó ṣe àfikún sí ìyàtọ̀ rẹ̀ wọn ṣé ifọkansi lati ṣé àpẹrẹ àwọn aami èdè ti yoo ṣàlàyé idanimọ orílẹ̀ èdè kan huda tẹsiwaju pe muhammad ahmad mahjub ṣé alaye ìmọ̀ràn ti iwe-kikọ sudanese ti á kọ ní èdè arabic ṣùgbọ́n ti a fí kun pẹlú àwọn idiomu ti ilẹ wa nítorí èyí ni ohun ti ó ṣètò àwọn iwe-iwe ti orílẹ̀ èdè kan yàtọ̀ si èkejì ẹgbẹ fajr ti rii ìfarahàn àkọ́kọ́ rẹ ninu àwọn iṣẹ ti muhammad al-mahdi al-majdhub ó di akéwì àkọ́kọ́ tí àwọn ìwé rẹ̀ ṣe àfihàn ìmọ̀ jíjẹ́ ti àwọn àṣà “black” àti “arab” méjèèjì alariwisi osama taj al-sir gbàgbọ́ pe sudanism tabi sudanisation jẹ kedere ninu ewì al-majdhub eyiti ó hàn ní ojú inú rẹ àwọn àwòrán àti èdè rẹ eyiti ọmọ rẹ ti o ku onise ìròyìn awad al-karim al-majdhub ẹniti sọ nípa baba rẹ pe bóyá ohun ti ó ṣe ìyàtọ̀ èdè al-majdhub ní idapọ rẹ - nigbami - laarin aṣa-ara àti èdè larubawa ti o wa titi ti lilo èdè tí ọrọ ọrọ̀ lasan àti ki ó gbìn rẹ sinu asọ ti ewi rẹ osama taj al-sir ọjọgbọn tí litireso ní ilé-ẹ̀kọ́ gíga tí khartoum sọ fún al-jazeera net pe “al-majdhub gbé ìgbésí ayé sudan lọ si ewi àti pé o jẹ ọkàn ninu àkọ́kọ́ lati dapọ laarin àwọn oloye-ọrọ àti ti o wọpọ iṣẹ àkànṣe ara ìlú sudan ṣé aṣojú ìlànà àṣà fún ú” al-siddiq omar al-siddiq jẹri pe sudanism kii ṣé ẹya pataki ti al-majdhub nikan àti pe àwòrán ewì jẹ ọkàn ninu eyiti ó hàn gbangba jùlọ laarin wọn al-majzoub jẹ ẹda ní yiya àwọn àwòrán àti ìgboyà ni iyaworan na àti pé “audacity” yii ko ní opin si àwọn àwòrán nikan ọkan nínú àwọn ẹyà pataki jùlọ ti ewì al-majdhub ní ìwúlò rẹ si ọkùnrin ti o rọrùn ni ita bí osama taj al-sir ṣé gbàgbọ́ pe al-majzoub “ewì ti o gbé - ní ewì ti o ga jùlọ àti èdè alaworan - lati aarin aarin ti ìgbésí aye si àgbègbè rẹ èdèàwùjọ àti ìṣèlú ó kọ̀wé nípa àwọn tó ní ṣọ́ọ̀bù kọfí àwọn tí ń fọ bàtà àpò àpò ẹni tó ń ta ẹ̀wà ẹni tó ń tajà alágbe àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ al-majdhub ti mẹnukan àwọn ìdí rẹ ninu ìbẹ̀rẹ̀ nar al-majdhub pe “mo tí jàǹfààní púpọ̀ ninu dídarapọ̀ mọ́ eniyan pàápàá àwọn tálákà nítorí pe wọn ní òótọ́-ọkàn ti o yanilẹnu ti o ṣé mi ní àǹfààní ti o si mú mi larada” al-majdhub kọ àwọn oríṣiríṣi ìwé miiran àti àwọn akojọpọ o tún ṣé alábàápín ninu àwọn ìwé ìròhìn fún àpẹẹrẹ the nile hana omdurman youth and sports àti àwọn ìwé ìròhìn sudanese miiran ní èdè lárúbáwá dar al-hilal al-doha àti iwe ìròhìn beirut al-adab ti ń gbé iṣẹ rẹ jáde o ní ọpọlọpọ àwọn ifọrọwanilẹnuwo lórí rédíò eyiti ó ṣé pataki jùlọ ni àwọn ifọrọwanilẹnuwo rẹ pẹlú rédíò àti tẹlifisiọnu sudanese voice of the arab voice of america german egypt and tunisian radio ìgbésí aye òṣèlú al-majdhub ṣé idasile pẹlú mahmoud muhammad taha ẹgbẹ arákùnrin republikani ní sudan ní ọdún 1945 ẹgbẹ arákùnrin republikani ṣé alabapin ninu ija fún òmìnira lodisi ìjọba amunisin ti ìlú gẹẹ́sì-egipti al-majdhub ni àwọn ewì iyin àwọn ipò ti àwọn republikani party àti mahmoud muhammad taha al-majdhub ku ní ọjọ kẹta oṣù kẹta ọdún 1982 ni omdurman sudan legesi al-majdhub ti gba idanimọ ninu ìtàn-akọọlẹ ti àwọn ìwé ara ìlú sudan gẹgẹbi itọpa ninu isọdọtun ti ewì sudanese wọ́n jẹ́wọ́ rẹ̀ pé ó dá ẹgbẹ́ olórin ewì kan sílẹ̀ pẹ̀lú ìbátan rẹ̀ abdalla al tayeb tí ó ṣe ọ̀nà tuntun sí ìṣẹ̀dá ewì yíyọ kúrò nínú ìbílẹ̀ àti àwọn ẹ̀kọ́ ewì líle ilé-ìwé ewì tuntun yii gba àṣà ti ko ni ihamọ àti òmìnira díẹ̀ sii ní ìbámu pẹlú àwọn ìṣe ti àwọn ewì àsìkò
aster gebrekirstos aster afwork gebrekirstos faas twas twas jẹ onimọ-jinlẹ ethiopia ati ọjọgbọn ti agroforestry ni ile-iṣẹ agrofogestry cortaforestry icraf igbesi aye ibẹrẹ ati ẹkọ atunmọ gelekerkos ni a bi ni shire tigray etiopia bi ọmọ akọkọ ti idile ti meje o ni ero ti di dokita ṣugbọn awọn abajade ile-iwe giga rẹ ko le ṣeto rẹ fun iṣẹ naa ati pe o ni lati yan laarin ẹkọ ati igbo ati igbo o yan igbẹhin o gba pe ale-jinlẹ ti imọ-jinlẹ ninu igbo lati ile-ẹkọ giga haramaya o duro si ile-ẹkọ giga hamara bi oluranlọwọ ile-iwe ile-iwe giga lẹsẹkẹsẹ ṣaaju ki o to bori pataki ti imọ ati iwadi 1996-1998 o mu ipo lecturi kan ni kọlẹji wondo geneet ti igbo ile-ẹkọ giga hawassassa a fun ni iṣẹ paṣipaarọ ọlọpa jaman daad sikolashipu lati ṣe dokita kan ti imọ-jinlẹ ni ile-ẹkọ giga ti ile-ẹkọ giga ni germany 2001-2005 lẹhin phd rẹ o darapọ mọ bi oniwadi poweddoctoral ni ile-iṣẹ biophysics ati ile-ẹkọ giga tovyya ati ganmany 2009-2011 iṣẹ ati iwadi gẹgẹbi onimọ-jinlẹ dendrochronology o ṣe agbekalẹ yàrá dendrochronology ni etiopia ni ọdun 2009 yàrá dendrochronology ni wondo genet college of forestry and natural resources ni ọdun 2010 ati ile-iyẹwu dendrochronology ti agbaye agroforestry ni kenya ni ọdun 2013 iwadi rẹ ti o fojusi lori ọjọ-alẹ iyipada oju-aye ati igbo awujọ gabrekirstos jẹ ọjọgbọn ti o wa ni iṣẹ abẹwo ni ile-iṣẹ iṣẹ imọ-oorun ti west ti west community ile-iwe fun ile-iwe ikọkọ kalada ti ayikacipsem o ni sìn bio ti ile-iṣẹ ti ile-ẹkọ giga ti committey ti ile-ẹkọ giga ati igbakeji alakoso ti iufrro iṣẹ ṣiṣe ati igbimọ idanwo ẹri ẹri imọ-jinlẹ16 awọn ẹbun ati idanimọ o ti di ẹlẹgbẹ ti ile-ẹkọ giga ti ile-iwe afirika ni ọdun 2017 ẹlẹgbẹ agbaye ti ile-ẹkọ giga ni ọdun 2021 ati ẹlẹgbẹ ti ile-ẹkọ giga ti awọn imọ-ẹkọ igi ni 2021 ni ọdun 2014 o fun un ni aami eye afefe afirika fun iwadi didara ni iyipada afefe ati idinku o tun jẹ winner ti 2019 special eye fun ilẹ breaking science awọn alamọdaju ọdọmọde jakejado afirika ati awọn obirin ni awọn idije imọ-jinlẹ ti a ṣeto nipasẹ ile-iṣẹ imọ-ẹrọ fun agricultural and rural cooperation acp-eu cta awọn ikẹkọ afihan imọ-ẹrọ afirika atps alliance fun iyika green ni afirika agra apejọ fun iwadi ogbin ni afirika fara apejọ awọn ile-ẹkọ giga agbegbe fun ikole agbara ni iṣẹ-ogbin ruforum ati ajọṣepọ tuntun fun idagbasoke afirika nepad
annona nutans annona nutans jẹ́ ẹ̀yà ti ọgbin nínú ìdílé annonaceae ó jẹ́ abínibí sí argentina bolivia brazil àti paraguay robert elias fries onímọ̀-jinlẹ̀ ará ìlú sweden tí o kọ́kọ́ ṣàpèjúwe ẹ̀dá náà ni ìpílẹ̀ṣẹẹ̀ sọ orúkọ rẹ̀ lẹ́hìn àwọn peduncles recurved èyítí ó fún àwọn òdodo ní nodding </link> ni latin irisi àpèjúwe rẹ̀ ó jẹ́ igbó ní gíga àwọn ẹ̀ka rẹ̀ ní àwọn lentil aláwọ̀ àwọ̀ búrẹ́dì membranous rẹ̀ àwọn ewé ofali jẹ́ 3-5 nípasẹ 25-32 centimeters pẹlú apex tí ó parí ní ààyè kékeré lójijì àwọn ewé kò ní irun lórí òkè wọn àti ní ìsàlẹ̀ wọn àyàfi lẹ́gbẹ̀ẹ́ àárín àti àwọn iṣọn nígbàtí ó jẹ́ ọdò àwọn ewé náà ni àwọn iṣọn kejì 10 ti ń jáde láti ẹgbẹ́ kọ̀ọ̀kan ti àárín àwọn petioles rẹ̀ jẹ́ milimita 2 gígùn àti pé ó ní ihò ní ẹgbẹ́ òkè wọn àwọn peduncles tí o tún padà jẹ́ gígùn 25-4 centimeters àfikún- axillary àti nígbà gbogbo farahàn ní idàkejì ewé kan àwọn peduncles jẹ́ adashe tàbí ní méjì-mèjì àwọn peduncles ní bract tí a bò ni àwọn irun awọ ipata ní ìpìlẹ̀ wọn àti òmìíràn ní ààyè àárín wọn àwọnsepal rẹ̀ ti wá ní ìṣọ̀kan láti ṣe calyx kan pẹ̀lú àwọn lobes onigun mẹ́ta tí ó wà sí ààyè kan ide òde ti calyx wà ní àwọn irun siliki tí ó ní àwọ̀ ìpáta àwọn petals rẹ̀ ti wà ní iṣọkan láti ṣé corolla kan 15-23 centimeters ní ìwọ̀n ìlà òpin tí ó ní àwọn lobes gbòòrò 3 tí ó pààrọ̀ pẹ̀lú àwọn lobes dín 3 ojú ìta ti corolla ti wà ní bò ní àwọn irun tí ó ní awọ-ipata dáradára corolla jẹ́ ofeefee sí àwọ̀ ocher pẹ̀lú àwọn ààyè eléyi ti inú àwọn stamen rẹ̀ jẹ́ 18-22 millimeters gígùn pẹ̀lú àwọn filamenti alapin àsopọ̀ tí ó wà láàrin àwọn lobes tí anther ti gbòòrò síi láti ṣe fìlà kan àwọn òdodo rẹ̀ ni àwọn carpels púpọ tí ó jẹ́ gynoecium tí ó ní àpẹrẹ konu àwọn ovaries tí ó ní apá 4 tí ó ní ìrísí prism jẹ́ 09-1 millimeters gígùn ẹran ara rẹ̀ àwọn aza onígùn jẹ́ 09-1 millimeters gígùn àti fòpin sí ni àwọn àbùkù ovoid àwọn àṣà ìta tí ó wà ní bò ní àwọn irun glandular tí ó dára àwọn èso ọsàn tí ó dàgbà jẹ́ 5 centimeters ní ìwọ̀n ìlà òpin àti 7 centimita gígùn ìsèdálè ibisí eruku adodo ti annona nutans ti wà ní ta bí tetrads yẹ pínpín àti ibùgbé ó ti ṣe àkíyèsí dàgbà ní àwọn ààyè àwọn pẹ̀tẹlẹ iyanrìn àti àwọn àfonífojì a ṣe àpèjúwe rẹ̀ bí jíjẹ ní ọdún 1914 nípasẹ onímọ̀-jinlẹ̀ amẹ́ríkà william edwin safford àwọn èso ti egan èso tuntun ti ròyìn bí lílò bí orísun oúnjẹ ní ìlú brazil
apricot apricot je eso tabi igi ti o nso eso órí eya orisirisi lati inu genus prunus nigbagbogbo apricot wa lati eya p armeniacasugbon eso ọrịsi eya ninu prunus sect armeniaca le je apricots etymology apricot koko farahan ni ede geesi ni 16th orudun gegebi abrecock lati middle french aubercot tabi nigbamii abricot lati spanish albaricoque ati catalan albercoc nigbamiran lati arabic الْبَرْقُوق al-barqūq the plums lati giriki byzantine greek βερικοκκίᾱ berikokkíā apricot tree afayo lati inu giriki to ti pe πραικόκιον praikókion apricot lati latin persica peach praecocia praecoquus early ripening
annona paludosa annona paludosa jẹ́ ẹ̀yà ti ògbin nínú ìdílé annonaceae ó jẹ́ abínibí si brazil french guiana guyana suriname àti venezuela jean baptiste christophore fusée aublet onímọ̀-oògùn faransé àti onímọ̀-jinlẹ̀ tí o kọ́kọ́ ṣàpèjúwe ẹ̀dá náà ni ìpílẹṣẹ̀ sọ orúkọ rẹ̀ lẹyìn swampy </link> ni latin ibùgbé àpèjúwe ó jẹ́ igbó tí ó dé 12-15 mita ní gíga àwọn ẹ̀ka rẹ̀ ni ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn lentil brown ina oblong àwọn ewé membranous jẹ́ 16-20 nípasẹ 6-75 centimeters àti pé ó wà sí ààyè kan ní ìparí wọn àwọn ewé tí ó dàgbà kò ní irun lórí dàda aláwọ̀ ewé wọn ṣùgbọ́n ní àwọn irun àwọ̀ ìpáta woolly lórí àwọn ipele ti ìsàlẹ̀ pupa wọn àwọn ewé náà ni àwọn iṣọn keji 18-20 tí ó jáde láti ẹgbẹ́ kọ̀ọ̀kan tí àwọn agbedeméjì wọn àwọn petioles rẹ̀ jẹ́ 5 nípasẹ 3 millimeters tí a bò ní ìwúwo ní àwọn irun irun-agutan tí wọn sì ní iho lórí òkè wọn àwọn òdodo rẹ̀ wà lórí àwọn peduncles gígùn 10-15 millimeter tí ó wáyé nìkan tàbí ní àwọn orísìí àwọn peduncles ti wà ní bò ni àwọn irun wooly àti kí o ní bracteole ní ìpìlẹ wọn àti ààyè àárín àwọn sepal rẹ̀ ti wà ní ìṣọ̀kan láti ṣé calyx kan pẹ̀lú àwọn lobes onígùn mẹ́ta mẹ́ta tí ó jẹ́ 10 nípasẹ 10 milimita tí ó wà sí ààyè títẹ̀ àwọn ojú ìta tí àwọn sepals ti wà ní bò ní àwọn irun irun-agutan tí ó ní àwọ̀ ìpáta àwọn òdodo rẹ̀ ni àwọn petals 6 tí a ṣètò sí àwọn orí ìlà méjì ti 3 àwọn nípọn ofali àwọn petals ita ni awọn ala ti o fi ọwọ kan ṣugbọn ko ni iṣọkan awọn petals ita jẹ 15-18 nipasẹ 15 millimeters ni oke ti aarin ati pe a bo ni awọn irun grẹy daradara awọn petals inu tinrin jẹ 14-15 nipasẹ milimita 6 ati idakeji pẹlu awọn petals ita awọn petals inu jẹ concave ati ti a bo lori awọn aaye mejeeji pẹlu awọn irun irun grẹy dáradára àwọn òdodo rẹ̀ ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn stamens tí ó jẹ́ 28-3 millimeters gígùn àwọn velvety àsopọ tí ó so àwọn lobes ti anthers fọ́ọ̀mù kan fìlà lórí òkè ti àwọn stamens àwọn òdodo rẹ̀ ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn carpels ogbo rẹ̀ ófálì èso pupa jẹ́ 6 nípasẹ 4 centimeters àti tí a bò ní ẹran-ara àwọn àsọtẹ́lẹ̀ tókasí gbòòrò rẹ dán àwọn irúgbìn ófálì jẹ́ 8 nípasẹ 4 millimeters pẹ̀lú caruncle olókìkí ní ìpìlẹ̀ wọn ìsèdálè ibisí erúkú adodo ti annona paludosa ti wà ní ta bi tetrads yẹ ìbùgbé àti pínpín ó dàgbà ní àwọn aláwọ̀ ewé gbígbẹ nlò ó jẹ́ ijabọ nípasẹ onímọ̀-jinlẹ̀ amẹ́ríkà àti onímọ̀-jinlẹ̀ edward lewis sturtevant ní ọdún 1919 láti ní àwọn èso tí ó jẹun sísànra àti ofeefee
sara ibrahim abdelgalil sara ibrahim abdelgalil arabic </link> jẹ dokita kan ti o da lori uk ati alagbawi ijọba tiwantiwa ti o ni ipa ninu awọn ipilẹṣẹ ajeji ti sudan ọmọ ẹgbẹ kan ti awọn onisegun ti sudan fun awọn ẹtọ eda eniyan o tẹnumọ aabo ọmọde o si ṣe alabapin ni itara lakoko awọn ehonu ara ilu sudan 20182019 ati lodi si ifipabalẹ ologun ti ọdun 2021 gẹgẹbi agbẹnusọ fun ẹgbẹ awọn akosemose sudanese igbesiaye sara ibrahim abdelgalil ni a bi si ibrahim hassan abdelgalil olukọ ọjọgbọn ti ọrọ-aje ni university of khartoum ati ọmọ ẹgbẹ ti democratic unionist party ti o ku ni ọjọ 14 oṣu kẹwa ọdun 2018 o gboye gboye pẹlu apon ti oogun apon ti iṣẹ abẹ lati ile-ẹkọ giga ti khartoum ni ọdun 1998 sara note 1 gbe lọ si united kindgom ni 2001 o si pari masters ni tropical paediatrics and child health liverpool school of tropical medicine ni 2002 o jẹ ẹlẹgbẹ ti royal college of paediatrics and child health o jẹ oludamọran itọju ọmọde ni nhs england lati ọdun 2003 ni ile-iwosan norfolk ati norwich university olukọ ẹlẹgbẹ ni ile- ẹkọ giga st lori awọn eniyan ti o ni ipalara ati awọn ọmọde a mọ̀ ọ́ sí gẹ́gẹ́ bí akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ ìbáṣepọ̀ àwọn ará ilẹ̀ òkèèrè láti ọ̀dọ̀ european union diaspora forum sara jẹ ọmọ ẹgbẹ ti awọn onisegun ti sudan fun eto eda eniyan o si dojukọ aabo ọmọde ni ipo ti o nija ti sudan sara jẹ alaga ti ẹgbẹ awọn onisegun sudan ẹka uk laarin ọdun 2017 ati 2020 ati agbẹnusọ fun ẹgbẹ awọn akosemose sudanese ẹgbẹ ẹgbẹ iṣowo ti o gba ipa pataki ni ọdun 2018-2019 awọn ikede ara ilu sudan lodi si ijọba omar al-bashir lakoko ọdun 2019 lakoko awọn ehonu o tẹnumọ si al jazeera pe “awọn eniyan ti o wa ni opopona n ṣe atako nitori epo ati akara wọn n ṣe ikede nitori ikuna gbogbogbo ti gbogbo eto ” ṣaaju ogun sudan ọdun 2023 o ṣe ipa kan ninu ikojọpọ atilẹyin lodi si ifipabanilopo ologun 25 oṣu kẹwa ọdun 2021 ati iwa-ipa ipinlẹ lori awọn alainitelorun alaafia nigba ogun sara sọ pe awọn onisegun kii yoo gba ẹgbẹ ni eyikeyi ija ogun wọn n ṣiṣẹ takuntakun lati gba awọn ẹmi là o nṣe iṣẹ bi oludamọran fun ile-iṣẹ awujọ shabaka o si ṣe alabapin si ṣiṣe aworan agbaye ti ara ilu sudan fun iranlọwọ omoniyan ati idasile ẹgbẹ iṣakojọpọ idaamu oludasile ti eto eto ijọba ni oke okeere ngo kan ni sudan sara kọ awọn ọdọ lori awọn ilana iṣakoso fun ijọba tiwantiwa ati awọn ẹtọ eniyan
banana melon ogede elegede jẹ iru heirloom elegede ni genus cucumis ti o wa lati bi igba 1880 ni ilẹ united states àpèjúwe o wọn ati iwọn ni ipari orúkọ rẹ wà láti elongated rẹ apẹrẹ tọkasi ati awọ ofeefeeti o se iranti ogede kàn bakanna bi orun ogede ti o lagbara eran rirọ re je awọ salmoni ati pe a sọ pé o ni adun ti o dun púpọ o je orisirisi olokiki ni opin orundun 19th ti james j h gregory se àkíyèsí bi fifamora àkíyèsí púpọ ni awọn ere iṣẹ ogbin wiwa eso ogbin náà wà ní gbogbo orisirisi ayelujara
garcinia cowa garcinia cowa ti a mọ si eso kowa tabi mangosteen cowa jẹ ohun ọgbin ti o ti wa nigba lailai o jẹ eso aláwọ̀ ewe asia india bangladesh myanmar malaysia vietnam laos cambodia ati guusu iwo oorun china igi náà ti wa ni ikore lati inu igbẹ fún àwọn eso ati awọn ewe yi o jeunti a lọ ní agbègbè àwọn òdodo fẹ ofeefee ako ati abo awọn ododo ti yapa a ti mọ bí agbègbè bi kau thekera কাও থেকেৰা in assamese kowa ni bengali ati malayalam kau ni manipuri lilo onjẹ wiwa eso naa le jẹ ni aise ati pe o ni adun kikan o ti wa ni lo ninu curries bi a tamarind-bi adun bi daradara bi a lilo fun ṣiṣe pickles o le ṣe si awọn ege ati sisun-oorun bi ọna lati tọju rẹ awọn ewe rẹ tun le jinna ati jẹun ogun ènìyàn thailand garcinia cowa ti lo ni oogun eniyan agbegbe epo igi bi antipyretic ati antimicrobial latex bi antipuretic ati awọn eso ati awọn ewe lati mu ilọsiwaju ẹjẹ pọ si bi ohun expectorant fun ikọ ati indigestion ati ki o kan laxative wọ́n gbà gbọ́ pé àwọn gbòǹgbò náà máa ń tu ibà sílẹ̀ nígbà tó sì wà ní ìlà oòrùn íńdíà wọ́n ti lo àwọn ege èso náà tí oòrùn gbẹ gẹ́gẹ́ bí ìtọ́jú fún ẹ̀je ogun ti o nkoju iba awọn ijinlẹ ti rii pe epo igi naa ni awọn xanthones marun pẹlu awọn ohun-ini egboogi-iba ni fitiro lodi si plasmodium falciparum dyes ati resini wọ́n tún máa ń lo èèpo náà láti fi ṣe àwọ̀ àwọ̀ ofeefee kan fún aṣọ resini gomu ni a lo ninu awọn varnishes
gaya melon gaya melon ti a tun mo si ivory gaya snowball sweet snowball ghost dinosaur dinosaur egg snow leopard matice matisse sugar baby ati silver star melons je kékeré sí irúgbìn oyin ti iwọn alabode ni idagbasoke ni akọkọ ni japan ati korea ati ni bayi dagba ni china mexico gúsù california ati south america àpèjúwe rind je tinrin púpọ àti pé o je ehin erin ni awo pẹlu sisan alawo ewe ati eran inu inu jẹ funfun won ri roboto ni apẹrẹ ati pe o le jẹ oblong diẹ die ara rẹ jẹ sisanra ati rirọ sí àárín ṣugbọn crispier sí ònà rind a ti ṣe àpèjúwe rẹ lati ni ìwọnbaadun didun pẹlu awọn akọsilẹ ododo o dara julọ ni iwọn otutu yara ati awọn melon ti a ti ge yóò dúró dara ninu firiji fún ọjọ marun wiwa o wa lati opin orisun omi sí ibẹrẹ ooru ati pe o wa ni opolopo awọn ọja agbe ati awọn ọja àsìá ni california ati pe o wa lẹhin nitori awọ ailegbe rẹ o tun wa ni awọn ọja nla ni australialaarin awọn orilẹ-ede miiran
ọkọ ofurufu pan am 914 ofurufu pan am 914 jẹ irokuro ti o sọ pe douglas dc-4 kan parẹ lẹhin igbati o ti lọ ni ọdun 1955 ati pe o tun balẹ lẹẹkansi ni ọdun mẹta lẹhinna itan naa ti jẹ olokiki lori intanẹẹti ti o ṣe ifihan lori awọn ikanni bii imọlẹ imọlẹ ìtàn ọrọ aṣiwadi naa sọ pe pan am douglas dc-4 pẹlu awọn arinrin-ajo 57 ati awọn ọmọ ẹgbẹ 6 ti sọnu laisi itọpa kan lori ọkọ ofurufu lati ilu new york si miami ni oṣu keje ọjọ 2 ọdun 1955 lẹhin ọdun 30 37 ni diẹ ninu awọn orisun a tun rii ọkọ ofurufu naa nitosi caracas lẹhin ibalẹ ni papa ọkọ ofurufu nibẹ ọkọ ofurufu naa tun gbera lẹẹkansi ati nikẹhin gbele si ibi atilẹba rẹ ni miami fidio youtube ti ọdun 2019 ti ọran naa ti wo awọn miliọnu awọn akoko ni awọn apejọ intanẹẹti akiyesi wa laarin awọn ohun miiran bi boya o ti jẹ irin-ajo nipasẹ akoko nipasẹ wormhole kan ọpọlọpọ awọn oluṣayẹwo otitọ </link> ti fihan pe eyi jẹ irokuro lati irohin agbaye osẹ iwe iroyin ti a mọ fun awọn itan-akọọlẹ ti a ṣe ti a tẹjade ni igba mẹta 1985 1993 ati 1999 aworan ti a fi ẹsun ti ọkọ ofurufu naa jẹ fọto ti twa trans world airlines dc-4 aworan ti ẹlẹri ti a fi ẹsun naa olutọju ọkọ oju-ofurufu ti venezuelan ṣe afihan awọn eniyan oriṣiriṣi ninu awọn oriṣiriṣi awọn nkan ti irohin agbaye ọsẹ pẹlupẹlu ko si awọn orisun imusin ti isẹlẹ naa boya ninu atẹjade tabi ni awọn ijabọ ijamba ọkọ ofurufu ti ilu aeronautics pẹlupẹlu ko si itọkasi ni eyikeyi awọn akojọ iṣelọpọ kikun fun dc-4 pe iru iṣẹlẹ kan waye lori eyikeyi awọn ẹrọ 1244 ti iru ti a ṣe pẹlu pan am ere telifisonu ni 2018 jara manifest han lori nbc olugbohunsafefe amẹrika itan ti o wa ninu jara naa ni atilẹyin nipasẹ isẹlẹ ẹsun naa